< Leviticus 27 >
Angraeng mah Mosi taengah,
2 “Sọ fún àwọn ọmọ Israẹli pé, ‘Bí ẹnìkan bá jẹ́ ẹ̀jẹ́ pàtàkì láti ya ènìyàn kan sọ́tọ̀ fún Olúwa nípa sísan iye tí ó tó,
Israel kaminawk khaeah hae tiah thui paeh; nihcae khaeah, Kami maeto mah angmah ih atho kating ah, Angraeng khaeah paek han lokkamhaih sah nahaeloe,
3 kí iye owó ọkùnrin láti ọmọ ogún ọdún sí ọgọ́ta ọdún jẹ́ àádọ́ta òsùwọ̀n ṣékélì fàdákà, gẹ́gẹ́ bí òsùwọ̀n ṣékélì ti ibi mímọ́ Olúwa.
na pakoep o han ih atho loe hae tiah oh; saning pumphaeto hoi saning qui tarukto kaom nongpa loe, hmuenciim ih shekel tahhaih pongah, phoisa shekel qui pangato hoi akrang han oh.
4 Bí ẹni náà bá jẹ obìnrin, kí iye owó rẹ̀ jẹ́ ọgbọ̀n òsùwọ̀n ṣékélì.
Nongpata ah om nahaeloe phoisa qui thumto hoiah akrang tih.
5 Bí ẹni náà bá jẹ́ ọmọ ọdún márùn-ún sí ogún ọdún, kí iye owó rẹ̀ jẹ́ ogún ṣékélì fún ọkùnrin àti òsùwọ̀n ṣékélì mẹ́wàá fún obìnrin.
Saning pangato hoi saning pumphaeto salak ih kami ah om nahaeloe, nongpa to shekel pumphaeto hoiah akrang ueloe, nongpata to shekel hato hoiah akrang tih.
6 Bí ẹni náà bá jẹ́ ọmọ oṣù kan sí ọdún márùn-ún, kí iye owó rẹ̀ jẹ́ òsùwọ̀n ṣékélì fàdákà márùn-ún fún ọkùnrin àti òsùwọ̀n ṣékélì fàdákà mẹ́ta fún obìnrin.
Khrahto hoi saning pangato salak kami ah om nahaeloe, nongpa to shekel pangato hoi akrang ueloe, nongpata to shekel thumto hoiah akrang tih.
7 Bí ẹni náà bá jẹ́ ọmọ ọgọ́ta ọdún àti jù bẹ́ẹ̀ lọ, kí iye owó rẹ̀ jẹ́ òsùwọ̀n ṣékélì mẹ́ẹ̀ẹ́dógún fún ọkùnrin àti òsùwọ̀n ṣékélì mẹ́wàá fún obìnrin.
Saning qui tarukto hoi ranui bang kami ah om nahaeloe, nongpa to shekel hatlai pangato hoiah akrang ueloe, nongpata to shekel hato hoiah akrang tih.
8 Bí ẹnìkan tí ó jẹ́ ẹ̀jẹ́ bá tálákà púpọ̀ dé bi pé kò lè san iye owó náà, kí a mú ẹni náà wá síwájú àlùfáà, àlùfáà yóò sì dá iye owó tí ó lè san lé e gẹ́gẹ́ bí agbára ẹni náà tí ó jẹ́ ẹ̀jẹ́.
Anih loe na khaeh ih atho pongah amtang kue nahaeloe, to kami to qaima khaeah caeh haih ah; qaima mah anih ih atho to khaek tih; lokkamhaih sahkung mah paek thaih ih atho baktih toengah, qaima mah atho to khaek pae tih.
9 “‘Bí ẹ̀jẹ́ tí ó jẹ́ bá jẹ́ ẹranko èyí tí ó jẹ́ ìtẹ́wọ́gbà gẹ́gẹ́ bí ọrẹ fún Olúwa, irú ẹran bẹ́ẹ̀ tí a bá fi fún Olúwa di mímọ́.
