< Leviticus 4 >
Hagi Ra Anumzamo'a Mosesena asamino,
2 “Sọ fún àwọn ọmọ Israẹli pé, ‘Bí ẹnìkan bá ṣẹ̀ láìmọ̀, tí ó ṣe ohun tí kò yẹ kó ṣe sí ọ̀kan nínú àwọn òfin Olúwa.
Mago vahe'mo'ma mago'azama hanifima, ana hugahuema huno ontahi'neno Ra Anumzamo'ma osihoma huno'ma hu'neazama hania kumimofonkura amanage hunka zamasamio.
3 “‘Bí àlùfáà tí a fi òróró yàn bá ṣẹ̀, tí ó sì mú ẹ̀bi wá sórí àwọn ènìyàn, ó gbọdọ̀ mú ọmọ akọ màlúù tí kò lábùkù wá fún Olúwa gẹ́gẹ́ bí ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀ fún ẹ̀ṣẹ̀ tí ó ṣẹ̀.
Ugagota pristi ne'mo'ma kumi'ma haniana, miko vahe'mokizmi zamazeri haviza hugahie. Ana hugahiankino nagra mago agaho ve bulimakao afu afuhe afahe'ma osu'nesia avreno, agrama hu'nenia kumitera kumi ofa hugahie.
4 Kí ó mú ọ̀dọ́ màlúù wá síwájú Olúwa ní ẹnu-ọ̀nà àgọ́ ìpàdé. Kí ó gbé ọwọ́ rẹ̀ lé e lórí, kí ó sì pa á níwájú Olúwa.
Hagi ana bulimakao afura avreno atruhu seli nomofo ufre kafante Ra Anumzamofo avuga ome anteno, azana asenire anteteno, anankena akafrigahie.
5 Kí àlùfáà tí a fi òróró yàn mú díẹ̀ nínú ẹ̀jẹ̀ akọ màlúù, kí ó sì gbé e lọ sínú àgọ́ ìpàdé.
Anama hutena ugagota pristi ne'mo mago'a korana erino atruhu seli nompi ufregahie.
6 Kí ó ti ìka bọ inú ẹ̀jẹ̀ náà kí ó sì wọ́n díẹ̀ nínú rẹ̀ ní ẹ̀ẹ̀méje níwájú Olúwa, níwájú aṣọ títa ibi mímọ́.
Hagi ana korampi azankoa reteno, Ra Anumzamofo avuga hunaragintegeno ruotage'ma hu'nea tavravemofo avuga, 7ni'a zupa rutri tri hugahie.
7 Àlùfáà yóò tún mú díẹ̀ nínú ẹ̀jẹ̀ náà sórí ìwo pẹpẹ tùràrí tó wà níwájú Olúwa nínú àgọ́ ìpàdé. Kí ó da gbogbo ẹ̀jẹ̀ akọ màlúù tókù sí ìsàlẹ̀ pẹpẹ ẹbọ sísun ní ẹnu-ọ̀nà àgọ́ ìpàdé.
Hagi ana pristi ne'mo'a, mago'a korana tagino atrumahu seli nompi Ra Anumzamofo avuga mnanentake'za kresramana vu itamofo pazivetaminte ome frentegahie. Hagi mago'a mesia korana, atru'ma hu seli nomofo avuga me'nea kresramana vu itamofo agafi miko tagi atregahie.
8 Kí ó yọ gbogbo ọ̀rá tí ń bẹ nínú akọ màlúù ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀ náà ọ̀rá tí ó bo nǹkan inú àti gbogbo ohun tó so mọ́ wọn.
Hagi kumite'ma ofama hunaku'ma hania bulimakaomofona mika afovane, arimpama eri anovazi'nea afova'ane,
9 Kíndìnrín méjèèjì pẹ̀lú ọ̀rá wọn tí ń bẹ lẹ́bàá ìhà àti ọ̀rá tí ó bo ẹ̀dọ̀, kí ó yọ ọ́ pẹ̀lú kíndìnrín.
tarega kreso'ane, eri anoma vazi'nea afovane asumnane, ana mika kreso'anena eri tagatitregahie.
