< Judges 1 >

1 Lẹ́yìn ikú Joṣua, ni orílẹ̀-èdè Israẹli béèrè lọ́wọ́ Olúwa pé, “Èwo nínú ẹ̀yà wa ni yóò kọ́kọ́ gòkè lọ bá àwọn ará Kenaani jagun fún wa?”
Joshua a dueknah hnukah Israel ca rhoek loh BOEIPA te a dawt uh tih, “Ulae kaimih ham Kanaan taengla aka cet vetih a moecuek kah bangla anih te a vathoh thil lah ve,” a ti uh.
2 Olúwa sì dáhùn pé, “Juda ni yóò lọ; nítorí pé èmi ti fi ilẹ̀ náà lé e lọ́wọ́.”
Te dongah BOEIPA loh, “Judah te cet saeh lamtah khohmuen he a kut ah ka paek tangtae coeng ni ke,” a ti nah.
3 Nígbà náà ni àwọn olórí ẹ̀yà Juda béèrè ìrànlọ́wọ́ láti ọ̀dọ̀ àwọn ọmọ Simeoni arákùnrin wọn pé, “Ẹ wá bá wa gòkè lọ sí ilẹ̀ tí a ti fi fún wa, láti bá àwọn ará Kenaani jà kí a sì lé wọn kúrò, àwa pẹ̀lú yóò sì bá a yín lọ sí ilẹ̀ tiyín bákan náà láti ràn yín lọ́wọ́.” Àwọn ọmọ-ogun Simeoni sì bá àwọn ọmọ-ogun Juda lọ.
Te vaengah a manuca Simeon te, “Kai hmulung khuila kamah taengla ha luei lamtah Kanaan ke vathoh thil sih. Kai khaw nang hmulung kah khuikah nang taengah ka pongpa van eh,” a ti nah tih Simeon khaw anih taengla cet.
4 Nígbà tí àwọn ọmọ-ogun Juda sì kọlu wọ́n, Olúwa sì fi àwọn ará Kenaani àti àwọn ará Peresi lé wọn lọ́wọ́, wọ́n sì pa ẹgbẹ̀rún mẹ́wàá ọkùnrin ní Beseki.
Judah a luei vaengah BOEIPA loh amih kut ah Kanaan neh Perizzi te a tloeng pah tih Bezek ah hlang thawng rha a tloek uh.
5 Ní Beseki ni wọ́n ti rí Adoni-Beseki, wọ́n sì bá a jagun, wọ́n sì ṣẹ́gun àwọn ará Kenaani àti Peresi.
Bezek ah Adonibezek te a hmuh uh tih anih te a tloek uh phoeiah Kanaan neh Perizzi te a tloek uh.
6 Ọba Adoni-Beseki sá àsálà, ṣùgbọ́n ogun Israẹli lépa rẹ̀ wọ́n sì bá a, wọ́n sì gé àwọn àtàǹpàkò ọwọ́ àti ẹsẹ̀ rẹ̀.
Adonibezek te rhaelrham van dae a hnukah a hloem uh tih a kae uh vaengah a kut a kho kah kutnu khonu te a tlueh pauh.
7 Nígbà náà ni Adoni-Beseki wí pé, “Àádọ́rin ọba ni èmi ti gé àtàǹpàkò wọn tí wọ́n sì ń ṣa èérún oúnjẹ jẹ lábẹ́ tábìlì mi. Báyìí Ọlọ́run ti san án fún mi gẹ́gẹ́ bí ohun tí mo ṣe sí wọn.” Wọ́n sì mú un wá sí Jerusalẹmu, ó sì kú síbẹ̀.
Te vaengah Adonibezek loh, “Manghai sawmrhih kut kho kah kutnu khonu ka tlueh pah tih ka caboei hmuikah cakdik aka rhut la om uh. Ka saii bangla Pathen loh kai taengah han thuung coeng,” a ti. Anih te Jerusalem la a khuen uh tih te ah te duek.
8 Àwọn ológun Juda sì ṣẹ́gun Jerusalẹmu, wọ́n sì kó o, wọ́n sì fi ojú idà kọlù ú, wọ́n sì dáná sun ìlú náà.
Judah ca rhoek loh Jerusalem te a vathoh thil uh tih a buem uh. cunghang ha neh a ngawn phoeiah khopuei te hmai ah a pup uh.