Paek han lokkam ih hmuen loe pacah ih moi ah oh moe, Angraeng khaeah tathlang hanah sin nahaeloe, a paek ih hmuen to ciim.
10 Ẹni tí ó jẹ́ ẹ̀jẹ́ náà kò gbọdọ̀ pàrọ̀ ẹran mìíràn, yálà kí ó pàrọ̀ èyí tí ó dára sí èyí tí kò dára tàbí èyí tí kò dára sí èyí tí ó dára. Bí ó bá ṣe bẹ́ẹ̀ ti Olúwa ni ẹranko méjèèjì.
Kahoih maw, kasae maw, moi maeto hoi maeto athlaeng han om ai; moi maeto hoi maeto athlaeng nahaeloe, to moi hoi athlaeng han koeh ih kalah moi maeto loe ciimcai han angaih.
11 Ṣùgbọ́n bí ó bá jẹ́ ẹ̀jẹ́ ní ti ẹranko àìmọ́ tí a fi tọrẹ: èyí tí kò jẹ́ ìtẹ́wọ́gbà bí i ọrẹ fún Olúwa. Kí ọkùnrin náà mú ọrẹ náà lọ fún àlùfáà.
Kaciim ai moi ah om nahaeloe, Angraeng khaeah tathlang han om ai; to pongah moi to khet hanah qaima khaeah caeh haih ah;
12 Kí àlùfáà díye lé e, gẹ́gẹ́ bí ó ti dára tàbí bí ó ti bàjẹ́ sí. Iye owó náà ni kí ó jẹ́.
anih mah kasae kahoih, atho to thui tih; atho loe qaima mah khaeh ih baktih toengah om tih.
13 Bí ẹni náà bá fẹ́ rà á padà, ó gbọdọ̀ san iye owó rẹ̀ àti ìdá ogún iye owó náà láfikún.
Paekkung mah akrang han koeh nahaeloe, khaeh ih atho nuiah pangato thungah maeto thap ueloe akrang tih.
14 “‘Bí ẹnikẹ́ni bá ya ilẹ̀ rẹ̀ sí mímọ́ fún Olúwa: kí àlùfáà kó sọ iye tí yóò san gẹ́gẹ́ bí ilẹ̀ náà ti dára tàbí bàjẹ́ sí, iye owó náà ni kí ó jẹ́.
Kami maeto mah a im to Angraeng khaeah kaciim ah paek han koeh nahaeloe, kahoih maw, ka sae maw, atho loe qaima mah khaeh ih baktih toengah om tih.
15 Bí ẹni tí ó yá ilé náà sí mímọ́ bá fẹ́ rà á padà. Jẹ́ kí ó fi ìdámárùn-ún owó ìdíyelé rẹ̀ kún ún, yóò si jẹ́ tirẹ̀.
To im to ciimsakkung mah akrang koeh nahaeloe, khaeh ih atho nuiah pangato thungah maeto thap ueloe, akrang tih; to pacoengah loe anih ih im ah om tih boeh.
16 “‘Bí ẹnìkan bá sì ya ara ilẹ̀ ìdílé rẹ̀ sí mímọ́ fún Olúwa. Iye tí ó bá jẹ́ ni kí wọ́n ṣètò gẹ́gẹ́ bí iye èso tí a ó fi gbìn ín. Àádọ́ta ṣékélì fàdákà fún òsùwọ̀n homeri irúgbìn barle.
Kami maeto mah a lawk ahap Angraeng khaeah paek nahaeloe, cang nazetto maw akunh, tito khet moe, atho khaeh han oh; barli cang homer maeto naah, atho phoisa shekel qui pangato oh.
17 Bí ó ba ṣe pé ní ọdún ìdásílẹ̀ ni ó ya ilẹ̀ náà sí mímọ́. Iye owó tí wọn sọtẹ́lẹ̀ náà ni kí o san.
Jubili saning thungah a lawk to paek nahaeloe, atho khaeh tangcae baktiah om poe tih.
