< Leviticus 11 >

1 Olúwa sọ fún Mose àti Aaroni pé,
Nake Jehova akĩĩra Musa na Harũni atĩrĩ,
2 “Ẹ sọ fún àwọn ara Israẹli pé, ‘Nínú gbogbo ẹranko tí ń gbé lórí ilẹ̀, àwọn wọ̀nyí ni ẹ le jẹ.
“Ĩrai andũ a Isiraeli ũũ, ‘Gatagatĩ-inĩ ka nyamũ ciothe iria irĩ bũrũri-inĩ-rĩ, ici nĩcio mũngĩrĩa:
3 Gbogbo ẹranko tí pátákò ẹsẹ̀ rẹ̀ bá là tí ó sì ń jẹ àpọ̀jẹ.
No mũrĩe nyamũ o yothe ĩrĩ mahũngũ marekanĩtie gatagatĩ biũ na ĩcookagia ithagumia.
4 “‘Àwọn mìíràn wà tó ń jẹ àpọ̀jẹ nìkan. Àwọn mìíràn wà tó jẹ́ pé pátákò ẹsẹ̀ wọn nìkan ni ó là, ìwọ̀nyí ni ẹ kò gbọdọ̀ jẹ fún àpẹẹrẹ bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ìbákasẹ ń jẹ àpọ̀jẹ kò ya pátákò ẹsẹ̀, àìmọ́ ni èyí jẹ́.
“‘Nĩ kũrĩ nyamũ imwe icookagia o ithagumia tu, na ingĩ irĩ o mahũngũ marekanĩtie; icio mũtikanacirĩe. Ngamĩĩra o na aakorwo nĩĩcookagia ithagumia-rĩ, mahũngũ mayo matirekanĩtie; ĩyo ĩrĩ thaahu harĩ inyuĩ.
5 Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé gara (ẹranko tí ó dàbí ehoro tí ń gbé inú àpáta) ń jẹ àpọ̀jẹ; aláìmọ́ ni èyí jẹ́ fún yín.
Gĩkami o na aakorwo nĩgĩcookagia ithagumia-rĩ, mahũngũ makĩo matirekanĩtie; kĩu kĩrĩ thaahu harĩ inyuĩ.
6 Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ehoro ń jẹ àpọ̀jẹ, ṣùgbọ́n kò ya pátákò ẹsẹ̀; aláìmọ́ ni èyí jẹ́ fún yín.
Mbũkũ o na aakorwo nĩĩcookagia ithagumia-rĩ, mahũngũ mayo matirekanĩtie; ĩyo ĩrĩ thaahu harĩ inyuĩ.
7 Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ẹlẹ́dẹ̀ ya pátákò ẹsẹ̀ ṣùgbọ́n kì í jẹ àpọ̀jẹ; aláìmọ́ ni èyí jẹ́ fún yín.
Nayo ngũrwe o na akorwo mahũngũ mayo nĩmarekanĩtie biũ-rĩ, ndĩcookagia ithagumia; ĩyo ĩrĩ thaahu harĩ inyuĩ.
8 Ẹ má ṣe jẹ ẹran wọn, ẹ kò sì gbọdọ̀ fọwọ́ kan òkú wọn. Àìmọ́ ni wọ́n jẹ́ fún yín.
Mũtikanarĩe nyama ciacio kana mũhutie ciimba ciacio; icio irĩ thaahu harĩ inyuĩ.
9 “‘Nínú gbogbo ohun tí Ọlọ́run dá tí ń gbé inú omi Òkun, àti nínú odò: èyíkéyìí tí ó bá ní lẹbẹ àti ìpẹ́ ni ẹ lè jẹ́.
“‘Harĩ ciũmbe ciothe iria itũũraga maaĩ-inĩ ma iria na ma tũrũũĩ-rĩ, no mũrĩe ciothe iria irĩ mathagu manyiitaine na nĩ irĩ ngaracũ mwĩrĩ.
10 Ṣùgbọ́n nínú gbogbo ẹ̀dá tí ń gbé inú òkun àti nínú odò tí kò ní lẹbẹ àti ìpẹ́, yálà nínú gbogbo àwọn tí ń rákò tàbí láàrín gbogbo àwọn ẹ̀dá alààyè yòókù tí ń gbé inú omi àwọn ni kí ẹ kórìíra.
No ciũmbe ciothe iria irĩ iria-inĩ kana tũrũũĩ-inĩ, na itirĩ mathagu manyiitaine o hamwe na ngaracũ mwĩrĩ, irĩ imwe cia iria ithiiaga irĩ hamwe, kana irĩ ciothe cia iria irĩ muoyo kũu maaĩ-inĩ; no nginya mũcithũũre biũ.
