< Judges 9 >

1 Ní ọjọ́ kan Abimeleki ọmọ Jerubbaali lọ sí ọ̀dọ̀ àwọn arákùnrin ìyá rẹ̀ ní Ṣekemu ó sì bá wọn sọ̀rọ̀ àti gbogbo àwọn ìbátan ìyá rẹ̀ wí pé,
Abimeleku mũrũ wa Jerubu-Baali nĩathiire kũrĩ aa mamawe na andũ othe a mbarĩ ya kũrĩa nyina oimĩte kũu Shekemu, akĩmeera atĩrĩ,
2 “Ẹ bi gbogbo àwọn ará Ṣekemu léèrè, ‘Èwo ló sàn fún un yín, ṣé kí gbogbo àwọn àádọ́rin ọmọ Jerubbaali jẹ ọba lórí yín ni tàbí kí ẹnìkan ṣoṣo ṣe àkóso yín?’ Ṣùgbọ́n ẹ rántí pé ẹran-ara yín àti ẹ̀jẹ̀ yín ni èmi ń ṣe.”
“Ũriai atũũri othe a Shekemu atĩrĩ, ‘Nĩ ũndũ ũrĩkũ mwega na inyuĩ. Nĩ mwathwo nĩ ariũ mĩrongo mũgwanja a Jerubu-Baali, kana mũthamakĩrwo nĩ mũndũ ũmwe?’ Ririkanai ndĩ wanyu, tuumĩte mũthiimo ũmwe.”
3 Nígbà tí àwọn arákùnrin rẹ̀ sọ èyí ní etí àwọn ará Ṣekemu, ọkàn wọn fà sí àti tẹ̀lé Abimeleki torí, wọ́n sọ wí pé, “Arákùnrin wa ní í ṣe.”
Rĩrĩa aa mamawe meerire atũũri a Shekemu ũhoro ũcio wothe, andũ a Shekemu makĩenda kũrũmĩrĩra Abimeleku nĩ ũndũ nĩmoigire atĩrĩ, “Ũcio nĩ mũrũ wa ithe witũ.”
4 Wọ́n fún un ní àádọ́rin ṣékélì fàdákà láti ilé òrìṣà Baali-Beriti, Abimeleki fi owó náà gba àwọn jàǹdùkú àti aláìníláárí ènìyàn tí wọ́n sì di olùtẹ̀lé rẹ̀.
Nao makĩmũhe cekeri mĩrongo mũgwanja cia betha irutĩtwo hekarũ-inĩ ya Baali-Berithu, nake Abimeleku agĩcihũthĩra kwandĩka andũ matarĩ kĩene na a mbũkĩrĩra, arĩa maatuĩkire arũmĩrĩri ake.
5 Ó kó wọn lọ sí ilé baba rẹ̀ ní Ofira, níbẹ̀ ní orí òkúta kan ṣoṣo ni ó ti pa àádọ́rin nínú àwọn arákùnrin rẹ̀, àwọn Jerubbaali, ṣùgbọ́n Jotamu, àbíkẹ́yìn nínú àwọn ọmọ Jerubbaali, bọ́ yọ nítorí pé ó sá pamọ́.
Agĩthiĩ gwa ithe mũciĩ o kũu Ofira na akĩũragithĩria ariũ a ithe mĩrongo mũgwanja ihiga-inĩ rĩmwe, nĩo ariũ a Jerubu-Baali. No Jothamu, mũrũ wa Jerubu-Baali ũrĩa warĩ kĩhinga-nda, nĩahonokire nĩ ũndũ nĩehithire.
6 Gbogbo àwọn ará Ṣekemu àti àwọn ará Beti-Milo pàdé pọ̀ ní ẹ̀bá igi óákù ní ibi òpó ní Ṣekemu láti fi Abimeleki jẹ ọba.
Nao atũũri othe a Shekemu na a Bethi-Milo makĩũngana mũtĩ-inĩ ũrĩa mũnene o hau gĩtugĩ-inĩ kĩrĩa kĩrĩ Shekemu, magĩtua Abimeleku mũthamaki.
