< Leviticus 19 >

1 Olúwa sọ fún Mose pé,
I korero ano a Ihowa ki a Mohi, i mea,
2 “Bá gbogbo àpéjọpọ̀ àwọn ọmọ Israẹli sọ̀rọ̀, sì wí fún wọn pé, ‘Ẹ jẹ́ mímọ́ nítorí Èmi Olúwa Ọlọ́run yín jẹ́ mímọ́.
Korero ki te whakaminenga katoa o nga tama a Iharaira, mea atu ki a ratou, Kia tapu koutou: he tapu hoki ahau, a Ihowa, to koutou Atua.
3 “‘Ẹnìkọ̀ọ̀kan yín gbọdọ̀ bọ̀wọ̀ fún ìyá àti baba rẹ̀, kí ẹ sì ya ọjọ́ ìsinmi mi sí mímọ́. Èmi ni Olúwa Ọlọ́run yín.
Me wehi tera, tera, ki tona whaea, ki tona papa, kia mau hoki ki aku hapati: ko Ihowa ahau, ko to koutou Atua.
4 “‘Ẹ má ṣe yípadà tọ ère òrìṣà lẹ́yìn, bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò gbọdọ̀ rọ ère òrìṣà idẹ fún ara yín. Èmi ni Olúwa Ọlọ́run yín.
Kei tahuri ki te whakapakoko, kei whakarewaina he atua ma koutou: ko Ihowa ahau, ko to koutou Atua.
5 “‘Nígbà tí ẹ̀yin bá sì rú ẹbọ àlàáfíà sí Olúwa, kí ẹ̀yin kí ó ṣe é ní ọ̀nà tí yóò fi jẹ́ ìtẹ́wọ́gbà dípò yín.
Ki te whakaherea ano he patunga mo te pai ki a Ihowa, hei te patunga e manakohia ai koutou.
6 Ní ọjọ́ tí ẹ bá rú u náà ni ẹ gbọdọ̀ jẹ ẹ́ tàbí ní ọjọ́ kejì; èyí tí ó bá ṣẹ́kù di ọjọ́ kẹta ni kí ẹ fi iná sun.
Me kai i te rangi ano i whakaherea ai, i te aonga ake ano hoki: a ki te toe tetahi wahi ki te toru o nga ra, me tahu ki te ahi.
7 Bí ẹ bá jẹ nínú èyí tí ó ṣẹ́kù di ọjọ́ kẹta, àìmọ́ ni èyí jẹ́, kò ní jẹ́ ìtẹ́wọ́gbà.
Ki te kainga hoki tetahi wahi i te toru o nga ra, ka whakariharihangia; e kore e manakohia:
8 Nítorí náà ẹnikẹ́ni tí ó bá jẹ ẹ́ ni a ó di ẹ̀bi rẹ̀ rù, nítorí pé ó ti ba ohun mímọ́ Olúwa jẹ́, irú ẹni bẹ́ẹ̀ ni kí ẹ gé kúrò láàrín àwọn ènìyàn rẹ̀.
A ka waha o ratou hara e nga tangata katoa i kainga ai, no te mea kua whakanoatia te mea tapu a Ihowa; a ka hatepea atu tauta tangata i roto i tona iwi.
9 “‘Nígbà tí ẹ̀yin bá kórè nǹkan oko yín, kí ẹ̀yin kí ó fi díẹ̀ sílẹ̀ láìkórè ní àwọn igun oko yín, ẹ̀yin kò sì gbọdọ̀ ṣa ẹ̀ṣẹ́ (nǹkan oko tí ẹ ti gbàgbé tàbí tí ó bọ́ sílẹ̀).
Ina kotia e koutou nga hua o to koutou whenua, kaua e kotia rawatia nga kokonga o tau mara, kaua ano hoki e hamua nga toenga o au hua.
10 Ẹ̀yin kò gbọdọ̀ kórè oko yín tan pátápátá, bẹ́ẹ̀ ni ẹ̀yin kò gbọdọ̀ ṣa èso tí ó rẹ̀ bọ́ sílẹ̀ nínú ọgbà àjàrà yín. Ẹ fi wọ́n sílẹ̀ fún àwọn aláìní àti fún àwọn àlejò. Èmi ni Olúwa Ọlọ́run yín.