18 Bí ó bá ya ilẹ̀ náà sí mímọ́ lẹ́yìn ọdún ìdásílẹ̀ kí àlùfáà sọ iye owó tí yóò san fún ọdún tókù kí ọdún ìdásílẹ̀ mìíràn tó pé iye owó tí ó gbọdọ̀ jẹ yóò dínkù.
Toe Jubili pacoengah ciimsak hanah lawk to paek nahaeloe, qaima mah hmabang ih Jubili phak hanah saning nazetto maw angai vop, tito kroek ueloe, khaeh tangcae ih atho to azuk tih.
19 Bí ẹni tí ó ya ilẹ̀ sí mímọ́ bá fẹ́ rà á padà, kí ó san iye owó náà pẹ̀lú àfikún ìdámárùn-ún. Ilẹ̀ náà yóò sì di tirẹ̀.
Ciimsakkung mah angmah ih lawk to akrang let han koeh nahaeloe, khaeh tangcae atho nuiah pangato thungah maeto thap ueloe, akrang tih; to pacoengah loe a lawk ah om let tih boeh.
20 Bí kò bá ra ilẹ̀ náà padà tàbí bí ó bá tà á fún ẹlòmíràn kò le è ri rà padà mọ́.
Toe lawk to akrang let han koeh ai moe, kalah kami khaeah zaw nahaeloe, akrang let thai mak ai boeh.
21 Bí a bá fi ilẹ̀ náà sílẹ̀ ní ọdún ìdásílẹ̀ yóò di mímọ́ gẹ́gẹ́ bí ilẹ̀ tí a fi fún Olúwa. Yóò sì di ohun ìní àlùfáà.
Jubili naah lawk to paek let nahaeloe, Angraeng khaeah paek ih hmuen ah oh baktih toengah, lawk to ciim tih; to lawk to qaimanawk ih hmuen ah om tih.
22 “‘Bí ẹnikẹ́ni bá ya ilẹ̀ tí ó ti rà tí kì í ṣe ilẹ̀ ìdílé rẹ̀ sí mímọ́ fún Olúwa.
Kami maeto mah angmah ih lawk na ai, kalah lawk to qan moe, Angraeng khaeah paek nahaeloe,
23 Kí àlùfáà sọ iye tí ó tọ títí di ọdún ìdásílẹ̀. Kí ọkùnrin náà sì san iye owó náà ní ọjọ́ náà gẹ́gẹ́ bí ohun mímọ́ sí Olúwa.
qaima mah Jubili karoek to khaeh ih atho to kroek ueloe, Angraeng khaeah ciimsakhaih niah atho to paek roep tih.
24 Ní ọdún ìdásílẹ̀ ilẹ̀ náà yóò padà di ti ẹni tí ó ni í, lọ́wọ́ ẹni tí a ti rà á.
Jubili saning phak naah loe, to lawk zaw kami, lawk tawnkung khaeah paek let tih.
25 Gbogbo iye owó wọ̀nyí gbọdọ̀ wà ní ìbámu pẹ̀lú ṣékélì ibi mímọ́, ogún gera.
Khaeh ih atho loe hmuenciim ih shekel tahhaih baktih toengah om ueloe, shekel maeto naah gerah pumphaeto om tih.
26 “‘Kò sí ẹni tí ó gbọdọ̀ ya gbogbo àkọ́bí ẹran sọ́tọ̀. Èyí jẹ́ ti Olúwa nípasẹ̀ òfin àkọ́bí: yálà akọ màlúù ni tàbí àgùntàn, ti Olúwa ni.
Toe Angraeng ih hmuen ah kaom, tapen tangsuek pacah ih moinawk loe mi mah doeh ciimsak hanah tathlang han om ai; maitaw maw, to tih ai boeh loe tuu maw Angraeng ih hmuen ah ni oh.