7 Nígbà tí wọ́n sọ ohun tí ó ń ṣẹlẹ̀ yìí fún Jotamu, ó gun orí ṣóńṣó òkè Gerisimu lọ, ó sì ké lóhùn rara pé, “Ẹ tẹ́tí sí mi, ẹ̀yin àgbàgbà Ṣekemu, kí Ọlọ́run le tẹ́tí sí yín.
Hĩndĩ ĩrĩa Jothamu aaheirwo ũhoro ũcio-rĩ, akĩhaica Kĩrĩma-igũrũ kĩa Gerizimu na akĩanĩrĩra, akĩmeera atĩrĩ, “Ta thikĩrĩriai inyuĩ atũũri a Shekemu, nĩgeetha o nake Ngai amũthikĩrĩrie.
8 Ní ọjọ́ kan àwọn igi jáde lọ láti fi òróró yan ọba fún ara wọn. Wọ́n pe igi Olifi pé, ‘Wá ṣe ọba wa.’
Mũthenya ũmwe mĩtĩ nĩyoimagarire ĩgaitĩrĩrie ũmwe wayo maguta atuĩke mũthamaki wayo. Nayo ĩkĩĩra mũtamaiyũ atĩrĩ, ‘Ũka ũtuĩke mũthamaki witũ.’
9 “Ṣùgbọ́n igi Olifi dá wọn lóhùn pé, ‘Èmi yóò ha fi òróró mi sílẹ̀ èyí tí a ń lò láti fi ọ̀wọ̀ fún àwọn ọlọ́run àti ènìyàn kí èmi sì wá ṣe olórí àwọn igi?’
“No mũtamaiyũ ũcio ũgĩcookia atĩrĩ, ‘No ndigane na maguta makwa marĩa matũmaga ngai o na andũ matĩĩo, ngariũnge ũũ na ũũ igũrũ rĩa mĩtĩ ĩrĩa ĩngĩ?’
10 “Àwọn igi sọ fún igi ọ̀pọ̀tọ́ pé, ‘Wá jẹ ọba ní orí wa.’
“Thuutha ũcio mĩtĩ ĩyo ĩkĩĩra mũkũyũ atĩrĩ, ‘Ũka ũtuĩke mũthamaki witũ.’
11 “Ṣùgbọ́n ọ̀pọ̀tọ́ dá wọn lóhùn pé, ‘Kí èmi fi èso mi tí ó dára tí ó sì dùn sílẹ̀ láti wá ṣe olórí àwọn igi?’
“No mũkũyũ ũcio ũgĩcookia atĩrĩ, ‘No ndigane na ngũyũ ciakwa njega ũguo na irĩ mũrĩo, ngariũnge ũũ na ũũ igũrũ rĩa mĩtĩ ĩrĩa ĩngĩ?’
12 “Àwọn igi sì tún sọ fún àjàrà pé, ‘Wá, kí o ṣe ọba wa.’
“Ningĩ mĩtĩ ĩkĩĩra mũthabibũ atĩrĩ, ‘Ũka ũtuĩke mũthamaki witũ.’
13 “Ṣùgbọ́n àjàrà dáhùn pé, ‘Ṣé kí èmi dẹ́kun àti máa so èso wáìnì mi èyí tí ó ń mú inú Ọlọ́run àti àwọn ènìyàn dùn láti máa ṣe olórí àwọn igi?’
“No mũthabibũ ũcio ũgĩcookia atĩrĩ, ‘No ndigane na ndibei yakwa ĩrĩa ĩkenagia ngai o na andũ, ngariũnge ũũ na ũũ igũrũ rĩa mĩtĩ ĩrĩa ĩngĩ?’
14 “Ní ìparí gbogbo àwọn igi lọ bá igi ẹ̀gún wọ́n sì sọ fún un pé, ‘Wá kí ó ṣe ọba wa.’
“Kũrĩkĩrĩria mĩtĩ yothe ĩkĩĩra mũtare wa gĩthaka-inĩ atĩrĩ, ‘Ũka ũtuĩke mũthamaki witũ.’
