< Lamentations 4 >

1 Báwo ni wúrà ṣe sọ ògo dídán rẹ̀ nù, wúrà dídára di àìdán! Òkúta ibi mímọ́ wá túká sí oríta gbogbo òpópó.
Hĩ! Kaĩ thahabu ĩyo nĩĩthirĩte ũkengu wayo-ĩ, thahabu ĩrĩa therie kaĩ ĩrĩ gũthita-ĩ! Tũhiga twa goro tũrĩa twamũre nĩtũhurunjĩtwo magomano-inĩ ma njĩra ciothe.
2 Báwo ni àwọn ọ̀dọ́mọkùnrin Sioni tí ó ṣe iyebíye, tí wọ́n fi wúrà dídára ṣe wá dàbí ìkòkò amọ̀ lásán iṣẹ́ ọwọ́ amọ̀kòkò!
Ariũ a Zayuni arĩa me bata, arĩa rĩmwe mangĩaringithanirio na thogora wa thahabu, kaĩ rĩu moonagwo ta nyũngũ cia rĩũmba-ĩ, o ta wĩra wa moko ma mũũmbi!
3 Àwọn ajáko pèsè ọmú wọn fún ìtọ́jú àwọn ọmọ wọn, ṣùgbọ́n àwọn ènìyàn mi wá láì lọ́kàn bí ògòǹgò ní aginjù.
O na mbwe nĩciongithagia ciana ciacio, no andũ akwa matuĩkĩte andũ matarĩ tha, o ta nyaga cia werũ-inĩ.
4 Nítorí òǹgbẹ, ahọ́n àwọn ọmọ ọwọ́ lẹ̀ mọ́ òkè ẹnu wọn; àwọn ọmọdé bẹ̀bẹ̀ fún oúnjẹ, ṣùgbọ́n kò sí ẹni tí ó fi fún wọn.
Rũrĩmĩ rwa gakenge rũnyiitanĩte na karakara nĩ ũndũ wa kũnyoota; twana tũhooyaga irio, no gũtirĩ mũndũ ũtũheaga.
5 Àwọn tí ó ń jẹ ohun dáradára di òtòṣì ní òpópó. Àwọn tí a fi aṣọ dáradára wọ̀ ni wọ́n sùn ní orí òkìtì eérú.
Andũ arĩa rĩmwe maarĩĩaga irio njega, rĩu maikaraga njĩra-inĩ mekonotete, arĩa maarerirwo makĩhumbagwo nguo cia rangi wa ndathi-rĩ, rĩu makomaga ciara-inĩ cia mũhu.
6 Ìjìyà àwọn ènìyàn mi tóbi ju ti Sodomu lọ, tí a sí ní ipò ní òjijì láìsí ọwọ́ láti ràn án lọ́wọ́.
Iherithia rĩa andũ akwa nĩ inene gũkĩra rĩa itũũra rĩa Sodomu, rĩrĩa rĩangʼaũranirio o rĩmwe, gũtarĩ guoko kwarĩteithirie.
7 Ọmọ ọba ọkùnrin wọn mọ́ ju òjò-dídì, wọ́n sì funfun ju wàrà lọ wọ́n ni ìtọ́jú bí iyùn pupa, ìrísí wọn dàbí safire.
Anene akuo maatherete gũkĩra tharunji, na makeerũha gũkĩra iria, maarĩ atune mĩĩrĩ gũkĩra ruru ĩrĩa ndune, magakĩhaana ta kahiga ka goro karĩa getagwo yakuti.
8 Ṣùgbọ́n nísinsin yìí wọ́n dúdú ju èédú; wọn kò sì dá wọn mọ̀ ní òpópó. Ara wọn hun mọ́ egungun; ó sì gbẹ bí igi gbígbẹ.
No rĩu mairĩte o na gũkĩra mbiro; matikũũrĩkanaga marĩ njĩra-inĩ. Ikonde cia mĩĩrĩ yao ciũmanĩrĩire na mahĩndĩ; ciumĩte o ta rũthanju.