10 Gẹ́gẹ́ bí a ṣe ń yọ ọ̀rá kúrò lára màlúù tí a fi rú ẹbọ àlàáfíà; àlùfáà yóò sì sun wọ́n lórí pẹpẹ ẹbọ sísun.
Ana huteno bulimakao afovareti'ma arimpa fru ofama kresramna neviankna huno ugagota Pristi ne'mo'a tevefi kre fanene hu ofama nehaza itare kresramna vugahie.
11 Ṣùgbọ́n awọ màlúù àti gbogbo ara rẹ̀, àti ẹsẹ̀, gbogbo nǹkan inú àti ìgbẹ́ rẹ̀.
Hianagi mika akru'agi, ame'agi amumazina'ane, azonane aseni'ane agusu'agese zama'ane,
12 Èyí túmọ̀ sí pé gbogbo ìyókù akọ màlúù náà ni kí ẹ gbé jáde síta lẹ́yìn ibùdó sí ibi tí a sọ di mímọ́ níbi tí à ń da eérú sí, kí ẹ sì sun wọ́n lórí iná igi, níbi eérú tí a kójọ.
maka erino kuma'mofo fegi'a agruma hu'nea kumapi tanefa'ma ome netrazafi, teve hanavazino kregahie.
13 “‘Bí gbogbo àpapọ̀ ènìyàn Israẹli bá ṣèèṣì ṣẹ̀, tí wọ́n sì ṣe ohun tí kò yẹ kí wọ́n ṣe sí ọ̀kan nínú àwọn òfin Olúwa, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé àpapọ̀ ènìyàn náà kò mọ̀ sí ọ̀rọ̀ náà, wọ́n jẹ̀bi.
Mika Israeli vahe'mo'zama Ra Anumzamofo kemo'ma i'oma huno'ma hu'nesia zama mago'azama hanaregama hantagama hu'za hanu'za kumire hu'za ontahisazanagi, zamagra kumi hugahaze.
14 Nígbà tí wọ́n bá mọ̀, gbogbo ìjọ ènìyàn yóò mú akọ màlúù wá sí àgọ́ ìpàdé gẹ́gẹ́ bí ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀.
Zamagrama antahisazama kumi hu'nonema hanu'za, mago ve agaho bulimakao afu avre'za kumizamiguma kresramana vu'zana, Anumzanema atru'mahu seli nomofo avuga ome anteho.
15 Kí àwọn àgbàgbà ìjọ Israẹli gbé ọwọ́ lórí akọ ọmọ màlúù náà níwájú Olúwa.
Hagi kva vahe'zmimo'za ana bulimakao afu'mofo asenire zamazana antetenageno, Ra Anumzamofo avuga ana bulimakaona anankena akafriho.
16 Kí àlùfáà tí a fi òróró yàn sì mú díẹ̀ lára ẹ̀jẹ̀ akọ ọmọ màlúù náà wá sínú àgọ́ ìpàdé.
Hagi ana hutesageno ugagota pristi ne'mo korama'a erino atrumahu seli nompi ufreno,
17 Kí ó ti ìka rẹ̀ bọ inú ẹ̀jẹ̀ náà kí ó sì wọn ní ẹ̀ẹ̀méje níwájú Olúwa níbi aṣọ títa ẹnu-ọ̀nà.
azankoa ana korampi reteno, tavaravema Ra Anumzamofo avugama hantintegeno me'nerega 7ni'a zupa rutri tri hugahie.
18 Kí ó sì mú díẹ̀ nínú ẹ̀jẹ̀ náà sórí ìwo pẹpẹ tó wà níwájú Olúwa nínú àgọ́ ìpàdé. Ìyókù ẹ̀jẹ̀ náà ni kí ó dà sí ìsàlẹ̀ pẹpẹ ẹbọ sísun ní ẹnu-ọ̀nà àgọ́ ìpàdé.
Hagi ana pristi ne'mo'a, mago'a korana tagino atrumahu seli nompi Ra Anumzamofo avuga mnanentake'za kresramana vu itamofo pazivetaminte ome frentegahie. Hagi mesia korana, atrumahu seli nomofo avugama me'nea kresramna vu itamofo agafi miko tagitregahie.
