< Leviticus 1 >

1 Olúwa sì pe Mose, ó sì bá a sọ̀rọ̀ láti inú àgọ́ àjọ. Ó wí pé,
Hina Gode da Ea Abula Diasuga esala, Mousesema misa: ne wele sia: i. E da Mousesema amo gobele salasu iasu sema olelei.
2 “Bá àwọn ọmọ Israẹli sọ̀rọ̀ kí o sì wí fún wọn pé, ‘Bí ẹnikẹ́ni nínú yín bá mú ọrẹ ẹbọ wá fún Olúwa, kí ọrẹ ẹbọ yín jẹ́ ẹran ọ̀sìn láti inú agbo ẹran tàbí láti inú ọ̀wọ́ ẹran.
“Isala: ili dunu da gobele salasu hou hamomusa: dawa: sea, ilia da agoane hamoma: ne sia: ma, ‘Nowa da ohe gobele salasu imunusa: dawa: sea, e da ea bulamagau afae o sibi afae o goudi afae lale ima: mu.
3 “‘Bí ọrẹ ẹbọ náà bá jẹ́ ẹbọ sísun láti inú agbo ẹran kí òun kí ó mú akọ màlúù tí kò lábùkù. Ó sì gbọdọ̀ mú un wá sí ẹnu-ọ̀nà àgọ́ àjọ kí ó ba à lè jẹ́ ìtẹ́wọ́gbà níwájú Olúwa
E da ea bulamagau afae gobele salimusa: dawa: sea, e da bulamagau gawali afae ida: iwane gala, ledo hamedafa gala, gaguli misa: ne sia: ma. Hina Gode da amo dunu hahawane gousa: ma: ne, e da amo bulamagau gawali, Gode Ea Abula Diasu amo ea holeiga ima: ne sia: ma.
4 kí ó gbé ọwọ́ rẹ̀ lé orí ẹbọ sísun náà yóò sì jẹ́ ìtẹ́wọ́gbà dípò o rẹ̀, yóò sì jẹ́ ètùtù fún un.
Amo dunu da ea lobo amo bulamagau gawali ea dialuma da: iya ligisima: mu. Amasea, Hina Gode da amo bulamagau gobele salasu liligi amo dunu ea wadela: i hou fadegale fasima: ne sia: mu.
5 Kí ó pa ọ̀dọ́ akọ màlúù náà níwájú Olúwa, lẹ́yìn náà ni àwọn àlùfáà tí í ṣe ọmọ Aaroni yóò gbé ẹ̀jẹ̀ ẹran náà, wọn yóò sì wọ́n ẹ̀jẹ̀ náà yí pẹpẹ tí ó wà ní ẹnu-ọ̀nà àgọ́ àjọ ká.
E da amogawi bulamagau medole legema: mu. Amola Elane ea gobele salasu dunu ilia da bulamagau ea maga: me lale, Hina Godema imunu. Amasea, ilia da amo maga: me oloda (amo da Abula Diasu ea holeiga diala) amo ea la: idi biyadu gala amoga sogaga: la: gaganomu.
6 Òun yóò bó awọ ara ẹbọ sísun náà, òun yóò sì gé e sí wẹ́wẹ́.
Amasea, gobele salasu iabe dunu, e da bulamagau ea gadofo houga: le, ea da: i hodo dadega: mu.
7 Àwọn ọmọ Aaroni tí í ṣe àlùfáà yóò fi iná sí orí pẹpẹ, wọn yóò sì to igi sórí pẹpẹ náà.
Amola gobele salasu dunu ilia da oloda da: iya lalu habei gilisili, didima: mu.
8 Lẹ́yìn náà ni àwọn ọmọ Aaroni tí í ṣe àlùfáà yóò tó ègé ẹran náà, pẹ̀lú orí àti ọ̀rá rẹ̀ sí orí igi tó ń jó lórí pẹpẹ.
Ilia da amo ohe ea dadega: i fifi (huluane, dialuma amola sefe) laluga ligisimu.
9 Kí ó fi omi sàn nǹkan inú àti àwọn ẹsẹ̀ rẹ̀, kí àlùfáà sì sun gbogbo rẹ̀ lórí pẹpẹ, ó jẹ́ ọrẹ ẹbọ sísun, ọrẹ ẹbọ tí a fi iná ṣe, àní òórùn dídùn sí Olúwa.