9 Àwọn tí ó kù nípasẹ̀ idà sàn ju àwọn tí ìyàn pa; tí ó wọ àkísà ebi, tí ó ń ṣòfò fún àìní oúnjẹ láti inú pápá.
Kaba arĩa mooragagwo na rũhiũ rwa njora, kũrĩ arĩa makuuaga nĩ ngʼaragu; matooragio nĩkũhũũta, makamoca nĩ ũndũ wa kwaga irio cia kuuma mũgũnda.
10 Pẹ̀lú ọwọ́ àwọn obìnrin aláàánú ni wọ́n ṣe ọmọ wọn jẹ tí ó di oúnjẹ fún wọn nígbà tí a pa àwọn ènìyàn mi run.
Moko ma andũ-a-nja arĩa marĩ tha nĩmarugire ciana ciao ene, igĩtuĩka irio ciao hĩndĩ ĩyo andũ akwa manangirwo.
11 Olúwa ti fi ihò kíkún fún ìbínú rẹ̀; ó sì tú ìbínú gbígbóná rẹ̀ jáde. Ó da iná ní Sioni tí ó jó ìpìlẹ̀ rẹ̀ run.
Jehova nĩarekereirie mangʼũrĩ make biũ; aitũrũrĩte marakara make mahiũ. Nĩakĩtie mwaki kũu Zayuni ũrĩa ũcinĩte mĩthingi yakuo.
12 Àwọn ọba ayé kò gbàgbọ́, tàbí àwọn ènìyàn ayé, wí pé àwọn ọ̀tá àti aninilára le wọ odi ìlú Jerusalẹmu.
Athamaki a thĩ matingĩetĩkirie, o na kana kĩrĩndĩ o na kĩmwe gĩa gũkũ thĩ, atĩ thũ na amuku nĩmangĩahotire gũtoonya ihingo cia Jerusalemu.
13 Èyí ṣẹlẹ̀ nítorí ẹ̀ṣẹ̀ àwọn wòlíì àti àìṣedéédéé àwọn olórí àlùfáà, tí ó ta ẹ̀jẹ̀ àwọn olódodo sílẹ̀ láàrín rẹ̀.
No ũndũ ũcio wekĩkire nĩ ũndũ wa mehia ma anabii akuo, na mawaganu ma athĩnjĩri-Ngai akuo arĩa manaita thakame ya andũ arĩa athingu kũu thĩinĩ.
14 Nísinsin yìí wọ́n ń rìn kiri ní òpópó bí ọkùnrin tí ó fọ́jú. Ẹ̀jẹ̀ ara wọn sọ wọ́n di àbàwọ́n tí kò sẹ́ni tó láyà láti fọwọ́ kan aṣọ wọn.
Rĩu maturuuraga njĩra-inĩ ta andũ atumumu. Mathaahĩtio nĩ thakame ũũ atĩ gũtirĩ mũndũ o na ũmwe ũngĩgeria kũhutia nguo ciao.
15 “Lọ kúrò! Ẹ̀yin di aláìmọ́!” ni àwọn ènìyàn ń kígbe sí wọn. “Ẹ lọ! Ẹ lọ! Ẹ má ṣe fọwọ́ kàn wá!” Àwọn ènìyàn láàrín orílẹ̀-èdè wí pé, “Wọn kì yóò tẹ̀dó síbí mọ́.”
Andũ mamakayagĩrĩria, makoiga atĩrĩ, “Thiĩi nakũu! Mũrĩ na thaahu! Thiĩi! Thiĩi! Mũtigatũhutie!” Ningĩ moora na maatuĩka orũũri, makeerwo atĩrĩ kũu ndũrĩrĩ-inĩ, “Matingĩikara gũkũ rĩngĩ.”
16 Olúwa ti tú wọn ká fúnra rẹ̀; kò sí bojútó wọn mọ́. Kò sí ọ̀wọ̀ fún olórí àlùfáà mọ́, àti àánú fún àwọn àgbàgbà.
Jehova we mwene nĩwe ũmahurunjĩte; nĩatigĩte kũmarũmbũiya. Athĩnjĩri-Ngai matiheagwo gĩtĩĩo, o na makarega gũtuga athuuri.