9 Lẹ́yìn nǹkan wọ̀nyí ni àwọn ogun Juda sọ̀kalẹ̀ lọ láti bá àwọn ará Kenaani tí ń gbé ní àwọn ìlú orí òkè ní gúúsù àti ní pẹ̀tẹ́lẹ̀ òkè lápá ìwọ̀-oòrùn Juda jagun.
Te phoeiah tlang neh tuithim kolrhawk kah aka om Kanaan te tloek ham Judah ca rhoek loh suntla uh.
10 Ogun Juda sì tún ṣígun tọ ará Kenaani tí ń gbé Hebroni (tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Kiriati-Arba) ó sì ṣẹ́gun Ṣeṣai, Ahimani àti Talmai.
Te phoeiah Hebron ah aka om Kanaan te khaw Judah loh a paan bal. Hebron kah a ming rhuem tah Kiriatharba ni. Te vaengah Sheshai, Ahiman neh Talmai te khaw a tloek uh.
11 Láti ibẹ̀, wọ́n sì wọ́de ogun láti ibẹ̀ lọ bá àwọn ènìyàn tí ń gbé ní Debiri (tí à ń pè ní Kiriati-Seferi nígbà kan rí).
Te lamloh Debir kah khosa rhoek te a paan uh cetuh. Derbir kah a ming rhuem tah Kiriathsepher ni.
12 Kalebu sì wí pé, “Èmi yóò fi ọmọbìnrin mi Aksa fún ọkùnrin tí ó bá kọlu Kiriati-Seferi, tí ó sì gbà á ní ìgbéyàwó.”
Te vaengah Kaleb loh, “Kiriathsepher aka tloek tih aka buem te tah ka canu Akcah te a yuu la ka paek ni,” a ti.
13 Otnieli ọmọ Kenasi, àbúrò Kalebu sì gbà á, báyìí ni Kalebu sì fi ọmọbìnrin rẹ̀ Aksa fún un ní ìyàwó.
Te dongah Kaleb mana Kenaz capa Othniel loh a buem tih a canu Akcah te a yuu la a paek.
14 Ní ọjọ́ kan, nígbà tí Aksa lọ sí ọ̀dọ̀ Otnieli, ó rọ̀ ọ́ kí ó béèrè ilẹ̀ oko lọ́wọ́ baba rẹ̀. Nígbà náà ni Aksa sọ̀kalẹ̀ ní orí kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ rẹ̀, Kalebu sì béèrè pé, “Kí ni kí èmi ṣe fún ọ?”
A yuu te ha pawk vaengah a napa taengkah khohmuen bih ham a va te a vueh. laak dong lamkah a bit uh vanneh anih te Kaleb loh, “Nang ham balae kan saii eh,” a ti nah.
15 Aksa sì dáhùn pé, “Mo ń fẹ́ kí o ṣe ojúrere kan fún mi, nígbà ti o ti fún mi ní ilẹ̀ ní gúúsù, fún mi ní ìsun omi náà pẹ̀lú.” Kalebu sì fún un ní ìsun òkè àti ìsun ìsàlẹ̀.
Te dongah a canu loh, “Kai ham khaw yoethennah nan suem vanbangla tuithim khohmuen ke kai m'pae mai lamtah tuidueh tui khaw kai ham nam paek mai mako,” a ti nah. Te dongah anih te Kaleb loh a siip tuidueh neh a hnawt tuidueh te a paek.
16 Àwọn ìran Keni tí wọ́n jẹ́ àna Mose bá àwọn ọmọ Juda gòkè láti ìlú ọ̀pẹ lọ sí aginjù Juda ní gúúsù Aradi; wọ́n sì lọ, orílẹ̀-èdè méjèèjì sì jùmọ̀ ń gbé pọ̀ láti ìgbà náà.
Rhophoe khopuei lamkah Moses masae Keni ca rhoek neh Arad tuithim Judah khosoek Judah ca rhoek tah luei uh tih pilnam taengah kho a sak uh.
17 Ó sì ṣe, àwọn ológun Juda tẹ̀lé àwọn ológun Simeoni arákùnrin wọn, wọ́n sì lọ bá àwọn ará Kenaani tí ń gbé Sefati jagun, wọ́n sì run ìlú náà pátápátá, ní báyìí àwa yóò pe ìlú náà ní Horma (Horma èyí tí ń jẹ́ ìparun).
Te phoeiah Judah te a mana Simeon neh cet rhoi tih Zephath khosa rhoek Kanaan te a tloek rhoi. Khopuei te a thup tih khopuei ming khaw Hormah la a sak pah.