11 Nígbà tí ẹ ti kórìíra wọn ẹ kò gbọdọ̀ jẹ ẹran wọn: ẹ gbọdọ̀ kórìíra òkú wọn.
Na tondũ no nginya mũcithũũre-rĩ, mũtikanarĩe nyama ciacio, na no nginya mũthũũre ciimba ciacio biũ.
12 Ohunkóhun tí ń gbé inú omi tí kò ní lẹbẹ àti ìpẹ́ gbọdọ̀ jásí ìríra fún yín.
Kĩndũ o gĩothe gĩtũũraga maaĩ-inĩ na gĩtirĩ mathagu manyiitaine kana ngaracũ mwĩrĩ, nĩciagũthũũrwo nĩ inyuĩ biũ.
13 “‘Àwọn ẹyẹ wọ̀nyí ni ẹ gbọdọ̀ kórìíra tí ẹ kò gbọdọ̀ jẹ wọ́n torí pé ohun ìríra ni wọ́n: idì, oríṣìíríṣìí igún,
“‘Ici nĩcio nyoni iria mwagĩrĩirwo nĩgũthũũra na mũtangĩrĩa tondũ nĩ thũũre; nacio nĩ nderi, na ndiyũ, na ndiyũ iria njirũ,
14 àwòdì àti onírúurú àṣá,
na hũngũ ĩrĩa ndune, na mũthemba o wothe wa hũngũ iria njirũ,
15 onírúurú ẹyẹ ìwò,
na mahuru mothe,
16 Òwìwí, onírúurú ògòǹgò, onírúurú ẹ̀lúùlú, onírúurú àwòdì,
na ndundu ĩrĩa ĩrĩ rũhĩa, na ndundu ĩrĩa ĩgambaga, na nyoni ya iria-inĩ ĩrĩa ĩrĩ mathagu maraaya, na mũthemba o wothe wa rwĩgĩ,
17 Òwìwí kéékèèké, onírúurú òwìwí,
na gatundu karĩa kanini, na nyoni ya iria-inĩ ĩrĩa ĩrĩ ngingo ndaaya, na ndundu ĩrĩa nene,
18 Òwìwí funfun àti òwìwí ilẹ̀ pápá, àti àkàlà,
na ndundu ĩrĩa njerũ, na ndundu ya werũ-inĩ, na hũngũ ya iria-inĩ,
19 àkọ̀, onírúurú òòdẹ̀, atọ́ka àti àdán.
na karoga-ngunũ, na mĩthemba yothe ya cũcũ-wa-njoka, na hudihuda, o na rũhuhu.
20 “‘Gbogbo kòkòrò tí ń fò tí ó sì ń fi ẹsẹ̀ mẹ́rẹ̀ẹ̀rin rìn ni wọ́n jẹ́ ìríra fún yín,
“‘Tũnyamũ tuothe tũrĩa tũmbũkaga na tũthiiagĩra thĩ na magũrũ mana nĩ mwagĩrĩirwo nĩ gũtũthũũra mũno.
21 irú àwọn kòkòrò oniyẹ̀ẹ́ tí wọn sì ń fi ẹsẹ̀ mẹ́rẹ̀ẹ̀rin rìn tí ẹ le jẹ nìyí, àwọn kòkòrò tí wọ́n ní ìṣẹ́po ẹsẹ̀ láti máa fi fò lórí ilẹ̀.
No nĩ kũrĩ tũnyamũ tũmwe tũrĩ mathagu na tũthiiaga na magũrũ mana tũrĩa mũngĩrĩa; natuo nĩ tũrĩa tũrĩ na magũrũ marĩ nyunĩro ma gũtũteithia kũrũga.
22 Nínú àwọn wọ̀nyí ni ẹ lè jẹ onírúurú eṣú, onírúurú ìrẹ̀ àti onírúurú tata.
Thĩinĩ wa tuo no mũrĩe mĩthemba yothe ya ngigĩ, na ndararĩki, na ngiria, o na kana ndaahi.
23 Ṣùgbọ́n gbogbo ohun ìyókù tí ń fò, tí ń rákò, tí ó ní ẹsẹ̀ mẹ́rin, òun ni kí ẹ̀yin kí ó kà sí ìríra fún yín.
No tũnyamũ tũu tũngĩ tuothe tũrĩ mathagu na tũrĩ na magũrũ mana no nginya mũtũthũũre mũno.