19 Kí ó yọ gbogbo ọ̀rá kúrò lára rẹ̀, kí ó sì sun ún lórí pẹpẹ.
Hagi agra miko afova'a tagatino kresramana vu itare negreno,
20 Kí ó sì ṣe akọ ọmọ màlúù yìí gẹ́gẹ́ bí ó ṣe ṣe akọ màlúù tó wà fún ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀. Báyìí ni àlùfáà yóò ṣe ṣe ètùtù fún wọn, á ó sì dáríjì wọ́n.
kumi'mofo ofama hu'neaza huno, ugagota pristi ne'mo ana ve bulimakao erino, mika vahe'mokizmi kumizmimofo nona huno kresramna vanigeno, Ra Anumzamo'a kumizmia atrezmantegahie.
21 Lẹ́yìn náà ni yóò sun màlúù yìí lẹ́yìn ibùdó, yóò sì sun ún gẹ́gẹ́ bó ṣe sun màlúù àkọ́kọ́. Èyí ni ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀ fún gbogbo ìjọ ènìyàn Israẹli.
Anantera ana bulimakaona erino kumamofo fegi'a ese bulimakaoma hu'neaza huno ome kregahie. E'i mika vahe'mokizmi kumi atrezmante ofe huno kresramana vugahie.
22 “‘Bí olórí kan bá ṣèèṣì ṣẹ̀ láìmọ̀ tí ó sì ṣe ohun tí kò yẹ kí ó ṣe sí ọ̀kan nínú àwọn òfin Olúwa Ọlọ́run rẹ̀, ó jẹ̀bi.
Hagi Israeli kva vahe'mo mago'azama hanafima hantga huno Ra Anumzamo'ma osuoma hu'nea zama e'i kumire huno ontahi'nenoma hanuno'a, kumi hugahie.
23 Nígbà tí a bá sì sọ ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀ fún un, ó gbọdọ̀ mú akọ ewúrẹ́ tí kò ní àbùkù wá gẹ́gẹ́ bí ẹbọ rẹ̀.
Hagi kumi hu'noe huno'ma antahisuno'a, kumi'aguma kresramana vu'zana ve meme afu afuhe afahe osu'nenia avreno ofama hu'zana vugahie.
24 Kí ó gbé ọwọ́ rẹ̀ lórí ewúrẹ́ náà, kí ó sì pa á níbi tí wọ́n ti ń pa ẹran ẹbọ sísun níwájú Olúwa. Ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀ ni.
Ana ve meme afu'mofo asenire azana anteteno, Ra Anumzamofo avugama me'nea kresramana vu itamofo avuga, anankena akafrigahie. E'i kumi'ma hu'nea zamofonte ofa hugahie.
25 Lẹ́yìn èyí, kí àlùfáà ti ìka rẹ̀ bọ inú ẹ̀jẹ̀ ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀ náà, kí ó fi sí orí ìwo pẹpẹ ẹbọ sísun, kí ó sì da ẹ̀jẹ̀ yòókù sí ìsàlẹ̀ pẹpẹ.
Hagi kumite kresramana vu mememofo korana pristi ne'mo'a azankoreti reno Ra Anumzamofo avuga kresramana vu itare'ma me'nea pazivete ome frentegahie. Hagi mesia korana ana kresramna vu itamofo agafi miko tagitregahie.
26 Kí ó sun gbogbo ọ̀rá rẹ̀ lórí pẹpẹ bí ó ṣe sun ọ̀rá ọrẹ àlàáfíà. Báyìí ní àlùfáà yóò ṣe ètùtù fún ẹ̀ṣẹ̀ ọkùnrin náà, a ó sì dáríjì í.
Arimpa fru ofama kresramna vu'neankna huno afova'a miko kre vagareno. E'ina'ma pristi ne'mo'ma hanuno'a, ana ne'mofo kumi'mofo nonahina kumi'a atrentegahie.
27 “‘Bí ènìyàn nínú àwọn ará ìlú bá ṣèèṣì ṣẹ̀ láìmọ̀ tí ó sì ṣe ohun tí kò yẹ sí ọ̀kan nínú àwọn òfin Olúwa, ó jẹ̀bi.
Ra Anumzamo'ma osihoma huno hu'nea ke'ma Israeli vahepinti'ma mago'mo'ma mago'azama hanafima, e'i kumire huno ontahi'neno ana ke'ma runetagreno, kumira osu'noe huno antahigahianagi agra kumi hugahie.
28 Nígbà tí a bá sọ ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀ fún un, ó gbọdọ̀ mú abo ewúrẹ́ tí kò ní àbùkù wá gẹ́gẹ́ bí ẹbọ fún ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀.
