< Lamentations 4 >

1 Báwo ni wúrà ṣe sọ ògo dídán rẹ̀ nù, wúrà dídára di àìdán! Òkúta ibi mímọ́ wá túká sí oríta gbogbo òpópó.
Sui te bahoeng muhut, sui then khaw tho uh, lungto cim khaw tollong tom kah taphung ah a hawk uh.
2 Báwo ni àwọn ọ̀dọ́mọkùnrin Sioni tí ó ṣe iyebíye, tí wọ́n fi wúrà dídára ṣe wá dàbí ìkòkò amọ̀ lásán iṣẹ́ ọwọ́ amọ̀kòkò!
Zion ca rhoek loh suicilh neh lung vang a thuek te balae tih aka picai kut dongkah a bibi tuitang paikaek bangla a poek uh.
3 Àwọn ajáko pèsè ọmú wọn fún ìtọ́jú àwọn ọmọ wọn, ṣùgbọ́n àwọn ènìyàn mi wá láì lọ́kàn bí ògòǹgò ní aginjù.
Pongui long pataeng rhangsuk a pumcum tih a ca a khut. Ka pilnam tanu tah kalaukva khuiah khosoek kah kalaukva bangla muen.
4 Nítorí òǹgbẹ, ahọ́n àwọn ọmọ ọwọ́ lẹ̀ mọ́ òkè ẹnu wọn; àwọn ọmọdé bẹ̀bẹ̀ fún oúnjẹ, ṣùgbọ́n kò sí ẹni tí ó fi fún wọn.
Tuihalh ah cahni kah a lai te a dang la kap tih camoe rhoek loh buh a hoe dae amih aka pae om pawh.
5 Àwọn tí ó ń jẹ ohun dáradára di òtòṣì ní òpópó. Àwọn tí a fi aṣọ dáradára wọ̀ ni wọ́n sùn ní orí òkìtì eérú.
Buhmong la aka ca rhoek te tollong ah aka pong, hlampai dongah aka tangnah rhoek loh natva ni a kop uh.
6 Ìjìyà àwọn ènìyàn mi tóbi ju ti Sodomu lọ, tí a sí ní ipò ní òjijì láìsí ọwọ́ láti ràn án lọ́wọ́.
Sodom kah tholhnah lakah ka pilnam nu kah thaesainah he rhoeng. Mikhaptok ah mael tih anih te kut long khaw a sambai moenih.
7 Ọmọ ọba ọkùnrin wọn mọ́ ju òjò-dídì, wọ́n sì funfun ju wàrà lọ wọ́n ni ìtọ́jú bí iyùn pupa, ìrísí wọn dàbí safire.
A hlangcoelh rhoek te vuelsong lakah cil tih suktui lakah bok. A rhuhrhong te lungvang lakah, a pumrho te minhum lakah thimyum.
8 Ṣùgbọ́n nísinsin yìí wọ́n dúdú ju èédú; wọn kò sì dá wọn mọ̀ ní òpópó. Ara wọn hun mọ́ egungun; ó sì gbẹ bí igi gbígbẹ.
A suisak te amhmol lakah hmuep tih tollong ah hmat uh voel pawh. A vin a rhuh dongah ben uh tih thing koh bangla om.
9 Àwọn tí ó kù nípasẹ̀ idà sàn ju àwọn tí ìyàn pa; tí ó wọ àkísà ebi, tí ó ń ṣòfò fún àìní oúnjẹ láti inú pápá.
Khokha dongah rhok lakah cunghang dongkah rhok la om te then. Amih te khohmuen thaih loh a thun tih cae uh.
10 Pẹ̀lú ọwọ́ àwọn obìnrin aláàánú ni wọ́n ṣe ọmọ wọn jẹ tí ó di oúnjẹ fún wọn nígbà tí a pa àwọn ènìyàn mi run.
Lungma nu rhoek kut loh a ca a thong uh tih ka pilnam canu kah pocinah dongah amih kah a caak la poeh uh.
11 Olúwa ti fi ihò kíkún fún ìbínú rẹ̀; ó sì tú ìbínú gbígbóná rẹ̀ jáde. Ó da iná ní Sioni tí ó jó ìpìlẹ̀ rẹ̀ run.
BOEIPA loh a kosi a sah tih a thintoek thinsa te a kingling. Zion ah hmai a hlup tih a khoengim a hlawp.
12 Àwọn ọba ayé kò gbàgbọ́, tàbí àwọn ènìyàn ayé, wí pé àwọn ọ̀tá àti aninilára le wọ odi ìlú Jerusalẹmu.
Jerusalem vongka longah rhal neh thunkha a kun te diklai manghai neh lunglai dongkah khosa boeih boeih loh tangnah uh pawh.
13 Èyí ṣẹlẹ̀ nítorí ẹ̀ṣẹ̀ àwọn wòlíì àti àìṣedéédéé àwọn olórí àlùfáà, tí ó ta ẹ̀jẹ̀ àwọn olódodo sílẹ̀ láàrín rẹ̀.
