< Leviticus 10 >
1 Nadabu àti Abihu tí í ṣe ọmọ Aaroni sì mú àwo tùràrí kọ̀ọ̀kan, wọ́n fi iná àti tùràrí sínú rẹ̀, wọ́n sì rú iná àjèjì níwájú Olúwa, èyí tó lòdì sí àṣẹ Olúwa.
Na rĩrĩ, ariũ a Harũni, nĩo Nadabu na Abihu, nĩmoire ngĩo ciao cia ũbani, magĩciĩkĩra mwaki na makĩongerera ũbani; na makĩrehe mwaki ũteetĩkĩrĩtio mbere ya Jehova, ũrĩa wareganĩte na watho wa Jehova.
2 Torí èyí, iná jáde láti ọ̀dọ̀ Olúwa, ó sì jó wọn pa, wọ́n sì kú níwájú Olúwa.
Nĩ ũndũ ũcio mwaki ũkiuma kũrĩ Jehova, ũkĩmaniina, nao magĩkuĩra o hau mbere ya Jehova.
3 Mose sì sọ fún Aaroni pé, “Ohun tí Olúwa ń sọ nípa rẹ̀ nìyìí nígbà tó wí pé, “‘Ní àárín àwọn tó súnmọ́ mi, Èmi yóò fi ara mi hàn ní mímọ́ ojú gbogbo ènìyàn Ní a ó ti bu ọlá fún mi.’” Aaroni sì dákẹ́.
Ningĩ Musa akĩĩra Harũni atĩrĩ, “Ũndũ ũyũ nĩguo Jehova aaririe, rĩrĩa oigire atĩrĩ: “‘Gatagatĩ-inĩ ka andũ arĩa marĩĩthengagĩrĩra, nĩndĩrĩĩonanagia ndĩ mũtheru; nĩndĩrĩtĩĩagwo mbere ya andũ othe.’” Nake Harũni agĩkira ki.
4 Mose pe Miṣaeli àti Elsafani ọmọ Usieli tí í ṣe arákùnrin Aaroni, ó sọ fún wọn pé, “Ẹ wá, kí ẹ sì gbé àwọn arákùnrin yín jáde kúrò níwájú ibi mímọ́ lọ sí ẹ̀yìn ibùdó.”
Musa agĩĩta Mishaeli na Elizafani, ariũ a Uzieli, ithe mũnini wa Harũni, akĩmeera atĩrĩ, “Ũkai haha, muoye ciimba cia ariũ a ithe wanyu, mũciumie nja ya kambĩ haraihu na itoonyero rĩa handũ-harĩa-haamũre.”
5 Wọ́n sì wá gbé wọn, pẹ̀lú ẹ̀wù àwọ̀tẹ́lẹ̀ wọn ní ọrùn wọn lọ sí ẹ̀yìn ibùdó bí Mose ti sọ.
Nĩ ũndũ ũcio magĩũka, makĩmakuua, marĩ o na kanjũ ciao, makĩmatwara nja ya kambĩ, o ta ũrĩa Musa aathanĩte.
6 Mose sọ fún Aaroni àti àwọn ọmọ rẹ̀ yòókù, Eleasari àti Itamari pé, “ẹ má ṣe ṣọ̀fọ̀ nípa ṣíṣe aláìtọ́jú irun yín tàbí kí ẹ ṣí orí yín sílẹ̀, ẹ kò sì gbọdọ̀ ya aṣọ, bí ẹ bá ṣe bẹ́ẹ̀, ẹ ó kùú, Olúwa yóò sì bínú sí gbogbo ìjọ ènìyàn. Ṣùgbọ́n àwọn ẹbí yín, àti gbogbo ilé Israẹli le è ṣọ̀fọ̀ lórí àwọn tí Olúwa fi iná parun.
Ningĩ Musa akĩĩra Harũni na ariũ ake Eleazaru na Ithamaru atĩrĩ, “Mũtikanareke njuĩrĩ cianyu ciikare itarĩ njanũre, kana mũtembũrange nguo cianyu, nĩguo mũtigakue, na mũtũme Jehova arakarĩre kĩrĩndĩ gĩkĩ gĩothe. No rĩrĩ, rekei andũ a nyũmba yanyu, nyũmba yothe ya Isiraeli, macakaĩre acio Jehova aniinĩte na mwaki.