Hagi agrama kumi hu'noema huno antahisuno'a, kumi'ma hu'nea zankura a' meme afuma afuhe afahe'ma osu'nesia avreno eno, kumi'arera ofa eme hugahie.
29 Kí ó gbé ọwọ́ rẹ̀ lórí ewúrẹ́ ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀ náà, kí ó sì pa á níbi ẹbọ sísun.
Hagi anama kumite'ma kresramna vunaku'ma hania meme afu'mofo asenire azana anteteno, kresramna vu afu'ma nehazare anankena akafrigahie.
30 Àlùfáà yóò sì ti ìka rẹ̀ bọ́ ẹ̀jẹ̀ náà, yóò fi sí orí ìwo pẹpẹ ẹbọ sísun, kí ó sì da ìyókù ẹ̀jẹ̀ náà sí ìsàlẹ̀ pẹpẹ.
Pristi vahe'mo'a azankoa ana korampi reteno, kresramana vu itare me'nea pazivetaminte ome frenenteno, mago'a mesia korana kresramana vu itamofo agafi mika tagitregahie.
31 Kí ó yọ gbogbo ọ̀rá ẹran náà gẹ́gẹ́ bó ṣe yọ ọ̀rá ẹran fún ọrẹ àlàáfíà. Kí àlùfáà sì sun ọ̀rá yìí lórí pẹpẹ bí òórùn dídùn sí Olúwa. Báyìí ni àlùfáà yóò ṣe ètùtù fún ẹni náà, a ó sì dáríjì í.
Anantera arimpa fru ofama hu'neankna huno, maka afova tagatitregahie. Ana hanigeno pristi vahe'mo'za ana afova'a eri'za kresranma vu itare vu'za, Ra Anumzamofonte ome Kresramana vanageno, knare sramna nentahino muse hugahie. E'ina'ma pristi ne'mo'ma hanigeno'a, ana ne'mofo kumi'amofo nona hinkeno, Ra Anumzamo'a kumi'a atrentegahie.
32 “‘Bí ó bá mú ọ̀dọ́-àgùntàn wá gẹ́gẹ́ bí ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀, kí ó mú abo tí kò lábùkù.
Hianagi kumi'mofo ofama hunaku'ma sipisipi afu'ma avreno'ma esuno'a, a' sipisipi afu'ma afuhe afahe'ma osu'nesia su'za avreno eno,
33 Kí ó gbé ọwọ́ rẹ̀ lé e lórí, kí ó sì pa á fún ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀ níbi tí wọ́n ti ń pa ẹran ẹbọ sísun.
ana sipisipi afu'mofo asenire azana anteteno, kresramna vu ofamahu afu'ma zmanankema nekafrizare, anankena akafrigahie.
34 Àlùfáà yóò sì ti ìka rẹ̀ bọ inú ẹ̀jẹ̀ ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀ náà, yóò sì fi sí orí ìwo pẹpẹ ẹbọ sísun, yóò sì da ìyókù ẹ̀jẹ̀ náà sí ìsàlẹ̀ pẹpẹ.
Pristi ne'mo'a azankore mago'a korana reteno, kresramana vu itare me'nea pazivetaminte ome frenenteno, mesia korana kresramana vu itamofo agafi maka tagitregahie.
35 Kí ó yọ gbogbo ọ̀rá rẹ̀ bó ti yọ ọ̀rá lára ọ̀dọ́-àgùntàn ọrẹ àlàáfíà, àlùfáà yóò sì sun ún ní orí pẹpẹ, lórí ọrẹ tí a fi iná sun sí Olúwa. Báyìí ni àlùfáà yóò ṣe ètùtù fún ẹni náà, nítorí ẹ̀ṣẹ̀ tí ó sẹ̀, a ó sì dáríjì í.
Ana'ma hutenuno'a arimpa fru ofama hu'neankna huno, maka afova tagatitregahie. Ana hanigeno pristi vahe'mo'za ana afova eri'za kresranma vu itare vu'za, Ra Anumzamofonte ome kresramna vuntegahaze. E'ina'ma pristi ne'mo'ma hanigeno'a, anama kumi'ma hu'nea ne'mofo kumi'amofo nona huno krenkeno, Ra Anumzamo'a kumi'a atrentegahie.