< Leviticus 17 >
Szóla ismét az Úr Mózesnek, mondván:
2 “Sọ fún Aaroni àti àwọn ọmọ rẹ̀ pẹ̀lú gbogbo àwọn ọmọ Israẹli: ‘Ohun tí Olúwa pàṣẹ nìyí,
Szólj Áronnak és az ő fiainak és Izráel minden fiának, és mondd nékik: Ez az a dolog, a mit megparancsolt az Úr, mondván:
3 bí ẹnikẹ́ni nínú ìdílé Israẹli bá pa màlúù tàbí ọ̀dọ́-àgùntàn tàbí àgbò nínú ibùdó tàbí bí ó bá pa á lẹ́yìn ibùdó
Ha valaki Izráel házából ökröt, vagy bárányt, vagy kecskét öl le a táborban, vagy a ki öl a táboron kivül,
4 tí kò sì mú un wá sí ibi àgọ́ ìpàdé láti fi rú ẹbọ sí Olúwa níwájú àgọ́ ìpàdé, ẹ̀bi ìtàjẹ̀ sílẹ̀ ni kí ẹ kà sí ẹni náà lọ́rùn: torí pé ó ti ta ẹ̀jẹ̀ sílẹ̀, ẹni náà ni a ó sì gé kúrò láàrín àwọn ènìyàn rẹ̀.
És nem viszi azt a gyülekezet sátorának nyílásához, hogy áldozattal járuljon az Úrhoz, az Úrnak hajléka előtt: vérontásul tulajdoníttassék az annak az embernek; vért ontott, töröltessék ki azért az ilyen ember az ő népe közűl:
5 Èyí rí bẹ́ẹ̀ kí àwọn ọmọ Israẹli le è máa mú ẹbọ wọn tí wọn ti rú ní ìta gbangba wá sí iwájú Olúwa: wọ́n gbọdọ̀ mú un wá síwájú àlùfáà àní sí Olúwa ní ẹnu-ọ̀nà àgọ́ ìpàdé, kí wọ́n sì rú wọn gẹ́gẹ́ bí ẹbọ àlàáfíà sí Olúwa.
Azért hogy vigyék el Izráel fiai az ő véres áldozataikat, a melyeket áldoznak vala a mezőn, vigyék el azokat az Úrnak, a gyülekezet sátorának nyílásához, a paphoz, és áldozzák meg azokat hálaáldozatul az Úrnak.
6 Àlùfáà náà yóò sì fi ẹ̀jẹ̀ náà wọ́n ibi pẹpẹ Olúwa ní ẹnu-ọ̀nà àgọ́ ìpàdé, yóò sì sun ọ̀rá rẹ̀ ní òórùn dídùn sí Olúwa.
És hintse a pap a vért az Úr oltárára, a mely a gyülekezet sátorának nyílásánál van, a kövérjét pedig füstölögtesse el kedves illatul az Úrnak.
7 Nítorí náà, kí wọn má ṣe rú ẹbọ wọn sí ère ẹranko mọ́, nínú èyí tí wọ́n ti ṣe àgbèrè tọ̀ lọ. Èyí yóò sì jẹ́ ìlànà títí láé láti ìran dé ìran wọn tí ń bọ̀.’
És ne áldozzák többé véres áldozataikat az ördögöknek, a kikkel ők paráználkodnak. Örökkévaló rendtartás legyen ez nékik nemzetségről nemzetségre.
8 “Kí ó sọ fún wọn pé, ‘Ọkùnrin yówù kí ó jẹ́ ní ìdílé Israẹli tàbí ti àwọn àlejò tí ń gbé láàrín wọn tí ó bá rú ẹbọ sísun tàbí ṣe ẹbọ
Mondjad nékik ezt is: Valaki az Izráel házából, vagy a köztök tartózkodó jövevények közül, egészen égőáldozatot áldoz vagy véres áldozatot,
9 tí kò sì mú un wá sí ẹnu-ọ̀nà àgọ́ ìpàdé láti fi rú ẹbọ sí Olúwa irú ẹni bẹ́ẹ̀ ni a ó gé kúrò láàrín àwọn ènìyàn rẹ̀.
És nem viszi azt a gyülekezet sátorának nyílásához, hogy elkészítse azt az Úrnak: irtassék ki az ilyen ember az ő népe közül.