7 Ẹ má ṣe kúrò ní ẹnu-ọ̀nà àgọ́ ìpàdé, bí ẹ bá kúrò níbẹ̀, ẹ ó kù ú, nítorí pé òróró ìtasórí Olúwa wà lórí yín.” Wọ́n sì ṣe bí Mose ti wí.
Mũtikehere itoonyero-inĩ rĩa Hema-ya-Gũtũnganwo nĩguo mũtigakue, tondũ nĩmũitĩrĩirio maguta ma Jehova.” Nĩ ũndũ ũcio magĩĩka o ta ũrĩa Musa aameerire.
8 Olúwa sì sọ fún Aaroni pé.
Ningĩ Jehova akĩĩra Harũni atĩrĩ,
9 “Ìwọ àti àwọn ọmọ rẹ̀ kò gbọdọ̀ mu ọtí wáìnì tàbí ọtí líle mìíràn nígbàkígbà tí ẹ bá n lọ inú àgọ́ ìpàdé, bí ẹ bá ṣe bẹ́ẹ̀, ẹ ó kù ú, èyí jẹ́ ìlànà títí láé fún un yín láti ìrandíran.
“Wee na ariũ aku-rĩ, mũtikananyue ndibei kana kĩndũ o gĩothe kĩngĩtũma mũndũ arĩĩo rĩrĩa rĩothe mũrĩtoonyaga Hema-ya-Gũtũnganwo, nĩguo mũtigakue. Ũndũ ũcio nĩ ũtuĩke watho mwandĩke wa gũtũũra nginya njiarwa-inĩ iria igooka.
10 Ẹ gbọdọ̀ mọ ìyàtọ̀ láàrín mímọ́ àti àìmọ́, láàrín èérí àti àìléèérí.
No nginya mũkũũranage indo iria nyamũre na iria itarĩ nyamũre, o na iria irĩ thaahu na iria itarĩ thaahu,
11 Ẹ gbọdọ̀ kọ́ àwọn ara Israẹli ní gbogbo àṣẹ tí Olúwa fún wọn láti ẹnu Mose.”
na no nginya mũrutage andũ a Isiraeli watho wothe wa kũrũmagĩrĩrwo, ũrĩa Jehova aamaheire na kanua ka Musa.”
12 Mose sì sọ fún Aaroni, Eleasari àti Itamari àwọn ọmọ rẹ̀ yòókù pé, “Ẹ mú ẹbọ ohun jíjẹ tó ṣẹ́kù láti inú ẹbọ àfinásun sí Olúwa, kí ẹ jẹ ẹ́ láìní ìwúkàrà nínú, lẹ́gbẹ̀ẹ́ pẹpẹ nítorí ó jẹ́ mímọ́ jùlọ.
Ningĩ Musa akĩĩra Harũni na ariũ ake arĩa maatigaire, nĩo Eleazaru na Ithamaru, atĩrĩ, “Oyai iruta rĩu rĩa mũtu rĩatigarĩte kuuma harĩ maruta marĩa maarutĩirwo Jehova ma gũcinwo na mwaki, mũrĩrĩe rĩthondeketwo rĩtarĩ na ndawa ya kũimbia, mũrĩĩre hau mwena-inĩ wa kĩgongona, nĩ ũndũ nĩ iruta rĩtheru mũno makĩria.
13 Ẹ jẹ́ ní ibi mímọ́, nítorí pé òun ni ìpín rẹ àti ti àwọn ọmọ rẹ nínú ẹbọ tí a finá sun sí Olúwa nítorí pé bẹ́ẹ̀ ni mo ṣe pa á láṣẹ.
Mũrĩrĩĩre handũ hatheru, tondũ nĩ rwĩga rwaku na rwa ariũ aku kuuma maruta-inĩ marĩa marutĩirwo Jehova ma gũcinwo na mwaki; tondũ ũguo nĩguo njathĩtwo.
14 Ṣùgbọ́n ìwọ àti àwọn ọmọkùnrin àti àwọn ọmọbìnrin rẹ le jẹ igẹ̀ ẹran tí a fì níwájú Olúwa àti itan tí wọ́n gbé síwájú Olúwa, kí ẹ jẹ wọ́n ní ibi tí a kà sí mímọ́, èyí ni a ti fún ìwọ àti àwọn ọmọ rẹ gẹ́gẹ́ bí ìpín yín nínú ẹbọ àlàáfíà àwọn ara Israẹli.