Gobele salasu iabe dunu da ohe ea iga amola emo amo dodofemu. Amasea, gobele salasu ouligisu dunu da amo liligi huluanedafa oloda da: iya gobesimu. Hina Gode da amo ha: i manu gobele salasu iasu ea gabusiga: hahawane naba.
10 “‘Bí ọrẹ ẹbọ náà bá jẹ́ ẹbọ sísun láti inú ọ̀wọ́ ẹran, láti ara àwọn àgùntàn tàbí ewúrẹ́ tàbí àgùntàn, kí ó mú akọ tí kò lábùkù,
Isala: ili dunu afae da sibi o goudi gobele salimusa: dawa: sea, e da gawali ida: iwane gala, ledo hamedei, ilegema: ne sia: ma.
11 kí ó pa á ní apá àríwá pẹpẹ níwájú Olúwa, kí àwọn ọmọ Aaroni tí í ṣe àlùfáà sì wọ́n ẹ̀jẹ̀ rẹ̀ yí gbogbo ẹ̀gbẹ́ pẹpẹ náà ká.
E da amo ohe oloda la: idi gagoe (north) amoga medole legemu. Amasea, gobele salasu dunu da ea maga: me oloda ea la: idi biyaduyale gala amoga sogaga: la: gaganoma: mu.
12 Kí ó gé e sí wẹ́wẹ́, kí àlùfáà sì to ègé ẹran náà; orí àti ọ̀rá rẹ̀ sí orí igi tó ń jó lórí pẹpẹ.
Amasea, dunu hi da amo ohe ea da: i hodo dadega: le, gobele salasu ouligisu dunu da dadega: i fifi (huluane, amola dialuma amola sefe) amo laluma gobesimu.
13 Kí ó fi omi ṣan nǹkan inú àti àwọn ẹsẹ̀ rẹ̀, kí àlùfáà sì gbé gbogbo rẹ̀ wá láti sun lórí pẹpẹ. Ó jẹ́ ẹbọ sísun tí a fi iná ṣe, àní òórùn dídùn sí Olúwa.
Gobele salasu iabe dunu da amo ohe ea iga amola emo dodofemu. Amasea, gobele salasu ouligisu dunu da amo gobele salasu Hina Godema ianu, oloda da: iya laluma gobesimu. Hina Gode da amo ha: i manu gobele salasu ea gabusiga: hahawane naba.
14 “‘Bí ó bá sì ṣe pé ti ẹyẹ ni ẹbọ sísun ọrẹ ẹbọ rẹ̀ sí Olúwa, ǹjẹ́ kí ó mú ọrẹ ẹbọ rẹ̀ wá nínú àdàbà tàbí ọmọ ẹyẹlé.
Isala: ili dunu da sio amo gobele salasu imunusa: dawa: sea, e da dafe sio o musuni gaguli misa: ne sia: ma.
15 Kí àlùfáà mu wá sí ibi pẹpẹ, kí ó yín in lọ́rùn, kí ó sì sun ún lórí pẹpẹ, kí ó sì ro ẹ̀jẹ̀ rẹ̀ ní ẹ̀gbẹ́ pẹpẹ.
Gobele salasu ouligisu dunu da amo sio oloda amogawi Hina Godema ianu, ea asogoa dugini, ea dialuma amo oloda da: iya gobesimu. E da ea maga: me oloda beba: le soga: sisimu.
16 Kí ó yọ àjẹsí ẹyẹ náà pẹ̀lú gbogbo ohun tí ó wà nínú rẹ̀, kí ó gbe lọ ṣí apá ìlà-oòrùn pẹpẹ níbi tí eérú wà.
E da sio ea wa amola amo ganodini liligi dialebe fadegale, oloda ea gusudili la: idiga (nasubu ligisisu) amoga galagamu.
17 Kí ó gbá apá rẹ̀ méjèèjì mú, kí ó fà á ya, ṣùgbọ́n kí ó má ya á tan pátápátá. Lẹ́yìn náà ni àlùfáà yóò sun ún lórí igi tí ó ń jó lórí pẹpẹ, ẹbọ sísun ni ọrẹ tí a fi iná ṣe, àní òórùn dídùn sí Olúwa.
E da sio ea ougia aduna dodobole gaguli, amo mae fadegale, ea da: i hodo dudugale, mae dadega: le, amo oloda da: iya gobesimu. Hina Gode da amo ha: i manu gobele salasu ea gabusiga: hahawane naba.

< Leviticus 1 >