17 Síwájú sí i, ojú wa kùnà fún wíwo ìrànlọ́wọ́ asán; láti orí ìṣọ́ wa ni à ń wò fún orílẹ̀-èdè tí kò le gbà wá là.
Makĩria ma ũguo-rĩ, maitho maitũ nĩmathirire hinya, o tũcũthĩrĩirie ũteithio ũrĩa tũtoonire; kuuma mĩthiringo iitũ ĩrĩa mĩraihu-rĩ, twetereire rũrĩrĩ rũtangĩahotire gũtũhonokia.
18 Wọ́n ń ṣọ́ wa kiri, àwa kò sì le rìn ní òpópó wa mọ́. Òpin wa ti súnmọ́, ọjọ́ wa sì níye nítorí òpin wa ti dé.
Andũ maatũcemaga ikinya gwa ikinya, nĩ ũndũ ũcio tũtingĩathiĩrĩire njĩra-inĩ ciitũ. Ithirĩro riitũ rĩgĩkuhĩrĩria, namo matukũ maitũ maarĩ matare, nĩgũkorwo ithirĩro riitũ nĩrĩakinyĩte.
19 Àwọn tí ń lé wa yára ju idì ojú ọ̀run lọ; wọ́n lé wa ní gbogbo orí òkè wọ́n sì gẹ̀gùn dè wá ní aginjù.
Andũ arĩa matũingatithĩtie-rĩ, maarĩ na ihenya gũkĩra nderi irĩ rĩera-inĩ; maatũhanyũkagĩria irĩma-inĩ, na magatuoheria werũ-inĩ.
20 Ẹni àmì òróró Olúwa, èémí ìyè wa, ni wọ́n fi tàkúté wọn mú. Àwa rò pé lábẹ́ òjìji rẹ̀ ni àwa yóò máa gbé láàrín orílẹ̀-èdè gbogbo.
Mũndũ ũrĩa mũitĩrĩrie maguta nĩ Jehova, o we ũrĩa warĩ ta mĩhũmũ iitũ-rĩ, nĩagwatirio nĩ mĩtego yao. Tweciiragia atĩ tũrĩ kĩĩruru-inĩ gĩake-rĩ, no tũtũũre gatagatĩ ka ndũrĩrĩ.
21 Ẹ yọ̀ kí inú yín sì dùn, ẹ̀yin ọmọbìnrin Edomu, ẹ̀yin tó ń gbé ní ilẹ̀ Usi. Ṣùgbọ́n, a ó gbé ago náà kọjá sọ́dọ̀ rẹ pẹ̀lú; ìwọ yóò yó bí ọ̀mùtí, ìwọ yóò sì rìn ní ìhòhò.
Kena na ũcanjamũke, wee Mwarĩ wa Edomu, o wee ũtũũraga bũrũri wa Uzu. No rĩrĩ, o nawe gĩkombe gĩkĩ nĩgĩgagũkora; ũgaakĩnyuĩra ũrĩĩo, na ũrutwo nguo, ũtigwo njaga.
22 Ìwọ ọmọbìnrin Sioni, ìjìyà rẹ yóò dópin; kò ní mú ìgbèkùn rẹ pẹ́ mọ́. Ṣùgbọ́n, ìwọ ọmọbìnrin Edomu, yóò jẹ ẹ̀ṣẹ̀ rẹ ní yà yóò sì fi àìṣedéédéé rẹ hàn kedere.
Wee Mwarĩ wa Zayuni-rĩ, iherithia rĩaku nĩrĩgathira; ndakoongerera ihinda rĩaku rĩa gũikara ũrĩ mũtahe. No wee, Mwarĩ wa Edomu-rĩ, nĩagakũherithĩria mehia maku na aguũrie waganu waku.

< Lamentations 4 >