< Leviticus 3 >
1 “‘Bí ọrẹ ẹnìkan bá jẹ́ ọrẹ àlàáfíà, tí ó sì mú ẹran wá láti inú agbo màlúù yálà akọ tàbí abo, kí ó mú èyí tí kò ní àbùkù wá síwájú Olúwa.
Birsining sunidighini inaqliq qurbanliqi bolsa, shundaqla kalilardin sunsa, u Perwerdigarning huzurigha béjirim bir erkikini yaki chishisini keltürsun.
2 Kí ó gbé ọwọ́ rẹ̀ lé e lórí, kí ó sì pa á ní ẹnu-ọ̀nà àgọ́ àjọ. Nígbà náà ni àwọn ọmọ Aaroni tí í ṣe àlùfáà yóò wọ́n ẹ̀jẹ̀ ẹran náà yí pẹpẹ ká.
U sunidighan bu haywanning béshigha qolini qoyup, andin uni jamaet chédirining kirish éghizi aldida boghuzlisun. Andin kahinlar bolghan Harunning oghulliri qénini qurban’gahning üsti qismining etrapigha sepsun.
3 Láti ara ọrẹ àlàáfíà ni kí ẹni náà ti mú ẹbọ tí a fi iná sun sí Olúwa, gbogbo ọ̀nà tí ó bo nǹkan inú ẹran náà àti gbogbo ọ̀rá tí ó so mọ́ wọn.
Sun’ghuchi kishi bu inaqliq qurbanliqidin Perwerdigargha atap otta sunulidighan hediye süpitide bir qismini élip béghishlisun, yeni ich qarnini yögep turghan mayni, shundaqla barliq ich méyini élip
4 Kíndìnrín méjèèjì pẹ̀lú ọ̀rá ara rẹ̀ tí ń bẹ lẹ́bàá ìhà rẹ̀, àti gbogbo ọ̀rá tí ó bo ẹ̀dọ̀, kí ó yọ ọ́ jáde pẹ̀lú kíndìnrín.
ikki börekni we ularning üstidiki hemde ikki yanpishidiki mayni ajritip, jigerning börekkiche bolghan chawa méyini késip, élip kelsun.
5 Nígbà náà ni àwọn ọmọ Aaroni yóò sun ún lórí pẹpẹ gẹ́gẹ́ bí ẹbọ sísun tí a fi iná sun, àní òórùn dídùn sí Olúwa.
Harunning oghulliri bolsa bularni qurban’gahning üstige keltürüp ot üstige qoyulghan otunning üstidiki köydürme qurbanliqqa qoshup köydürsun. Bu ot arqiliq sunulidighan, Perwerdigargha xushbuy chiqirilidighan qurbanliq bolidu.
6 “‘Bí ó bá ṣe inú agbo ewúrẹ́ àti àgùntàn ni ó ti mú ọrẹ àlàáfíà wá fún Olúwa kí ó mú akọ tàbí abo tí kò ní àbùkù.
Birsining Perwerdigargha qilidighan inaqliq qurbanliqi üchün sunidighini ushshaq maldin bolsa, undaqta u béjirim bir erkikini yaki chishisini keltürsun.
7 Bí ó bá ṣe pé ọ̀dọ́-àgùntàn ni ó mú, kí ó mú un wá síwájú Olúwa.
Eger uning qurbanliqi qoy bolsa uni Perwerdigarning aldigha keltürüp,
8 Kí ó gbé ọwọ́ rẹ̀ lé e lórí, kí ó sì pa á níwájú àgọ́ ìpàdé, kí àwọn ọmọ Aaroni wọ́n ẹ̀jẹ̀ ẹran náà yí pẹpẹ ká.
qurbanliq qilidighan bu haywanning béshigha qolini qoyup, andin uni jamaet chédirining kirish aghzining aldida boghuzlisun. Andin Harunning oghulliri qénini élip qurban’gahning üsti qismining etrapigha sepsun.