18 Àwọn ogun Juda sì ṣẹ́gun Gasa àti àwọn agbègbè rẹ̀, Aṣkeloni àti Ekroni pẹ̀lú àwọn ìlú tí ó yí ọ̀kọ̀ọ̀kan wọn ká.
Te vaengah Judah loh Gaza neh a khorhi, Ashkelon neh a khorhi, Ekron neh a khorhi te a loh.
19 Olúwa sì wà pẹ̀lú ẹ̀yà Juda, wọ́n gba ilẹ̀ òkè, ṣùgbọ́n wọn kò le lé àwọn ènìyàn tí ó wà ní pẹ̀tẹ́lẹ̀, nítorí wọ́n ní kẹ̀kẹ́ ogun onírin.
Te vaengah BOEIPA loh Judah a om puei tih tlang khaw a huul coeng dae kol kah khosa rhoek tah thi leng a khueh dongah haek thai pawh.
20 Gẹ́gẹ́ bí Mose ti ṣèlérí, wọ́n fún Kalebu ní Hebroni, ó sì lé àwọn tí ń gbé ibẹ̀ kúrò; àwọn náà ni ìran àwọn ọmọ Anaki mẹ́ta.
Moses kah a thui bangla Hebron te Kaleb taengah a paek uh hatah te lamkah Anak ca rhoek pathum te vik a vai.
21 Àwọn ẹ̀yà Benjamini ni wọn kò le lé àwọn Jebusi tí wọ́n ń gbé Jerusalẹmu, nítorí náà wọ́n ń gbé àárín àwọn Israẹli títí di òní.
Jerusalem kah khosa Jebusi te tah Benjamin ca rhoek loh ana haek pawt dongah tihnin due Jerusalem kah Benjamin ca rhoek taengah Jebusi loh kho a sak.
22 Àwọn ẹ̀yà Josẹfu sì bá Beteli jagun, Olúwa síwájú pẹ̀lú wọn.
Joseph imko loh Bethel a paan uh vaengah khaw amih te BOEIPA loh a om puei.
23 Nígbà tí ẹ̀yà Josẹfu rán àwọn ènìyàn láti lọ yọ́ Beteli wò (orúkọ ìlú náà tẹ́lẹ̀ rí ni Lusi).
Lamhma a ming Luz khopuei la aka om Bethel te Joseph imko loh a yaam uh.
24 Àwọn ayọ́lẹ̀wò náà rí ọkùnrin kan tí ń jáde láti inú ìlú náà wá, wọ́n sì wí fún un pé, “Fi ọ̀nà àtiwọ ìlú yìí hàn wá, àwa ó sì dá ẹ̀mí rẹ sí, a ó sì ṣe àánú fún ọ.”
Te vaengah kho khui lamkah aka lo hlang pakhat te longyam rhoek loh a hmuh uh tih, “Khopuei khuirhai te kaimih n'tueng dae, nang taengah sitlohnah ka saii uh van bitni,” a ti nah.
25 Ó sì fi ọ̀nà ìlú náà hàn wọ́n, wọ́n sì fi ojú idà kọlu ìlú náà, ṣùgbọ́n wọ́n dá ọkùnrin náà àti gbogbo ìdílé rẹ̀ si.
Te dongah amih te khopuei vongrhai a tueng tih khopuei te cunghang ha neh a tloek uh. Tedae hlang pakhat neh a imkhui pum te tah a loeih sakuh.
26 Ọkùnrin náà sí lọ sí ilẹ̀ àwọn ará Hiti, ó sì tẹ ìlú kan dó, ó sì pe orúkọ rẹ̀ ní Lusi, èyí sì ni orúkọ rẹ̀ títí di òní.
Te dongah hlang pakhat te Khitti kho la cet tih kho a thoong. Tekah kho ming te Luz la ana khue dongah tihnin due anih ming la om.
27 Ṣùgbọ́n Manase kò lé àwọn ará Beti-Ṣeani àti ìlú rẹ̀ wọ̀n-ọn-nì jáde, tàbí àwọn ará Taanaki àti àwọn ìgbèríko rẹ̀, tàbí àwọn ará Dori àti àwọn ìgbèríko rẹ̀, tàbí àwọn ará Ibleamu àti àwọn ìgbèríko rẹ̀, tàbí àwọn ará Megido àti àwọn ìgbèríko tí ó yí i ká, torí pé àwọn ará Kenaani ti pinnu láti máa gbé ìlú náà.