Kaua hoki e hamua tau mara waina, kaua ano e kohia nga karepe taka o tau mara waina; me waiho ma te rawakore, ma te tangata iwi ke: ko Ihowa ahau, ko to koutou Atua.
11 “‘Ìwọ kò gbọdọ̀ jalè. “‘Ìwọ kò gbọdọ̀ parọ́. “‘Ẹ kò gbọdọ̀ tan ara yín jẹ.
Kaua e tahae; kaua hoki e teka, kaua ano e tinihanga tetahi ki tetahi.
12 “‘Ìwọ kò gbọdọ̀ fi orúkọ mi búra èké, kí o sì tipa bẹ́ẹ̀ ba orúkọ Ọlọ́run rẹ jẹ́. Èmi ni Olúwa.
Kei oatitia tekatia hoki toku ingoa, kaua ano hoki e whakanoatia te ingoa o tou Atua: ko Ihowa ahau.
13 “‘Ìwọ kò gbọdọ̀ rẹ́ aládùúgbò rẹ jẹ bẹ́ẹ̀ ni ìwọ kò gbọdọ̀ jà á lólè. “‘Ìwọ kò gbọdọ̀ dá owó iṣẹ́ alágbàṣe dúró di ọjọ́ kejì.
Kaua e tukinotia tou hoa, kaua hoki e pahuatia: kaua nga utu o te kaimahi e takoto tonu ki a koe i te po, a tae noa ki te ata.
14 “‘Ìwọ kò gbọdọ̀ ṣépè lé adití, bẹ́ẹ̀ ni o kò gbọdọ̀ fi ohun ìdìgbòlù sí iwájú afọ́jú, ṣùgbọ́n bẹ̀rù Ọlọ́run rẹ. Èmi ni Olúwa.
Kaua e kanga te turi, kaua ano e maka he whakatutuki ki te aroaro o te matapo; engari me wehi ki tou Atua: ko Ihowa ahau.
15 “‘Ìwọ kò gbọdọ̀ yí ìdájọ́ po, má ṣe ojúsàájú sí ẹjọ́ tálákà, bẹ́ẹ̀ ni o kò gbọdọ̀ gbé ti ọlọ́lá lẹ́yìn, ṣùgbọ́n fi òdodo ṣe ìdájọ́, àwọn aládùúgbò rẹ.
Kei whakahaere he ina whakawa; kaua e whakaaro ki te kanohi o te rawakore, kaua hoki e whakahonoretia te kanohi o te nui: me whakawa koe mo tou hoa i runga i te tika.
16 “‘Ìwọ kò gbọdọ̀ máa ṣèyíṣọ̀hún bí olóòfófó láàrín àwọn ènìyàn rẹ. “‘Ìwọ kò gbọdọ̀ ṣe ohunkóhun tí yóò fi ẹ̀mí aládùúgbò rẹ wéwu. Èmi ni Olúwa.
Kaua e kopikopiko i roto i tou iwi kawekawe korero ai: kaua ano hoki e tu kia whakahekea te toto o tou hoa: ko Ihowa ahau.
17 “‘Ìwọ kò gbọdọ̀ kórìíra arákùnrin rẹ lọ́kàn rẹ, bá aládùúgbò rẹ wí, kí o má ba à jẹ́ alábápín nínú ẹ̀bi rẹ̀.
Kei kino koe ki tou teina i roto i tou ngakau: riria marietia tou hoa, kaua e waiho he hara i runga i a ia.
18 “‘Ìwọ kò gbọdọ̀ gbẹ̀san: má sì ṣe bínú sí èyíkéyìí nínú àwọn ènìyàn rẹ. Ṣùgbọ́n, kí ìwọ kí ó fẹ́ ẹnìkejì rẹ bí ara rẹ. Èmi ni Olúwa.
Kaua e rapu utu, kaua hoki e mauahara ki nga tamariki a tou iwi; engari arohaina tou hoa ano ko koe: ko Ihowa ahau.
19 “‘Máa pa àṣẹ mi mọ́. “‘Ìwọ kò gbọdọ̀ jẹ́ kí ohun ọ̀sìn rẹ máa gùn pẹ̀lú ẹ̀yà mìíràn. “‘Ìwọ kò gbọdọ̀ gbin dàrúdàpọ̀ oríṣìí irúgbìn méjì sínú oko kan. “‘Ìwọ kò gbọdọ̀ wọ aṣọ èyí tí a fi oríṣìí ohun èlò ìhunṣọ méjì ṣe.