9 Kí o sì mú wá nínú ẹbọ àlàáfíà náà, fún ẹbọ tí a fi iná ṣe sí Olúwa; ọ̀rá rẹ̀ àti gbogbo ìrù rẹ̀ tí ó ní ọ̀rá, òun ni kí o mú kúrò súnmọ́ egungun ẹ̀yìn àti ọ̀rá tí ó bo ìfun lórí; àti gbogbo ọ̀rá tí ń bẹ lára ìfun.
Sun’ghuchi kishi bu inaqliq qurbanliqidin Perwerdigargha atap otta sunulidighan hediye süpitide bir qismini, yeni uning méyini élip béghishlisun, — pütün mayliq quyruqini uning omurtqisigha yéqin yerdin ajritip élip, ich qarnini yögep turghan mayni, shundaqla barliq ich méyini élip,
10 Kíndìnrín méjèèjì pẹ̀lú ọ̀rá tí ń bẹ lẹ́bàá ìhà rẹ̀ àti ọ̀rá tí ó bo ẹ̀dọ̀, kí o yọ ọ́ jáde pẹ̀lú kíndìnrín.
ikki börekni we ularning üstidiki hemde ikki yanpishidiki mayni ajritip, jigerning börekkiche bolghan chawa méyini késip, élip kelsun.
11 Kí àlùfáà sun ún lórí pẹpẹ bí oúnjẹ ọrẹ tí a fi iná sun sí Olúwa.
Kahin bularni qurban’gahning üstide köydürsun; bu otta sunulidighan, Perwerdigargha atalghan taam hediyesi bolidu.
12 “‘Bí ó bá ṣe pé ewúrẹ́ ni ó mú, kí ó mú un wá síwájú Olúwa.
Uning sunidighini öchke bolsa, buni Perwerdigarning huzurigha keltürsun.
13 Kí ó gbé ọwọ́ lé e lórí. Kí ó sì pa á ní iwájú àgọ́ ìpàdé. Nígbà náà ni àwọn ọmọ Aaroni yóò wọ́n ẹ̀jẹ̀ ẹran náà yí pẹpẹ ká.
U qolini uning béshigha qoyup, andin uni jamaet chédirining aldida boghuzlisun. Andin Harunning oghulliri qénini élip qurban’gahning üsti qismining etrapigha sepsun.
14 Lára ọrẹ tó mú wá, kí ó mú ẹbọ sísun fún Olúwa, gbogbo ọ̀rá tí ó bo nǹkan inú rẹ̀ àti ohun gbogbo tó so mọ́ ọn.
Andin sun’ghuchi kishi bu qurbanliqtin Perwerdigargha atap otta sunulidighan hediye süpitide bir qismini élip béghishlisun, yeni ich qarnini yögep turghan mayni, shundaqla barliq ich méyini élip,
15 Kíndìnrín méjèèjì pẹ̀lú ọ̀rá ara rẹ̀ tí ń bẹ lẹ́bàá ìhà rẹ̀ àti ọ̀rá tí ó bo ẹ̀dọ̀, kí ó yọ ọ́ jáde pẹ̀lú kíndìnrín.
ikki börekni we ularning üstidiki hemde ikki yanpishidiki mayni ajritip, jigerning börekkiche bolghan chawa méyini késip, élip kelsun.
16 Kí àlùfáà sun ún lórí pẹpẹ bí oúnjẹ, ọrẹ tí a fi iná sun, ní òórùn dídùn. Gbogbo ọ̀rá rẹ̀ jẹ́ ti Olúwa.
Kahin bularni qurban’gahning üstide köydürsun; bu otta sunulidighan, xushbuy chiqiridighan taam hediyesi bolidu. Mayning hemmisi Perwerdigargha tewedur.
17 “‘Èyí jẹ́ ìlànà láéláé fún àwọn ìran tó ń bọ̀, ní gbogbo ibi tí ẹ bá ń gbé, ẹ kò gbọdọ̀ jẹ ọ̀rá tàbí ẹ̀jẹ̀.’”
Bu herqandaq turar jayinglarda silerge ebediy belgilime bolidu; siler héchqandaq may yaki qan yémeslikinglar kérek.