27 Bí ó bá jẹ́ ọ̀kan nínú àwọn ẹran tí kò mọ́, nígbà náà ni kí ó rà á padà gẹ́gẹ́ bí ìdíyelé rẹ̀, kí ó sì fi ìdámárùn-ún lé e, tàbí bí a kò bá rà á padà kí ẹ tà á gẹ́gẹ́ bí ìdíyelé rẹ̀.
Kaciim ai pacah ih moi loe, na khaeh ih atho baktih toengah akrang ah, khaeh ih atho nuiah pangato thungah maeto thap ah loe akrang ah; akrang han koeh ai nahaeloe, khaeh tangcae atho baktih toengah zaw ah.
28 “‘Ohun tí a bá yà sí mímọ́ pátápátá láti ọwọ́ ẹnikẹ́ni sí Olúwa tàbí ẹranko tàbí ilẹ̀ tí ó jogún, òun kò gbọdọ̀ tà á kí ó rà á padà. Gbogbo ohun ìyàsọ́tọ̀ bẹ́ẹ̀ di mímọ́ jùlọ fún Olúwa.
Toe kami maeto mah tawnh ih kami maw, to tih ai boeh loe moi maw, to tih ai boeh loe lawk maw, Angraeng khaeah lokkam hoi paek ih hmuennawk boih loe, zaw thai mak ai ueloe, akrang doeh akrang let thai mak ai; palungthin boih hoi paek ih hmuen loe Angraeng khaeah kaciim koek hmuen ah oh.
29 “‘Ẹni tí ẹ bá ti yà sọ́tọ̀ fún pípa, ẹnikẹ́ni kò gbọdọ̀ rà á padà, pípa ni kí ẹ pa á.
Kaminawk mataeng doeh, paek tangcae kami loe, akrang let thai ai; hum han ni oh boeh.
30 “‘Gbogbo ìdámẹ́wàá ilẹ̀ náà yálà tí èso ilẹ̀ ni, tàbí tí èso igi, ti Olúwa ni. Mímọ́ ni fún Olúwa.
Lawk ih cang maw, to tih ai boeh loe thingthai qumponawk maw, hato thungah maeto loe Angraeng ih hmuen ah oh, Angraeng ih kaciim hmuen ah oh.
31 Bí ẹnikẹ́ni bá fẹ́ ra ìdámẹ́wàá nǹkan rẹ̀ padà, o gbọdọ̀ fi márùn-ún kún un.
Kami maeto mah hato thungah maeto akrang koeh nahaeloe, khaeh ih atho nuiah pangato thungah maeto thap pacoengah, akrang han oh.
32 Gbogbo ìdámẹ́wàá àgbò àti ẹran ọ̀sìn, àní ìdámẹ́wàá ẹran tó bá kọjá lábẹ́ ọ̀pá darandaran kí ó jẹ́ mímọ́ fún Olúwa.
Tuu maw, to tih ai boeh loe maitaw maw, tuu khawngkung ih cunghet thungah akun moinawk boih, hato thungah maeto loe, Angraeng khaeah kaciim hmuen ah oh.
33 Ènìyàn kò gbọdọ̀ wádìí bóyá ó dára tàbí kò dára, kò sì gbọdọ̀ pààrọ̀ rẹ̀. Bí ó bá pààrọ̀ rẹ̀: àti èyí tí ó pààrọ̀ àti èyí tí ó fi pààrọ̀ ni kí ó jẹ́ mímọ́. Wọn kò gbọdọ̀ rà á padà.’”
Anih mah kasae maw, kahoih maw, qoi mak ai, moi doeh maeto hoi maeto athlaeng mak ai; athlaeng han koeh nahaeloe, paek ih moi hoi athlaeng ih moi to ciim hmaek han oh; akrang doeh akrang thai mak ai, tiah thui paeh, tiah a naa.
34 Àwọn àṣẹ wọ̀nyí ni Olúwa pa fún Mose fún àwọn ọmọ Israẹli ní orí òkè Sinai.
Hae loe Sinai mae ah Israel kaminawk han, Angraeng mah Mosi khaeah paek ih loknawk ah oh.