A tonghma rhoek kah tholhnah neh a khosoih rhoek kah thaesainah loh a khui ah hlangdueng kah thii a hawk sak.
14 Nísinsin yìí wọ́n ń rìn kiri ní òpópó bí ọkùnrin tí ó fọ́jú. Ẹ̀jẹ̀ ara wọn sọ wọ́n di àbàwọ́n tí kò sẹ́ni tó láyà láti fọwọ́ kan aṣọ wọn.
Tollong ah mikdael la vikvuek uh tih a pueinak te ben thai pawt ham thii neh nok uh.
15 “Lọ kúrò! Ẹ̀yin di aláìmọ́!” ni àwọn ènìyàn ń kígbe sí wọn. “Ẹ lọ! Ẹ lọ! Ẹ má ṣe fọwọ́ kàn wá!” Àwọn ènìyàn láàrín orílẹ̀-èdè wí pé, “Wọn kì yóò tẹ̀dó síbí mọ́.”
Amih rhalawt rhoek te, “Nong uh, nong, nong uh lamtah ben uh boeh,” tila a o uh. Yong khonghak tih a poengdoe uh vaengah, “Namtom taengkah bakuep ham khoengvoep uh boeh,” a ti uh.
16 Olúwa ti tú wọn ká fúnra rẹ̀; kò sí bojútó wọn mọ́. Kò sí ọ̀wọ̀ fún olórí àlùfáà mọ́, àti àánú fún àwọn àgbàgbà.
BOEIPA mikhmuh ah amih a taekyak te amih paelki ham a khoep moenih. Khosoih rhoek kah maelhmai khaw dan uh pawt tih patong neh hamca rhoek khaw rhen uh pawh.
17 Síwájú sí i, ojú wa kùnà fún wíwo ìrànlọ́wọ́ asán; láti orí ìṣọ́ wa ni à ń wò fún orílẹ̀-èdè tí kò le gbà wá là.
Amih a khoengvoep bangla kaimih khaw ka khoengvoep uh. Kaimih kah bomnah ham khaw kaimih mik ni a kha. Aka daem sak pawh namtom te kaimih kah rhaltawt lamloh n'rhaltawt thil khaw a honghi ni.
18 Wọ́n ń ṣọ́ wa kiri, àwa kò sì le rìn ní òpópó wa mọ́. Òpin wa ti súnmọ́, ọjọ́ wa sì níye nítorí òpin wa ti dé.
Kaimih kah toltung ah pongpa ham kaimih kah kholaeh a thuih uh. Kaimih kah a bawtnah loh ha tawn uh tih kaimih kah khohnin a cup coeng dongah kaimih kah a bawtnah ha pawk coeng.
19 Àwọn tí ń lé wa yára ju idì ojú ọ̀run lọ; wọ́n lé wa ní gbogbo orí òkè wọ́n sì gẹ̀gùn dè wá ní aginjù.
Kaimih aka hloem rhoek te vaan kah atha lakah kapyang la om uh. Kaimih he tlang ah n'hlak tih khosoek ah khaw kaimih n'rhongngol thil uh.
20 Ẹni àmì òróró Olúwa, èémí ìyè wa, ni wọ́n fi tàkúté wọn mú. Àwa rò pé lábẹ́ òjìji rẹ̀ ni àwa yóò máa gbé láàrín orílẹ̀-èdè gbogbo.
BOEIPA loh a koelh kaimih hnarhong lamkah hil pataeng amih kah rhomhmop ah man. Te te namtom taengah khaw, “A hlipkhup ah n'hing uh bitni,” n'ti uh dae ta.
21 Ẹ yọ̀ kí inú yín sì dùn, ẹ̀yin ọmọbìnrin Edomu, ẹ̀yin tó ń gbé ní ilẹ̀ Usi. Ṣùgbọ́n, a ó gbé ago náà kọjá sọ́dọ̀ rẹ pẹ̀lú; ìwọ yóò yó bí ọ̀mùtí, ìwọ yóò sì rìn ní ìhòhò.
Uz Kho kah khosa, khosa Edom nu rhoek ngaingaih uh lamtah kohoe sak uh. Nang te khaw boengloeng loh m'paan tih na rhuihmil neh na yan uh bitni.
22 Ìwọ ọmọbìnrin Sioni, ìjìyà rẹ yóò dópin; kò ní mú ìgbèkùn rẹ pẹ́ mọ́. Ṣùgbọ́n, ìwọ ọmọbìnrin Edomu, yóò jẹ ẹ̀ṣẹ̀ rẹ ní yà yóò sì fi àìṣedéédéé rẹ hàn kedere.
Zion nu nang kah thaesainah tah bawt tih nang poelyoe ham koei voel mahpawh. Edom nu nang kah thaesainah khaw a cawh vetih na tholhnah te a phoe ni.

< Lamentations 4 >