< Lamentations 5 >
1 Rántí, Olúwa, ohun tí ó ṣẹlẹ̀ sí wa; wò ó, kí o sì rí ìtìjú wa.
Ao Awurade, kae deɛ aba yɛn so; hwɛ, na hunu yɛn animguaseɛ.
2 Àwọn ohun ìní wa ti di ti àlejò, ilé wa ti di ti àjèjì.
Wɔadane yɛn agyapadeɛ ama ahɔhoɔ, wɔde yɛn afie ama ananafoɔ.
3 Àwa ti di aláìní òbí àti aláìní baba, àwọn ìyá wa ti di opó.
Yɛayɛ nwisiaa na yɛnni agyanom, yɛn maamenom ayɛ sɛ akunafoɔ.
4 A gbọdọ̀ ra omi tí à ń mu; igi wa di títà fún wa.
Ɛsɛ sɛ yɛtɔ nsuo a yɛnom; yɛbɛnya nnyina a, gye sɛ yɛtɔ.
5 Àwọn tí ó ń lé wa súnmọ́ wa; àárẹ̀ mú wa àwa kò sì rí ìsinmi.
Wɔn a wɔtaa yɛn no abɛn yɛn pɛɛ; Yɛabrɛ na yɛnnya ahomegyeɛ.
6 Àwa jọ̀wọ́ ara wa fún Ejibiti àti Asiria láti rí oúnjẹ tó tó jẹ.
Yɛde yɛn ho maa Misraim ne Asiria sɛdeɛ yɛbɛnya aduane a ɛbɛso yɛn.
7 Àwọn baba wa ti ṣẹ̀, wọn kò sì ṣí mọ́, àwa sì ń ru ìjìyà ẹ̀ṣẹ̀ wọn.
Yɛn agyanom yɛɛ bɔne, na wɔnni hɔ bio, na yɛn na wɔn asotwe abɛda yɛn so.
8 Àwọn ẹrú ń jẹ ọba lórí wa, kò sì ṣí ẹni tí yóò gbà wá lọ́wọ́ wọn.
Nkoa di yɛn so, na obiara nni hɔ a ɔbɛgye yɛn afiri wɔn nsam.
9 Àwa ń rí oúnjẹ wa nínú ewu ẹ̀mí wa nítorí idà tí ó wà ní aginjù.
Yɛde yɛn nkwa bɔ afɔdeɛ de pɛ yɛn anoduane, akofena a ɛwɔ ɛserɛ so no enti.
10 Ẹran-ara wa gbóná bí ààrò, ebi sì yó wa bí àárẹ̀.
Yɛn honam adɔ sɛ fononoo. Ɛkɔm ama huraeɛ abɔ yɛn.
11 Wọ́n ti fipá bá àwọn obìnrin wa lòpọ̀ ní Sioni, àti àwọn wúńdíá ti o wa ní ìlú Juda.
Wɔato mmaa monnaa wɔ Sion, ne mmaabunu a wɔwɔ Yuda nkuro so.
12 Àwọn ọmọ ọbakùnrin ti di síso sókè ní ọwọ́ wọn; kò sí ìbọ̀wọ̀ fún àgbàgbà mọ́.
Wɔkyekyere mmapɔmma nsa na wɔasɛn wɔn; wɔmmfa anidie mma mpanimfoɔ.
13 Àwọn ọ̀dọ́mọkùnrin wa ru òkúta; àwọn ọmọkùnrin sì ń ṣàárẹ̀ lábẹ́ ẹrù igi.
Mmeranteɛ yɛ adwuma den wɔ ayuoyammoɔ so; na mmerantewaa nan toto wɔ nnyina duruduru ase.
14 Àwọn àgbàgbà ti lọ kúrò ní ẹnu-bodè ìlú; àwọn ọ̀dọ́mọkùnrin sì dákẹ́ orin wọn.
Mpanimfoɔ ntena kuropɔn apono ano bio; mmeranteɛ agyae wɔn nnwontoɔ.
15 Ayọ̀ ti ṣáko ní ọkàn wa; ọ̀fọ̀ sì ti dúró bí ijó fún wa.
Ahosɛpɛ afiri yɛn akoma mu; yɛn asa adane agyaadwotwa.
16 Adé ti ṣí kúrò ní orí wa ègbé ni fún wa, nítorí a ti ṣẹ̀.
Ahenkyɛ afiri yɛn tiri so. Yɛn ara, yɛnnue sɛ yɛayɛ bɔne!
17 Nítorí èyí, àárẹ̀ mú ọkàn wa, nítorí èyí, ojú wa sì ṣú.
Yei enti yɛn akoma atɔ piti, yeinom enti yɛn ani so ayɛ kusuu
18 Fún òkè Sioni tí ó ti di ahoro lórí rẹ̀ àwọn kọ̀lọ̀kọ̀lọ̀ sì ń rìn kiri.
wɔ Sion bepɔ a ada mpan na sakraman nenam soɔ no enti.
19 Ìwọ, Olúwa, jẹ ọba títí láé; ìjọba rẹ dúró láti ìran kan dé ìran mìíràn.
Wo, Ao Awurade, di ɔhene afebɔɔ; wʼahennwa firi awoɔ ntoatoasoɔ kɔsi awoɔ ntoatoasoɔ.
20 Kí ló dé tí o ń gbàgbé wa ní gbogbo ìgbà? Kí ló dé tí o fi kọ̀ wá sílẹ̀ fún ọjọ́ pípẹ́?
Adɛn enti na wo werɛ firi yɛn daa yi? Adɛn enti na wagya yɛn mmerɛ tenten mu yi?
21 Mú wa padà sí ọ̀dọ̀ rẹ, Olúwa, kí àwa kí ó le padà; mú ọjọ́ wa di tuntun bí ìgbàanì,
Ka yɛn bata wo ho bio, Ao, Awurade, na yɛatumi aba wo nkyɛn; yɛ yɛn nna foforɔ sɛ tete no
22 àyàfi tí o bá ti kọ̀ wá sílẹ̀ pátápátá tí ìbínú rẹ sí wa sì kọjá ìwọ̀n.
agye sɛ wapo yɛn koraa anaa sɛ wo bo afu yɛn mmorosoɔ.