< Leviticus 12 >

1 Olúwa sọ fún Mose pé,
Angraeng mah Mosi khaeah,
2 “Sọ fún àwọn ará Israẹli pé: ‘Obìnrin tí ó bá lóyún tí ó sì bí ọmọkùnrin, yóò wà láìmọ́ fún ọjọ́ méje bí ìgbà tí ó wà ní ipò àìmọ́ lákokò nǹkan oṣù rẹ̀.
Israel kaminawk khaeah thui paeh; nongpata loe zokpom moe, capa to sah nahaeloe, khrah kruek athii hnuk naah ciim ai ah ohhaih ih atawk baktih toengah, anih loe nih sarihto thung ciim mak ai.
3 Ní ọjọ́ kẹjọ ni kí ẹ kọ ọmọ náà ní ilà.
Ni tazetto naah a capa ih tangzat hin to aah pae han oh.
4 Obìnrin náà yóò sì dúró fún ọjọ́ mẹ́tàlélọ́gbọ̀n láti di mímọ́ kúrò nínú ìsun ẹ̀jẹ̀ rẹ̀. Kò gbọdọ̀ fi ọwọ́ kan ohunkóhun tí ó jẹ́ mímọ́ tàbí kí ó lọ sí ibi mímọ́ Olúwa títí di ọjọ́ tí ìwẹ̀nùmọ́ rẹ̀ yóò kọjá.
To pacoengah nongpata ih kuithlam to ciim hanah, ni qui thumto pacoeng, ni thumto zing vop tih; anih loe kaciim ah ohhaih ni boeng ai karoek to, kaciim hmuen to sui mak ai ueloe, hmuenciim ah doeh caeh mak ai.
5 Bí ó bá ṣe obìnrin ni ó bí, fún ọ̀sẹ̀ méjì ni obìnrin náà yóò fi wà ní ipò àìmọ́, gẹ́gẹ́ bí àkókò nǹkan oṣù rẹ̀. Ó sì gbọdọ̀ dúró ní ọjọ́ mẹ́rìndínláàádọ́rin láti di mímọ́ kúrò nínú ìsun ẹ̀jẹ̀ rẹ̀.
Toe caa nongpata to sah nahaeloe, athii hnuk naah ciim ai ah ohhaih atawk baktih toengah, zar hnetto thung ciim ai ah om tih; to pacoengah kuithlam to ciim hanah ni qui tarukto pacoeng, ni tarukto thung zing vop tih.
6 “‘Nígbà tí ọjọ́ ìwẹ̀nùmọ́ rẹ̀ fún ọmọkùnrin tàbí ọmọbìnrin bá kọjá kí ó mú ọ̀dọ́-àgùntàn ọlọ́dún kan wá fún àlùfáà ní ẹnu-ọ̀nà àgọ́ ìpàdé fún ẹbọ sísun àti ọmọ ẹyẹlé tàbí àdàbà kan fún ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀.
Capa hanah maw, canu hanah maw, ciimhaih ni boeng naah, hmai angbawnhaih sak hanah, saningto kaom tuucaa maeto, zae angbawnhaih sak hanah, pahuu caa maeto maw, to tih ai boeh loe im pahuu maeto, amkhuenghaih kahni im thok taengah qaima khaeah sin han oh;
7 Ó gbọdọ̀ fi wọ́n rú ẹbọ níwájú Olúwa láti ṣe ètùtù fún obìnrin náà lẹ́yìn náà ni yóò di mímọ́ kúrò nínú ìsun ẹ̀jẹ̀ rẹ̀. “‘Ìwọ̀nyí ni àwọn ìlànà fún obìnrin tí ó bá bí ọmọkùnrin tàbí ọmọbìnrin.
qaima mah nongpata han zae angbawnhaih sah pae tih; to pacoengah loe nongpata to kuithlam hoiah ciim tih boeh; hae loe nongpa maw, nongpata maw caa sah nongpata han paek ih atawk ah oh.
8 Bí kò bá lágbára àti fi àgùntàn ṣe é, ó gbọdọ̀ le mú àdàbà méjì tàbí ọmọ ẹyẹlé méjì, ọ̀kan fún ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀, àti èkejì fún ẹbọ sísun. Báyìí ni àlùfáà yóò ṣe ètùtù fún un. Òun yóò sì di mímọ́.’”
Nongpata mah tuucaa to sin thai ai nahaeloe, pahuu hnetto maw, to tih ai boeh loe im pahuu hnetto sin han oh; maeto hoiah hmai angbawnhaih to sah ueloe, kalah maeto hoiah zae angbawnhaih to sah tih; qaima mah to nongpata han zae angbawnhaih sah pae tih; to naah anih loe zaehaih to ciim tih boeh.

< Leviticus 12 >