Kia mau ki aku tikanga. Kaua e whakatupuria he uri mo au kararehe ki tera atu tu karerehe: kaua e whakauruurua nga purapura e whakatongia e koe ki tau mara: kaua ano hoki e meatia ki a koe he kakahu ko tetahi wahi he rinena, ko tetahi he huruhur u.
20 “‘Bí ọkùnrin kan bá bá obìnrin tí ó jẹ́ ẹrú lòpọ̀, ẹni tí a ti mọ̀ pọ̀ pẹ̀lú ọkùnrin mìíràn tí a kò sì tí ì rà á padà tàbí sọ ọ́ di òmìnira. Ẹ gbọdọ̀ ṣe ìwádìí kí ẹ sì jẹ wọ́n ní ìyà tó tọ́ ṣùgbọ́n ẹ kò gbọdọ̀ pa wọ́n, torí pé kò ì tí ì di òmìnira.
Ki te takoto puremu hoki tetahi ki te wahine pononga kua oti te taumau ma te tane, ki te mea kihai i utua, i whakahokia, kihai ano hoki i tukua kia haere noa atu; ka whiua raua; e kore raua e whakamatea, no te mea kihai ia i tukua kia haere noa atu.
21 Kí ọkùnrin náà mú àgbò kan wá sí ẹnu-ọ̀nà àgọ́ ìpàdé bí i ẹbọ ẹ̀bi sí Olúwa.
A me kawe e te tane tana whakahere mo te he ki a Ihowa, ki te whatitoka o te tapenakara o te whakaminenga, he hipi toa hei whakahere mo te he.
22 Àlùfáà yóò sì ṣe ètùtù fún un, pẹ̀lú àgbò ẹbọ ẹ̀bi náà níwájú Olúwa fún ìdáríjì ẹ̀ṣẹ̀ tí ó ti ṣẹ̀. A ó sì dárí ẹ̀ṣẹ̀ náà jì í.
A ka whakamarie te tohunga mona ki te hipi toa, ki te whakahere mo te he ki te aroaro o Ihowa, mo tona hara i hara ai; a ku murua tona hara i hara ai.
23 “‘Nígbà tí ẹ bá dé ilẹ̀ náà tí ẹ sì gbin igi eléso, kí ẹ ká èso wọn sí ohun èèwọ̀. Fún ọdún mẹ́ta ni kí ẹ kà á sí èèwọ̀, ẹ kò gbọdọ̀ jẹ ẹ́.
E tae hoki koutou ki te whenua, a ka whakatongia e koutou nga rakau kai katoa; me waiho nga hua hei mea kokotikore, kia toru nga tau e waiho ai e koutou hei mea kokotikore: e kore e kainga.
24 Ṣùgbọ́n ní ọdún kẹrin, gbogbo èso wọ̀nyí yóò jẹ́ mímọ́, ọrẹ fún ìyìn Olúwa.
I te wha ia o nga tau ka tapu nga hua katoa o reira, hei whakamoemiti ki a Ihowa.
25 Ní ọdún karùn-ún ni ẹ̀yin tó lè jẹ nínú èso igi náà, kí èso wọn ba à le máa pọ̀ sí i. Èmi ni Olúwa Ọlọ́run yín.
Engari i te rima o nga tau me kai e koutou nga hua o reira, a ka maha ake ona hua ma koutou: ko Ihowa ahau, ko to koutou Atua.
26 “‘Ẹ má ṣe jẹ ẹrankẹ́ran pẹ̀lú ẹ̀jẹ̀ rẹ̀. “‘Ẹ kò gbọdọ̀ lọ sí ọ̀dọ̀ yẹ̀míwò tàbí oṣó.
Kaua e kainga tototia tetahi mea: kaua ano hoki e rapu tikanga i nga tohu, i nga kapua.
27 “‘Ẹ má ṣe dá òṣù sí àárín orí yín (fífá irun ẹ̀gbẹ́ orí, tí a ó sì dá irun àárín orí sí) tàbí kí ẹ ré orí irùngbọ̀n yín bí àwọn aláìkọlà ti ń ṣe.
Kaua e whakaporotakatia nga taha o o koutou mahunga, kaua ano hoki e whakaahuatia kinotia nga taha o tou pahau.