Bethshan neh a khobuel rhoek, Taanakh neh a khobuel rhoek, Dore kah aka om, aka om neh a khobuel rhoek, Ibleam kah aka om rhoek neh a khobuel rhoek, Megiddo kah aka om rhoek neh a khobuel rhoek tah Manasseh loh ana haek pawt dongah Kanaan rhoek loh khohmuen ah khosak ham khak huul uh.
28 Nígbà tí àwọn ọmọ Israẹli di alágbára, wọ́n mú àwọn ará Kenaani sìn bí i ẹrú, ṣùgbọ́n wọn kò fi agbára lé wọn jáde kúrò ní ilẹ̀ náà.
Israel a om vaengah a moem tih Kanaan te saldong la a khueh tih a haek rhoe a haek moenih.
29 Efraimu náà kò lé àwọn ará Kenaani tí ó ń gbé Geseri jáde, ṣùgbọ́n àwọn ará Kenaani sì ń gbé láàrín àwọn ẹ̀yà Efraimu.
Gezer ah aka om Kanaan te khaw Ephraim loh ana haek pawt dongah Gezer kah Kanaan tah amih lakli ah kho a sak.
30 Bẹ́ẹ̀ ni àwọn Sebuluni kò lé àwọn ará Kenaani tí ń gbé Kitironi jáde tàbí àwọn ará Nahalali, ṣùgbọ́n wọ́n sọ wọ́n di ẹrú. Wọ́n sì ń sin àwọn ará Sebuluni.
Kitron kah khosa rhoek neh Nahalal kah khosa rhoek te khaw Zebulun loh ana haek pawt dongah a lakli ah Kanaan loh kho a sak tih saldong la om uh.
31 Bẹ́ẹ̀ ni Aṣeri kò lé àwọn tí ń gbé ní Akko tàbí ní Sidoni tàbí ní Ahlabu tàbí ní Aksibu tàbí ní Helba tàbí ní Afiki tàbí ní Rehobu.
Akkho kah khosa rhoek, Sidon kah khosa rhoek neh Ahlab, Akhzib, Helbah, Aphek, Rehoh te khaw Asher loh ana haek pawh.
32 Ṣùgbọ́n nítorí àwọn ará Aṣeri ń gbé láàrín àwọn ará Kenaani tí wọ́n ni ilẹ̀ náà.
Amih te ana haek pawt dongah khohmuen kah aka om Kanaan lakli ah Asher long khaw kho a sak.
33 Àwọn ẹ̀yà Naftali pẹ̀lú kò lé àwọn ará Beti-Ṣemeṣi àti Beti-Anati jáde; ṣùgbọ́n àwọn ẹ̀yà Naftali náà ń gbé àárín àwọn ará Kenaani tí ó ti ní ilẹ̀ náà rí, ṣùgbọ́n àwọn tí ń gbé Beti-Ṣemeṣi àti Beti-Anati ń sìn ìsìn tipátipá.
Bethshemesh kah khosa rhoek neh Bethanath khosa rhoek te Naphtali loh ana haek pawt dongah khohmuen kah aka om Kanaan lakli ah kho a sak. Tedae Bethshemesh neh Bethanath kah aka om rhoek te tah amih ham saldong la om uh.
34 Àwọn ará Amori fi agbára dá àwọn ẹ̀yà Dani dúró sí àwọn ìlú orí òkè, wọn kò sì jẹ́ kí wọn sọ̀kalẹ̀ wá sí pẹ̀tẹ́lẹ̀.
Tlang kah Dan ca rhoek te Amori loh la a nen dongah anih te tah kol la suntlak sak ham pae pawh.
35 Àwọn ará Amori ti pinnu láti dúró lórí òkè Heresi àti òkè Aijaloni àti ti Ṣaalbimu, ṣùgbọ́n nígbà tí ẹ̀yà Josẹfu di alágbára wọ́n borí Amori wọ́n sì mú wọn sìn.
Amori khaw Heres tlang, Aijalon neh Shaalbim ah khosak ham huul uh ngawn dae Joseph imko kah a bong a ban a puel phoeiah tah amih te saldong la om uh.
36 Ààlà àwọn ará Amori sì bẹ̀rẹ̀ láti ìgòkè Akrabbimu kọjá lọ sí Sela àti síwájú sí i.
Amori khorhi he Akrabbim kham lamloh Sela voelh a poeng duela om.

< Judges 1 >