< Leviticus 10 >

1 Nadabu àti Abihu tí í ṣe ọmọ Aaroni sì mú àwo tùràrí kọ̀ọ̀kan, wọ́n fi iná àti tùràrí sínú rẹ̀, wọ́n sì rú iná àjèjì níwájú Olúwa, èyí tó lòdì sí àṣẹ Olúwa.
Songa nandrambe ty sadron’ afo’e t’i Nadabe naho i Abiho, ana’ i Aharone, naho nasia’ iareo afo, naho nampipohañ’ emboke vaho ninday afo tsie añatrefa’ Iehovà, ie tsy nandilia’e.
2 Torí èyí, iná jáde láti ọ̀dọ̀ Olúwa, ó sì jó wọn pa, wọ́n sì kú níwájú Olúwa.
Aa le niforoake boak’ am’ Iehovà ty afo namorototo iareo, vaho nikoromak’ añatrefa’ Iehovà.
3 Mose sì sọ fún Aaroni pé, “Ohun tí Olúwa ń sọ nípa rẹ̀ nìyìí nígbà tó wí pé, “‘Ní àárín àwọn tó súnmọ́ mi, Èmi yóò fi ara mi hàn ní mímọ́ ojú gbogbo ènìyàn Ní a ó ti bu ọlá fún mi.’” Aaroni sì dákẹ́.
Le hoe t’i Mosè amy Aharone, Izay ty talin-tsara’ Iehovà, ie nanao ty hoe: Hampiavahe’ o mpañarine ahikoo iraho, vaho ho rengèñe añatrefa’ ondaty iabio. Fe nianjiñe t’i Aharone.
4 Mose pe Miṣaeli àti Elsafani ọmọ Usieli tí í ṣe arákùnrin Aaroni, ó sọ fún wọn pé, “Ẹ wá, kí ẹ sì gbé àwọn arákùnrin yín jáde kúrò níwájú ibi mímọ́ lọ sí ẹ̀yìn ibùdó.”
Kinanji’ i Mosè t’i Misaele naho i Eltsafane, ana’ i Oziele, rahalahin-drae’ i Aharone, le natao’e ty hoe: Mb’ etoa, takono boak’ aolo’ i toetse miavakey mb’ alafen-tobe añe o longo’oo.
5 Wọ́n sì wá gbé wọn, pẹ̀lú ẹ̀wù àwọ̀tẹ́lẹ̀ wọn ní ọrùn wọn lọ sí ẹ̀yìn ibùdó bí Mose ti sọ.
Aa le nimb’eo iereo nitakoñe aze aman-tsikiñe mb’ alafe’ i tobey mb’eo, amy nitsarae’ i Mosèy.
6 Mose sọ fún Aaroni àti àwọn ọmọ rẹ̀ yòókù, Eleasari àti Itamari pé, “ẹ má ṣe ṣọ̀fọ̀ nípa ṣíṣe aláìtọ́jú irun yín tàbí kí ẹ ṣí orí yín sílẹ̀, ẹ kò sì gbọdọ̀ ya aṣọ, bí ẹ bá ṣe bẹ́ẹ̀, ẹ ó kùú, Olúwa yóò sì bínú sí gbogbo ìjọ ènìyàn. Ṣùgbọ́n àwọn ẹbí yín, àti gbogbo ilé Israẹli le è ṣọ̀fọ̀ lórí àwọn tí Olúwa fi iná parun.
Le hoe t’i Mosè amy Aharone naho amy Elazare naho Itamare, ana’e, Ko añafahan-tsabaka ty añambone’ areo, naho ko mandria-tsaroñe tsy mone hihomake vaho hifetsak’ am’ondaty iabio ty haviñerañe. Fe o longo’ areoo, i anjomba’ Israele iabiy ty handala i famorototoañe niviañe’ Iehovày.
7 Ẹ má ṣe kúrò ní ẹnu-ọ̀nà àgọ́ ìpàdé, bí ẹ bá kúrò níbẹ̀, ẹ ó kù ú, nítorí pé òróró ìtasórí Olúwa wà lórí yín.” Wọ́n sì ṣe bí Mose ti wí.
Le ko mienga ty lalan-kibohom-pamantañañe tsy mone hihomake, amy te ama’ areo ty mena-pañoriza’ Iehovà. Le nanoe’ iareo ty nitsarae’i Mosè.
8 Olúwa sì sọ fún Aaroni pé.
Le hoe ty nitsarae’ Iehovà amy Aharone,
9 “Ìwọ àti àwọn ọmọ rẹ̀ kò gbọdọ̀ mu ọtí wáìnì tàbí ọtí líle mìíràn nígbàkígbà tí ẹ bá n lọ inú àgọ́ ìpàdé, bí ẹ bá ṣe bẹ́ẹ̀, ẹ ó kù ú, èyí jẹ́ ìlànà títí láé fún un yín láti ìrandíran.
Ko mikama divay ndra toake, ihe naho o ana’o miharo ama’oo, t’ie mizilik’ amy kibohom-pamantañañey ao, tsy mone hikoromake. Fañè nainaie amo tarira’ areo mifandimbeo izay,
10 Ẹ gbọdọ̀ mọ ìyàtọ̀ láàrín mímọ́ àti àìmọ́, láàrín èérí àti àìléèérí.
hampiavahañe ty masiñe ami’ty tsotra naho ty maleotse ami’ty malio,
11 Ẹ gbọdọ̀ kọ́ àwọn ara Israẹli ní gbogbo àṣẹ tí Olúwa fún wọn láti ẹnu Mose.”
naho hañanarañe o ana’ Israeleo ze hene fañè nitsarae’ Iehovà am’ iereo am-pità’ i Mosè.