10 “‘Bí ẹnikẹ́ni bá jẹ ẹ̀jẹ̀ yálà nínú ìdílé Israẹli tàbí àwọn àlejò tí ń gbé láàrín wọn, Èmi yóò bínú sí irú ẹni náà tí ó jẹ ẹ̀jẹ̀, èmi yóò sì gé e kúrò láàrín àwọn ènìyàn rẹ̀.
És ha valaki Izráel házából, vagy a köztök tartózkodó jövevények közül valamiféle vért megeszik: kiontom haragomat az ellen, a ki a vért megette, és kiirtom azt az ő népei közül.
11 Nítorí pé nínú ẹ̀jẹ̀ ni ẹ̀mí ẹ̀dá wà, èmi sì ti fi fún yín lórí pẹpẹ fún ètùtù ọkàn yín: nítorí pé ẹ̀jẹ̀ ni a fi ń ṣe ètùtù fún ẹ̀mí ènìyàn.
Mert a testnek élete a vérben van, én pedig az oltárra adtam azt néktek, hogy engesztelésül legyen a ti életetekért, mert a vér a benne levő élet által szerez engesztelést.
12 Ìdí nìyí tí mo fi sọ fún àwọn ọmọ Israẹli pé, ọ̀kankan nínú yín kò gbọdọ̀ jẹ ẹ̀jẹ̀, bẹ́ẹ̀ ni àlejò kan tí ń ṣe àtìpó nínú yín kò gbọdọ̀ jẹ ẹ̀jẹ̀.
Azért mondtam Izráel fiainak: Egy lélek se egyék vért közületek; a köztetek tartózkodó jövevény se egye meg a vért.
13 “‘Ẹnikẹ́ni yálà nínú àwọn ọmọ Israẹli tàbí àlejò tí ń gbé láàrín wọn, tí ó bá pa ẹranko tàbí ẹyẹ tí ó yẹ fún jíjẹ gbọdọ̀ ro ẹ̀jẹ̀ rẹ̀ sílẹ̀ kí ó sì bò ó mọ́lẹ̀.
És ha valaki Izráel fiai közül, vagy a köztök tartózkodó jövevények közül vadászásban vadat vagy madarat fog, a mely megehető: ontsa ki annak vérét, és fedje be azt földdel.
14 Torí pé ẹ̀mí gbogbo ẹ̀dá ni ẹ̀jẹ̀ rẹ̀, torí náà ni mo fi kìlọ̀ fún àwọn ọmọ Israẹli pé wọn kò gbọdọ̀ jẹ ẹ̀jẹ̀ ohun abẹ̀mí kankan, torí pé nínú ẹ̀jẹ̀ ohun abẹ̀mí wọ̀nyí ni ẹ̀mí wọn wà, ẹnikẹ́ni tí ó bá jẹ ẹ́ ni a ó gé kúrò.
Mert minden testnek élete az ő vére a benne levő élettel. Azért mondom Izráel fiainak: Semmiféle testnek a vérét meg ne egyétek, mert minden testnek élete az ő vére; valaki megeszi azt, irtassék ki.
15 “‘Ẹnikẹ́ni tí ó bá jẹ ohun tí ó kú sílẹ̀ fúnra rẹ̀, tàbí èyí tí ẹranko búburú pa kálẹ̀ yálà onílé tàbí àlejò, ó ní láti fọ aṣọ rẹ̀. Kí ó sì fi omi wẹ ara rẹ̀, yóò sì wà ní ipò àìmọ́ títí di àṣálẹ́ lẹ́yìn èyí ni yóò tó di mímọ́.
Ha pedig valaki elhullott, vagy vadtól megszaggatott állatot eszik, akár benszülött, akár jövevény: mossa meg ruháit, és mosódjék meg vízben, és tisztátalan legyen estvéig, azután tiszta.
16 Ṣùgbọ́n bí ó bá kọ̀ láti wẹ ara rẹ̀ tí kò sì fọ aṣọ rẹ̀ náà: ẹ̀bi rẹ̀ yóò wà lórí ara rẹ̀.’”
Hogyha meg nem mossa ruháit, sem a testét le nem mossa: viselje az ő vétségének terhét.