15 “Igi ẹ̀gún dá àwọn igi lóhùn pé, ‘Bí olóòtítọ́ ni ẹ bá fẹ́ yàn mí ní ọba yín. Ẹ sá àsálà sí abẹ́ ibòòji mi; ṣùgbọ́n tí kì í bá ṣe bẹ́ẹ̀ jẹ́ kí iná jáde láti inú igi ẹ̀gún kí ó sì jó àwọn igi kedari àti ti Lebanoni run!’
“Naguo mũtare ũcio wa gĩthaka ũkĩĩra mĩtĩ ĩyo atĩrĩ, ‘Kũngĩkorwo ti-itherũ nĩ mũkwenda kũnjitĩrĩria maguta nduĩke mũthamaki wanyu-rĩ, gĩũkei mwĩhithe kĩĩruru-inĩ gĩakwa; no kũngĩkorwo ti ũguo-rĩ, mwaki ũrokiuma mũtare-inĩ wa gĩthaka ũcine mĩtarakwa ya Lebanoni!’
16 “Báyìí tí ó bá jẹ́ pé ẹ̀yin ṣe ohun tí ó ní ọlá àti pẹ̀lú ẹ̀mí òtítọ́ ní fífi Abimeleki jẹ ọba, tí ó bá ṣe pé ohun tí ó tọ́ ni ẹ ṣe sí Jerubbaali àti ìdílé rẹ̀, bí ẹ bá san ẹ̀san tó yẹ fún un.
“No rĩrĩ, angĩkorwo mwekire ũndũ ũcio na kĩhooto, na mũrĩ na ngoro njega rĩrĩa mwatuire Abimeleku mũthamaki, na angĩkorwo nĩmwĩkĩte Jerubu-Baali na nyũmba yake maũndũ mega, mũkamwĩka ũrĩa agĩrĩirwo nĩ gwĩkwo-rĩ,
17 Nítorí pé baba mi jà nítorí yín, ó fi ẹ̀mí rẹ̀ wéwu láti gbà yín sílẹ̀ lọ́wọ́ àwọn ará Midiani;
tondũ baba nĩwe wamũrũĩrĩire, agĩtwarĩrĩria muoyo wake ũgwati-inĩ nĩgeetha amũhonokie moko-inĩ ma Amidiani,
18 ṣùgbọ́n lónìí ẹ̀yin ṣọ̀tẹ̀ sí ilé baba mi, ní orí òkúta kan ṣoṣo ni ẹ ti pa àwọn àádọ́rin ọmọ rẹ̀, ẹ̀yin sì ti fi Abimeleki ọmọ ẹrúbìnrin rẹ̀ jẹ ọba lórí àwọn ènìyàn Ṣekemu nítorí tí ó jẹ́ arákùnrin yín.
(no ũmũthĩ nĩmũũkĩrĩire nyũmba ya baba, mũkooragĩra ariũ ake mĩrongo mũgwanja ihiga-inĩ rĩmwe, na mũgatua Abimeleku, mũrũ wa ngombo yake ya mũirĩtu, mũthamaki wa atũũri a Shekemu tondũ nĩ mũrũ wa ithe wanyu),
19 Bí ohun tí ẹ ṣe sí Jerubbaali àti ìdílé rẹ̀ bá jẹ́ ohun tí ó yẹ, tí ẹ sì ṣe òtítọ́ inú sí i, kí ẹ ní ayọ̀ nínú Abimeleki kí òun náà sì ní ayọ̀ nínú yín.
mũngĩkorwo mwĩkĩte ũndũ ũcio na kĩhooto, na mũrĩ na ngoro njega kũrĩ Jerubu-Baali na nyũmba yake ũmũthĩ-rĩ, Abimeleku arotuĩka gĩkeno kĩanyu, o na inyuĩ mũgĩtuĩke gĩkeno gĩake!
20 Ṣùgbọ́n tí kò bá ṣe bẹ́ẹ̀ jẹ́ kí iná jó jáde wá láti ọ̀dọ̀ Abimeleki kí ó sì jó yín run. Ẹ̀yin ará Ṣekemu àti ará Beti-Milo, kí iná pẹ̀lú jáde láti ọ̀dọ̀ yín wá ẹ̀yin ará Ṣekemu àti ará Beti-Milo kí ó sì jó Abimeleki run.”