28 “‘Ẹ má ṣe tìtorí òkú, gé ibi kankan nínú ẹ̀yà ara yín, ẹ kò sì gbọdọ̀ sín gbẹ́rẹ́ kankan. Èmi ni Olúwa.
Kaua e haea o koutou kikokiko mo te tapapaku, kaua ano hoki e taia he tohu ki a koutou: ko Ihowa ahau.
29 “‘Ẹ má ṣe ba ọmọbìnrin yín jẹ́ láti sọ ọ́ di panṣágà, kí ilẹ̀ yín má ba à di ti àgbèrè, kí ó sì kún fún ìwà búburú.
Kaua e whakanoatia tau tamahine, e meinga hei wahine kairau; kei riro te whenua i te kairau, a ka ki te whenua i te kino.
30 “‘Ẹ gbọdọ̀ máa pa ìsinmi mi mọ́ kí ẹ sì fi ọ̀wọ̀ fún ibi mímọ́ mi. Èmi ni Olúwa.
Kia mau ki aku hapati, kia hopohopo hoki ki toku wahi tapu: ko Ihowa ahau.
31 “‘Ẹ má ṣe tọ abókùúsọ̀rọ̀ tàbí àwọn àjẹ́ lọ, ẹ kò gbọdọ̀ tọ̀ wọ́n lẹ́yìn láti jẹ́ kí wọ́n sọ yín di aláìmọ́. Èmi ni Olúwa Ọlọ́run yín.
Kaua e whakaaro atu ki nga waka atua, kaua ano hoki e whai atu ki nga mata maori, whakapokea ai e ratou: ko Ihowa ahau, ko to koutou Atua.
32 “‘Fi ọ̀wọ̀ fún ọjọ́ orí arúgbó, ẹ sì bu ọlá fún àwọn àgbàlagbà kí ẹ sì bẹ̀rù Ọlọ́run yín. Èmi ni Olúwa.
Me whakatika ake koe i te aroaro o te matenga hina, me whakahonore hoki te mata o te koroheke, me wehi ano hoki ki tou Atua: ko Ihowa ahau.
33 “‘Nígbà tí àjèjì kan bá ń gbé pẹ̀lú yín ní ilẹ̀ yín, ẹ má ṣe ṣe é ní ibi
Ki te noho hoki te tangata iwi ki ki a koe, ki tou whenua, kaua koutou e mahi i te kino ki a ia.
34 kí àjèjì tí ń gbé pẹ̀lú yín dàbí onílé láàrín yín kí ẹ sì fẹ́ràn rẹ̀ bí i ara yín, torí pé ẹ̀yin ti jẹ́ àjèjì ní ilẹ̀ Ejibiti rí. Èmi ni Olúwa Ọlọ́run yín.
Ki ta koutou kia rite ki tetahi o o koutou tangata whenua te manene e noho ana i a koutou, arohaina ia ano ko koe; he manene hoki koutou i mua, i te whenua o Ihipa: ko Ihowa ahau, ko to koutou Atua.
35 “‘Ẹ má ṣe lo òsùwọ̀n èké, nígbà tí ẹ bá ń díwọ̀n yálà nípa òsùwọ̀n ọ̀pá, òsùwọ̀n ìwúwo tàbí òsùwọ̀n onínú.
Kei he ta koutou whakahaere ina whakawa, i te ruri ranei, i te pauna taimaha ranei, i te mehua ranei.
36 Ẹ jẹ́ olódodo pẹ̀lú àwọn òsùwọ̀n yín òsùwọ̀n ìtẹ̀wọ̀n, òsùwọ̀n wíwúwo, òsùwọ̀n ìyẹ̀fun àti òsùwọ̀n nǹkan olómi yín ní láti jẹ́ èyí tí kò ní èrú nínú. Èmi ni Olúwa Ọlọ́run yín tí ó mú yín jáde láti ilẹ̀ Ejibiti.
Kia tika a koutou pauna, kia tika nga whakataimaha, kia tika te epa, kia tika hoki te hine: ko Ihowa ahau, ko to koutou Atua, i kawe mai nei i a koutou i te whenua o Ihipa.
37 “‘Ẹ ó sì máa pa gbogbo àṣẹ àti òfin mi mọ́, ẹ ó sì máa ṣe wọ́n. Èmi ni Olúwa.’”
Mo reira kia mau ki aku tikanga katoa, me aku whakaritenga katoa, mahia ano hoki: ko Ihowa ahau.

< Leviticus 19 >