No wee, na ariũ aku na airĩtu aku no mũrĩe gĩthũri kĩrĩa gĩathũngũthĩtio, na kĩero kĩrĩa kĩaheanĩtwo. Mũcirĩĩre handũ hatarĩ thaahu; icio nĩwe ũheetwo hamwe na ciana ciaku ituĩke rwĩga rwanyu rwa maruta ma ũiguano ma andũ a Isiraeli.
15 Itan tí wọ́n mú wá àti igẹ̀ ẹran tí ẹ fì ni ẹ gbọdọ̀ mú wá pẹ̀lú ọ̀rá ẹbọ tí a finá sun láti le è fì wọ́n níwájú Olúwa bí ẹbọ fífì. Èyí yóò sì jẹ́ ìpín tìrẹ àti ti àwọn ọmọ rẹ nígbà gbogbo bí Olúwa ṣe pàṣẹ.”
Kĩero kĩu kĩarutĩtwo, na gĩthũri kĩu gĩathũngũthĩtio, no nginya irehanĩrio na maguta ma maruta ma gũcinwo na mwaki, na ithũngũthio mbere ya Jehova, ituĩke igongona rĩa gũthũngũthio. Rũrũ nĩruo rwĩga rwaku na rwa ciana ciaku hĩndĩ ciothe, o ta ũrĩa Jehova aathanĩte.”
16 Nígbà tí Mose wádìí nípa ewúrẹ́ ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀ tó sì rí i pé wọ́n ti sun ún, ó bínú sí Eleasari àti Itamari, àwọn ọmọ Aaroni yòókù, ó sì béèrè pé,
Rĩrĩa Musa oorĩrĩirie ũhoro wa mbũri ĩrĩa ya iruta rĩa kũhoroherio mehia, na akĩmenya atĩ nĩyarĩkĩtie gũcinwo biũ-rĩ, akĩrakarĩra Eleazaru na Ithamaru, ariũ a Harũni arĩa maatigaire, akĩmooria atĩrĩ,
17 “Èéṣe tí ẹ kò jẹ ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀ náà ní agbègbè ibi mímọ́? Ó jẹ́ mímọ́ jùlọ, a fi fún yín láti lè mú ẹ̀ṣẹ̀ ìjọ ènìyàn kúrò nípa fífi ṣe ètùtù fún wọn níwájú Olúwa.
“Nĩ kĩĩ kĩgiririe mũrĩĩre iruta rĩu rĩa kũhoroheria mehia handũ-harĩa-haamũre? Nĩ iruta itheru mũno makĩria; mwaheirwo iruta rĩu rĩa kweheragia mahĩtia ma kĩrĩndĩ rĩrĩa mũkũmahoroheria hau mbere ya Jehova.
18 Níwọ́n ìgbà tí ẹ kò mú ẹ̀jẹ̀ rẹ̀ wá sí Ibi Mímọ́, ẹ̀ bá ti jẹ ewúrẹ́ náà ní agbègbè Ibi Mímọ́ bí mo ṣe pa á láṣẹ.”
Kuona atĩ thakame yayo ndĩnatoonyio thĩinĩ wa Handũ-hau-Hatheru-rĩ, nĩmũkwagĩrĩirwo nĩkũrĩĩra mbũri ĩyo Handũ-hau-Haamũre, o ta ũrĩa ndaathanire.”
19 Aaroni sì dá Mose lóhùn pé, “Lónìí tí wọ́n rú ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀ àti ẹbọ sísun wọn níwájú Olúwa ni irú èyí tún ṣẹlẹ̀ sí mi. Ǹjẹ́ inú Olúwa yóò wá dùn bí mo bá jẹ ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀ lónìí?”
Harũni agĩcookeria Musa, akĩmwĩra atĩrĩ, “Ũmũthĩ nĩmarutire igongona rĩao rĩa kũhoroherio mehia, na iruta rĩao rĩa njino hau mbere ya Jehova, no maũndũ ta macio o na niĩ manangora. Ingĩkũrĩĩte iruta rĩu rĩa kũhoroherio mehia ũmũthĩ-rĩ, ũndũ ũcio nĩũngĩkenirie Jehova?”
20 Nígbà tí Mose gbọ́ èyí, ọkàn rẹ̀ balẹ̀.
Hĩndĩ ĩrĩa Musa aiguire ũhoro ũcio-rĩ, akĩiganĩra.