24 “‘Nípa àwọn wọ̀nyí ni ẹ le fi sọ ara yín di àìmọ́. Ẹnikẹ́ni tí ó bá fọwọ́ kan òkú wọn yóò di aláìmọ́ títí ìrọ̀lẹ́.
“‘Nĩmũgethaahia na maũndũ maya; ũrĩa wothe ũngĩhutia ciimba ciatuo agaatinda arĩ na thaahu o nginya hwaĩ-inĩ.
25 Ẹnikẹ́ni tí ó bá gbé òkú wọn gbọdọ̀ fọ aṣọ rẹ̀, yóò sì jẹ́ aláìmọ́ títí ìrọ̀lẹ́.
Mũndũ o wothe ũkooya kĩimba gĩatuo no nginya athambie nguo ciake, na nĩagatinda arĩ na thaahu o nginya hwaĩ-inĩ.
26 “‘Àwọn ẹranko tí pátákò wọn kò là tan tàbí tí wọn kò jẹ àpọ̀jẹ jẹ́ àìmọ́ fún yín. Ẹni tí ó bá fọwọ́ kan òkú èyíkéyìí nínú wọn yóò jẹ́ aláìmọ́.
“‘Nyamũ o yothe ĩrekanĩtie mahũngũ no matirekanĩtie biũ, kana ĩrĩa ĩtacookagia ithagumia, ĩyo ĩrĩ thaahu harĩ inyuĩ; mũndũ o wothe ũkaahutia kĩimba kĩa ĩmwe yacio nĩakanyiitwo nĩ thaahu.
27 Nínú gbogbo ẹranko tí ń fi ẹsẹ̀ mẹ́rẹ̀ẹ̀rin rìn, àwọn tí ń fi èékánná wọn rìn jẹ́ aláìmọ́ fún yín, ẹni tí ó bá fọwọ́ kan òkú wọn yóò jẹ́ aláìmọ́ títí di ìrọ̀lẹ́.
Harĩ nyamũ ciothe iria ithiiaga na magũrũ mana-rĩ, iria ikinyaga na ithu irĩ thaahu harĩ inyuĩ; mũndũ ũrĩa wothe ũkaahutia ciimba ciacio agaatinda arĩ na thaahu o nginya hwaĩ-inĩ.
28 Ẹni tí ó bá gbé òkú wọn gbọdọ̀ fọ aṣọ rẹ̀, yóò sì jẹ́ aláìmọ́ títí di ìrọ̀lẹ́. Wọ̀nyí jẹ́ àìmọ́ fún yín.
Mũndũ o wothe ũngĩoya ciimba ciacio no nginya athambie nguo ciake, na atiinde arĩ na thaahu o nginya hwaĩ-inĩ. Icio irĩ thaahu harĩ inyuĩ.
29 “‘Nínú gbogbo ẹranko tí ń rìn lórí ilẹ̀ ìwọ̀nyí ni ó jẹ́ àìmọ́ fún yín: Asé, eku àti oríṣìíríṣìí aláǹgbá,
“‘Harĩ nyamũ ciothe iria ithiiagĩra thĩ, ici nĩcio irĩ thaahu harĩ inyuĩ: mũrũngũru na mbĩa, na njagathi iria nene cia mĩthemba yothe,
30 Ọmọnílé, alágẹmọ, aláǹgbá, ìgbín àti ọ̀gà.
na gĩthenyũka, na kĩgurumũki, na njagathi, na gĩcagathi kĩrĩa kĩa mahiga-inĩ, na kĩĩmbu.
31 Nínú gbogbo ohun tí ń rìn lórí ilẹ̀, ìwọ̀nyí jẹ́ àìmọ́ fún yín. Ẹnikẹ́ni tí ó bá fọwọ́ kan òkú wọn yóò di aláìmọ́ títí ìrọ̀lẹ́.
Harĩ iria ciothe ithiiagĩra thĩ, ici irĩ thaahu harĩ inyuĩ. Mũndũ o wothe ũngĩcihutia ikuĩte-rĩ, agaatinda arĩ na thaahu o nginya hwaĩ-inĩ.
32 Bí ọ̀kan nínú wọn bá kú tí wọ́n sì bọ́ sórí nǹkan kan, bí ó ti wù kí irú ohun náà wúlò tó, yóò di aláìmọ́ yálà aṣọ ni a fi ṣe é ni tàbí igi, irun aṣọ tàbí àpò, ẹ sọ ọ́ sínú omi yóò jẹ́ aláìmọ́ títí ìrọ̀lẹ́ lẹ́yìn náà ni yóò tó di mímọ́.
