< Leviticus 21 >

1 Olúwa sọ fún Mose wí pe, “Bá àwọn àlùfáà tí wọ́n jẹ́ ọmọ Aaroni sọ̀rọ̀, kí o sì sọ fún wọn pé, ‘Ẹnikẹ́ni nínú wọn kò gbọdọ̀ sọ ara rẹ̀ di aláìmọ́ nítorí àwọn ènìyàn wọn tí ó kù.
Og HERREN sagde til Moses: Tal til Præsterne, Arons Sønner, og sig til dem: Præsten må ikke gøre sig uren ved Lig blandt sin Slægt,
2 Ṣùgbọ́n bí ó bá ṣe àwọn tí ó súnmọ́ ọn bí ìyá rẹ̀, baba rẹ̀, ọmọ rẹ̀ ọkùnrin tàbí obìnrin, àti arákùnrin rẹ̀.
medmindre det er hans nærmeste kødelige Slægtninge, hans Moder eller Fader, hans Søn eller Datter, hans Broder
3 Tàbí fún arábìnrin rẹ̀ tí kò ì tí ì wọ ilé ọkọ tí ó ń gbé lọ́dọ̀ rẹ̀. Nítorí tí arábìnrin bẹ́ẹ̀, ó lè sọ ara rẹ̀ di aláìmọ́.
eller Søster, for så vidt hun var Jomfru og endnu hørte til hans Familie og ikke var gift; i så Fald må han gøre sig uren ved hende;
4 Nítorí tí ó jẹ́ olórí, òun kò gbọdọ̀ sọ ara rẹ̀ di aláìmọ́, bẹ́ẹ̀ ni kò gbọdọ̀ ba ara rẹ̀ jẹ́ láàrín àwọn ènìyàn rẹ̀.
men han må ikke gøre sig uren ved hende, når hun var gift med en Mand af hans Slægt, og således pådrage sig Vanhelligelse.
5 “‘Àlùfáà kò gbọdọ̀ fá irun orí rẹ̀ bẹ́ẹ̀ ni kò gbọdọ̀ rẹ́ irùngbọ̀n rẹ̀. Kò gbọdọ̀ fi abẹ ya ara rẹ̀ láti fihàn pé òun wà ní ipò ọ̀fọ̀.
De må ikke klippe sig en skaldet Plet på deres Hoved, ikke studse deres Skæg eller gøre Indsnit i deres Legeme.
6 Wọ́n gbọdọ̀ jẹ́ mímọ́ fún Ọlọ́run, kí wọ́n má ba à sọ orúkọ Ọlọ́run wọn di àìmọ́, nítorí pé àwọn ni wọ́n ń fi iná sun ẹbọ sí Olúwa wọn, ti ó jẹ oúnjẹ Ọlọ́run wọn. Nítorí náà wọn gbọdọ̀ jẹ́ mímọ́.
Hellige skal de være for deres Gud og må ikke vanhellige deres Guds Navn, thi de frembærer HERRENs Ildofre, deres Guds Spise; derfor skal de være hellige.
7 “‘Àwọn àlùfáà kò gbọdọ̀ fẹ́ panṣágà tàbí obìnrin tí ó ti fi ọkùnrin ba ara rẹ̀ jẹ́ tàbí obìnrin tí ọkọ rẹ̀ ti kọ̀sílẹ̀ nítorí pé àwọn àlùfáà jẹ́ mímọ́ sí Ọlọ́run wọn.
En Horkvinde og en skændet Kvinde må de ikke ægte; heller ikke en Kvinde, der er forstødt af sin Mand, må de ægte; thi han er helliget sin Gud.
8 Àwọn ènìyàn gbọdọ̀ máa kà wọ́n sí mímọ́, nítorí pé àwọn ni wọ́n ń rú ẹbọ oúnjẹ fún mi. Èmi ni Olúwa, mo jẹ́ mímọ́, mo sì ya àwọn ènìyàn mi sí mímọ́.
Du skal regne ham for hellig, thi han frembærer din Guds Spise; han skal være dig hellig, thi hellig er jeg HERREN, som helliger dem.
9 “‘Bí ọmọbìnrin àlùfáà kan bá fi iṣẹ́ àgbèrè ba ara rẹ̀ jẹ́, ó dójútì baba rẹ̀, iná ni a ó dá sun ún.
Når en Præstedatter vanhelliger sig ved at bedrive Hor, da vanhelliger hun sin Fader; hun skal brændes på Bål,
10 “‘Lẹ́yìn tí a ti fi òróró yan olórí àlùfáà láàrín àwọn arákùnrin rẹ̀, tí a sì ti fi àmì òróró yàn án láti máa wọ aṣọ àlùfáà, ó gbọdọ̀ tọ́jú irun orí rẹ̀, bẹ́ẹ̀ ni kò gbọdọ̀ fa aṣọ rẹ̀ ya láti fihàn pé òun wà ní ipò ọ̀fọ̀.
Den Præst, der er den ypperste blandt sine Brødre, han, over hvis Hoved Salveolien udgydes, og som indsættes ved at iføres Klæderne, må hverken lade sit Hovedhår vokse frit eller sønderrive sine Klæder.