12 Mose sì sọ fún Aaroni, Eleasari àti Itamari àwọn ọmọ rẹ̀ yòókù pé, “Ẹ mú ẹbọ ohun jíjẹ tó ṣẹ́kù láti inú ẹbọ àfinásun sí Olúwa, kí ẹ jẹ ẹ́ láìní ìwúkàrà nínú, lẹ́gbẹ̀ẹ́ pẹpẹ nítorí ó jẹ́ mímọ́ jùlọ.
Le hoe t’i Mosè amy Aharone naho amy Elazare vaho Itamare, sehangan’ ana’e rey: Rambeso ty enga-mahakama nisisa amy nisoroñañe am’ Iehovày, vaho ikamao po-dalivay marine’ i kitreliy fa miava-do’e.
13 Ẹ jẹ́ ní ibi mímọ́, nítorí pé òun ni ìpín rẹ àti ti àwọn ọmọ rẹ nínú ẹbọ tí a finá sun sí Olúwa nítorí pé bẹ́ẹ̀ ni mo ṣe pa á láṣẹ.
Ho kamae’ areo amy toe-miavakey amy t’ie anjara’o naho anjara’ o ana’oo boak’ amy soroñañe am’ Iehovày, amy nandiliañ’ ahikoy.
14 Ṣùgbọ́n ìwọ àti àwọn ọmọkùnrin àti àwọn ọmọbìnrin rẹ le jẹ igẹ̀ ẹran tí a fì níwájú Olúwa àti itan tí wọ́n gbé síwájú Olúwa, kí ẹ jẹ wọ́n ní ibi tí a kà sí mímọ́, èyí ni a ti fún ìwọ àti àwọn ọmọ rẹ gẹ́gẹ́ bí ìpín yín nínú ẹbọ àlàáfíà àwọn ara Israẹli.
Ho kamae’o ami’ty malio ka ty tratra’ i engan-kelahelay naho ty tso’ i enga-kavoañey, ihe naho o ana-dahi’oo naho o anak-ampela’o miharo ama’oo, amy t’ie natolotse ho zo’o naho zo’ o keleia’oo boak’ amo engam-pañanintsiñe fisoroña’ o ana’ Israeleo.
15 Itan tí wọ́n mú wá àti igẹ̀ ẹran tí ẹ fì ni ẹ gbọdọ̀ mú wá pẹ̀lú ọ̀rá ẹbọ tí a finá sun láti le è fì wọ́n níwájú Olúwa bí ẹbọ fífì. Èyí yóò sì jẹ́ ìpín tìrẹ àti ti àwọn ọmọ rẹ nígbà gbogbo bí Olúwa ṣe pàṣẹ.”
Hasese’ iareo mindre amo safo’e hisoroñañeo ty tson’ engan-kavoañe naho ty tratra’ i engan-kelahelay, hahelahela ho engan-kelahela añatrefa’ Iehovà. Le ho azo naho o ana’ areo mindre ama’oo ho fañè tsy modo ami’ty nandilia’ Iehovà.
16 Nígbà tí Mose wádìí nípa ewúrẹ́ ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀ tó sì rí i pé wọ́n ti sun ún, ó bínú sí Eleasari àti Itamari, àwọn ọmọ Aaroni yòókù, ó sì béèrè pé,
Nitsoehe’ i Mosè amy zao i osen’ engan-kakeoy; inao finorototo! Niviñera’e t’i Elazare naho Itamare, ana’ i Aharone honka’e rey, ami’ty hoe:
17 “Èéṣe tí ẹ kò jẹ ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀ náà ní agbègbè ibi mímọ́? Ó jẹ́ mímọ́ jùlọ, a fi fún yín láti lè mú ẹ̀ṣẹ̀ ìjọ ènìyàn kúrò nípa fífi ṣe ètùtù fún wọn níwájú Olúwa.
Ino ty tsy nihinana’ areo i engan-kakeoy amy toe-miavakey ao? Miavake izay vaho natolon’ Añahare anaha­reo hivave ty hìla’ i màroy hijebañañe iareo añatrefa’ Iehovà.
18 Níwọ́n ìgbà tí ẹ kò mú ẹ̀jẹ̀ rẹ̀ wá sí Ibi Mímọ́, ẹ̀ bá ti jẹ ewúrẹ́ náà ní agbègbè Ibi Mímọ́ bí mo ṣe pa á láṣẹ.”
Inao, tsy nasese amy toe-miavakey ty lio’e, aa le ho nihinana’ areo amy toe-miavakey ao, amy nandiliakoy.
19 Aaroni sì dá Mose lóhùn pé, “Lónìí tí wọ́n rú ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀ àti ẹbọ sísun wọn níwájú Olúwa ni irú èyí tún ṣẹlẹ̀ sí mi. Ǹjẹ́ inú Olúwa yóò wá dùn bí mo bá jẹ ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀ lónìí?”
Le hoe t’i Aharone amy Mosè: Ingo te binanabana’ iareo anindroany i engan-kakeo’ iareoy naho o fisoroña’ iareo añatrefa’ Iehovào; aa i hene nizo ahiko anianiy, naho nihinanako i engan-kakeoy anindroany ampiva­zohoa’ Iehovà, ho ni-nò’e hao?
20 Nígbà tí Mose gbọ́ èyí, ọkàn rẹ̀ balẹ̀.
Ie jinanji’ i Mosè izay le nisoa am-pihaino’e ao.

< Leviticus 10 >