Rĩrĩa ĩmwe yacio ĩngĩkua na ĩgũĩre kĩndũ, kĩndũ kĩu o na kĩngĩkorwo kĩrĩ kĩa wĩra ũrĩkũ, nĩgĩkanyiitwo nĩ thaahu, o na aakorwo gĩthondeketwo na mbaũ, kana gĩtambaya, kana rũũa kana ikũnia. Nĩkĩrindwo maaĩ-inĩ; gĩgaakorwo kĩrĩ na thaahu o nginya hwaĩ-inĩ, na nĩgĩgacooka gĩthirwo nĩ thaahu.
33 Bí èyíkéyìí nínú wọn bá bọ́ sínú ìkòkò amọ̀, gbogbo ohun tí ó wà nínú rẹ̀ ti di àìmọ́. Ẹ gbọdọ̀ fọ ìkòkò náà.
Nyamũ ĩmwe ya icio ĩngĩgũa thĩinĩ wa nyũngũ ya rĩũmba-rĩ, kĩndũ kĩrĩa gĩothe kĩrĩ thĩinĩ wayo nĩgĩkanyiitwo nĩ thaahu, na no nginya mũũrage nyũngũ ĩyo.
34 Bí omi inú ìkòkò náà bá dà sórí èyíkéyìí nínú oúnjẹ tí ẹ̀ ń jẹ oúnjẹ náà di aláìmọ́. Gbogbo ohun mímu tí a lè mú jáde láti inú rẹ̀ di àìmọ́.
Irio o ciothe ingĩrĩĩo no ikorwo irĩ na maaĩ moimĩte nyũngũ-inĩ ta ĩyo irĩ na thaahu, na kĩndũ o gĩothe gĩa kũnyuuo kiumĩte thĩinĩ wayo kĩrĩ na thaahu.
35 Gbogbo ohun tí èyíkéyìí nínú òkú wọn bá já lé lórí di àìmọ́. Yálà ààrò ni tàbí ìkòkò ìdáná wọn gbọdọ̀ di fífọ́. Wọ́n jẹ́ àìmọ́. Ẹ sì gbọdọ̀ kà wọ́n sí àìmọ́.
Kĩndũ o gĩothe kĩngĩkaagwĩrwo nĩ kĩimba kĩmwe gĩacio, nĩgĩkanyiitwo nĩ thaahu; riiko kana nyũngũ ya kũruga no nginya ciũragwo. Indo icio irĩ na thaahu, nacio indo icio nĩigatuĩka thaahu harĩ inyuĩ.
36 Bí òkú wọn bá bọ́ sínú omi tàbí kànga tó ní omi nínú, omi náà kò di aláìmọ́ ṣùgbọ́n ẹnikẹ́ni tí ó bá yọ òkú wọn jáde tí ó fi ọwọ́ kàn án yóò di aláìmọ́.
No rĩrĩ, gĩthima kana irima rĩa maaĩ, icio itingĩnyiitwo nĩ thaahu, no mũndũ o wothe ũkaahutia kĩimba kĩmwe kĩa indo icio irĩ thaahu nĩakanyiitwo nĩ thaahu.
37 Bí òkú ẹranko wọ̀nyí bá bọ́ sórí ohun ọ̀gbìn tí ẹ fẹ́ gbìn wọ́n sì jẹ́ mímọ́.
Kĩimba kĩngĩkaagwĩra mbeũ o na irĩkũ cia kũhaandwo, itikanyiitwo nĩ thaahu.
38 Ṣùgbọ́n bí ẹ bá ti da omi sí ohun ọ̀gbìn náà tí òkú wọn sì bọ́ sí orí rẹ̀ àìmọ́ ni èyí fún un yín.
No mbeũ icio ingĩkorwo irindĩtwo maaĩ-inĩ, nakĩo kĩimba gĩcigũĩre, mbeũ icio irĩ na thaahu harĩ inyuĩ.
39 “‘Bí ẹran kan bá kú nínú àwọn tí ẹ lè jẹ, ẹnikẹ́ni tí ó bá fọwọ́ kan òkú rẹ̀ yóò di aláìmọ́ títí ìrọ̀lẹ́.
“‘Nyamũ ĩrĩa mwĩtĩkĩrĩtio kũrĩa ĩngĩkua, mũndũ o wothe ũkaahutia kĩimba kĩayo agaatinda arĩ na thaahu o nginya hwaĩ-inĩ.