11 Kí ó ma ṣe wọlé tọ òkú lọ, kí ó má ṣe sọ ará rẹ di àìmọ́ nítorí baba tàbí nítorí ìyá rẹ̀.
Han må ikke gå hen til noget som helst Lig, end ikke ved sin Fader eller Moder må han gøre sig uren.
12 Kò gbọdọ̀ kúrò ní ibi mímọ́ Ọlọ́run tàbí kí ó sọ ọ́ di aláìmọ́ torí pé a ti fi ìfòróróyàn Ọlọ́run yà á sí mímọ́. Èmi ni Olúwa.
Han må ikke forlade Helligdommen for ikke at vanhellige sin Guds Helligdom, thi hans Guds Salveolies Vielse er på ham; jeg er HERREN!
13 “‘Ọmọbìnrin tí yóò fẹ́ gbọdọ̀ jẹ́ ẹni tí kò mọ ọkùnrin rí.
Han skal ægte en Kvinde, der er Jomfru;
14 Kò gbọdọ̀ fẹ́ opó tàbí ẹni tí a kọ̀sílẹ̀ tàbí obìnrin tí ó ti fi àgbèrè ba ara rẹ̀ jẹ́, ṣùgbọ́n kí ó fẹ́ obìnrin tí kò mọ ọkùnrin rí, láàrín àwọn ènìyàn rẹ̀.
en Enke, en forstødt, en skændet, en Horkvinde må han ikke ægte, kun en Jomfru af sin Slægt må han tage til Hustru,
15 Kí ó má ba à sọ di aláìmọ́ nínú àwọn ènìyàn rẹ̀. Èmi ni Olúwa tí ó sọ ọ́ di mímọ́.’”
for at han ikke skal vanhellige sit Afkom blandt sin Slægt; thi jeg er HERREN, som helliger ham.
16 Olúwa sì bá Mose sọ̀rọ̀ pé,
HERREN talede fremdeles til Moses og sagde:
17 “Sọ fún Aaroni pé, ‘Ẹnikẹ́ni nínú irú-ọmọ rẹ̀ ní ìran-ìran wọn, tí ó bá ní ààrùn kan, kí ó má ṣe súnmọ́ tòsí láti rú ẹbọ ohun jíjẹ sí Ọlọ́run rẹ̀.
Tal til Aron og sig: Ingen af dit Afkom i de kommende Slægter, som har en Legemsfejl, må træde frem for at frembære sin Guds Spise,
18 Ẹnikẹ́ni tí ó bá ní àbùkù kò gbọdọ̀ súnmọ́ ibi ẹbọ náà. Kò gbọdọ̀ sí afọ́jú tàbí arọ, alábùkù ara tàbí àwọn tí ara wọn kò pé.
det må ingen, som har en Legemsfejl, hverken en blind eller en halt eller en med vansiret Ansigt eller for lang en Legemsdel
19 Kò gbọdọ̀ sí ẹnikẹ́ni yálà ó rọ lápá lẹ́sẹ̀,
eller med Brud på Ben eller Arm
20 tàbí tí ó jẹ́ abuké, tàbí tí ó ya aràrá tàbí tí ó ní àìsàn ojú tàbí tí ó ní egbò tàbí tí a ti yọ nǹkan ọmọkùnrin rẹ̀.
eller en pukkelrygget eller en med Tæring eller en, der har Pletter i Øjnene eller lider af Skab eller Ringorm eller har svulne Testikler.
21 Ẹnikẹ́ni tí ó ní àbùkù nínú irú-ọmọ Aaroni àlùfáà kò gbọdọ̀ súnmọ́ tòsí láti rú ẹbọ tí fi iná sun sí Olúwa. Nítorí pé ó jẹ́ alábùkù, kò gbọdọ̀ súnmọ́ tòsí láti rú ẹbọ àkàrà sí Ọlọ́run rẹ̀.
Af Præsten Arons Efterkommere må ingen, som har en Legemsfejl, nærme sig for at frembære HERRENs Ildofre; han har en Legemsfejl, han må ikke nærme sig for at frembære sin Guds Spise.
22 Ó lè jẹ́ oúnjẹ Ọlọ́run rẹ̀ tàbí èyí tí ó mọ́ jùlọ, ṣùgbọ́n torí pé ó ní àbùkù kò gbọdọ̀ súnmọ́ ibi aṣọ títa tàbí pẹpẹ.
Han må vel spise sin Guds Spise, både det, som er højhelligt, og det, som er helligt,
23 Nípa ṣíṣe bẹ́ẹ̀ yóò ba ibi mímọ́ mi jẹ́ torí pé, Èmi Olúwa ló ti sọ wọ́n di mímọ́.’”
men til Forhænget må han ikke komme, og Alteret må han ikke nærme sig, thi han har en Legemsfejl og må ikke vanhellige mine hellige Ting; thi jeg er HERREN, som helliger dem.
24 Wọ̀nyí ni àwọn ohun tí Mose sọ fún Aaroni, àwọn ọmọ Aaroni àti gbogbo ọmọ Israẹli.
Og Moses talte således til Aron og hans Sønner og alle Israeliterne.

< Leviticus 21 >