40 Ẹnikẹ́ni tí ó bá jẹ èyíkéyìí nínú òkú ẹranko náà gbọdọ̀ fọ aṣọ rẹ̀, yóò sì di aláìmọ́ títí ìrọ̀lẹ́. Ẹnikẹ́ni tí ó bá gbé òkú ẹranko yóò fọ aṣọ rẹ̀ yóò sì wà ní àìmọ́ títí ìrọ̀lẹ́.
Mũndũ o wothe ũngĩrĩa nyama cia kĩimba kĩu no nginya athambie nguo ciake, nake agaatinda arĩ na thaahu o nginya hwaĩ-inĩ. Mũndũ o wothe ũngĩoya kĩimba kĩu no nginya athambie nguo ciake, nake atiinde arĩ na thaahu o nginya hwaĩ-inĩ.
41 “‘Ìríra ni gbogbo ohun tí ń rìn káàkiri lórí ilẹ̀ jẹ́, ẹ kò gbọdọ̀ jẹ wọ́n.
“‘Kĩũmbe gĩothe kĩrĩa gĩtambaga thĩ nĩgĩthũũre; ti gĩa kũrĩĩo.
42 Ẹ kò gbọdọ̀ jẹ ohunkóhun tí ń rìn ká orí ilẹ̀ yálà ó ń fàyàfà tàbí ó ń fi ẹsẹ̀ mẹ́rẹ̀ẹ̀rin rìn, tàbí ó ń fi ọ̀pọ̀lọpọ̀ ẹsẹ̀ rìn ìríra ni èyí.
Mũtikanarĩe kĩũmbe gĩothe kĩrĩa gĩtambaga thĩ, kana gĩthiiaga na nda, kana na magũrũ mothe mana, kana magũrũ maingĩ; icio mũcithũũre mũno.
43 Ẹ̀yin kò gbọdọ̀ fi ohun kan tí ń rákò, sọ ara yín di ìríra, bẹ́ẹ̀ ni ẹ̀yin kò gbọdọ̀ fi wọ́n sọ ara yín di aláìmọ́, tí ẹ̀yin yóò fi ti ipa wọn di eléèérí.
Mũtikanethaahie na kĩũmbe o na kĩmwe gĩacio. Mũtikaneĩkĩre thaahu nĩ ũndũ wacio kana mũreke imũgwatie thaahu.
44 Èmi ni Olúwa Ọlọ́run yín, ẹ ya ara yín sọ́tọ̀ kí ẹ sì jẹ́ mímọ́ torí pé mo jẹ́ mímọ́. Ẹ má ṣe sọ ara yín di àìmọ́ nípasẹ̀ ohunkóhun tí ń rìn káàkiri lórí ilẹ̀.
Niĩ nĩ niĩ Jehova Ngai wanyu; mwĩamũrei na mwĩtherie, tondũ niĩ ndĩ mũtheru. Mũtikanethaahie na kĩũmbe o gĩothe kĩrĩa gĩtambaga thĩ.
45 Èmi ni Olúwa tí ó mú yín jáde láti ilẹ̀ Ejibiti wá láti jẹ́ Ọlọ́run yín torí náà, ẹ jẹ́ mímọ́ torí pé mímọ́ ni èmi.
Niĩ nĩ niĩ Jehova ũrĩa wamũrutire kuuma bũrũri wa Misiri nduĩke Ngai wanyu; nĩ ũndũ ũcio mwĩtheriei, tondũ niĩ ndĩ mũtheru.
46 “‘Àwọn wọ̀nyí ni ìlànà fún ẹranko, ẹyẹ, gbogbo ẹ̀dá alààyè tí ń gbé inú omi àti àwọn ẹ̀dá tí ó ń rìn lórí ilẹ̀.
“‘Macio nĩmo mawatho marĩa makoniĩ nyamũ, na nyoni, na kĩndũ gĩothe kĩrĩ muoyo kĩrĩa gĩthiiagĩra maaĩ-inĩ, na kĩũmbe o ro gĩothe kĩrĩa gĩtambaga thĩ.
47 Ẹ gbọdọ̀ mọ ìyàtọ̀ láàrín àìmọ́ àti mímọ́ láàrín ẹ̀dá alààyè, tí ẹ le jẹ àti èyí tí ẹ kò le jẹ.’”
No nginya mũkũũranage nyamũ iria irĩ thaahu na iria itarĩ thaahu, na mũkũũranage ciũmbe iria irĩ muoyo ingĩrĩĩo na iria itangĩrĩĩo.’”

< Leviticus 11 >