No kũngĩkorwo ti ũguo-rĩ, mwaki ũrokiuma harĩ Abimeleku ũmũcine, ũmũniine biũ, atũũri aya a Shekemu na Bethi-Milo, o na mwaki ũrokiuma harĩ inyuĩ atũũri a Shekemu na Bethi-Milo, ũcine Abimeleku, ũmũniine biũ.”
21 Lẹ́yìn tí Jotamu ti sọ èyí tan, ó sá àsálà lọ sí Beeri, ó sì gbé níbẹ̀ nítorí ó bẹ̀rù arákùnrin rẹ̀ Abimeleki.
Hĩndĩ ĩyo Jothamu agĩĩthara, akĩũrĩra kũu Biri, nake agĩtũũra kuo nĩ ũndũ nĩetigagĩra mũrũ wa ithe, Abimeleku.
22 Lẹ́yìn tí Abimeleki ti ṣe àkóso Israẹli fún ọdún mẹ́ta,
Thuutha wa Abimeleku gwathana Isiraeli mĩaka ĩtatũ-rĩ,
23 Ọlọ́run rán ẹ̀mí búburú sáàárín Abimeleki àti àwọn ará Ṣekemu, àwọn ẹni tí ó hu ìwà ọ̀tẹ̀.
Ngai agĩtũma roho mũũru gatagatĩ ka Abimeleku na atũũri a Shekemu, arĩa meekire maũndũ mooru ma ũhinga kũrĩ Abimeleku.
24 Ọlọ́run ṣe èyí láti gbẹ̀san àwọn ìwà búburú, àti ìtàjẹ̀ sílẹ̀ àwọn àádọ́rin ọmọ Jerubbaali lára Abimeleki arákùnrin wọn àti lára àwọn ènìyàn Ṣekemu, ẹni tí ó ràn án lọ́wọ́ láti pa àwọn arákùnrin rẹ̀.
Ngai eekire ũndũ ũyũ nĩgeetha ngero ĩrĩa yagerirwo ariũ mĩrongo mũgwanja a Jerubu-Baali, ya gũitwo thakame yao, ĩrĩhio mũrũ wa ithe wao, Abimeleku, na ĩrĩhio atũũri a Shekemu arĩa maamũteithirie kũũraga ariũ a ithe.
25 Nítorí ìkórìíra tí wọ́n ni sí àwọn olórí, ni Ṣekemu dẹ àwọn ènìyàn sí àwọn orí òkè láti máa dá àwọn ènìyàn tó ń kọjá lọ́nà, kí wọn sì máa jà wọ́n lólè, àwọn kan ló sọ èyí fún Abimeleki.
Nĩ ũndũ wa kũregana nake-rĩ, atũũri acio a Shekemu nĩmaigire andũ irĩma-inĩ nĩguo mohie na matunye o mũndũ ũrĩa wahĩtũkaga indo ciake, naguo ũhoro ũcio ũkĩmenyithio Abimeleku.
26 Gaali ọmọ Ebedi àti àwọn arákùnrin rẹ̀ wá sí Ṣekemu, àwọn ará Ṣekemu sì gbẹ́kẹ̀lé wọn, wọ́n sì fi inú tán wọn.
Nake Gaali mũrũ wa Ebedi hamwe na ariũ a ithe magĩthaamĩra kũu Shekemu, nao atũũri akuo makĩmwĩhoka.
27 Lẹ́yìn ìgbà tí wọ́n jáde lọ sí oko, wọ́n sì ṣa èso àjàrà wọn jọ, wọ́n fún èso àjàrà náà, wọ́n sì ṣe àjọ̀dún nínú ilé òrìṣà wọn. Nígbà tí wọ́n ń jẹ tí wọ́n ń mu wọ́n fi Abimeleki ré.
Thuutha wa gũthiĩ mĩgũnda-inĩ na gũcookereria thabibũ na gũcihiha, makĩgĩa na iruga hekarũ-inĩ ya ngai yao. Rĩrĩa maarĩĩaga na makĩnyuuaga, makĩruma Abimeleku.
28 Gaali ọmọ Ebedi dáhùn pé, “Ta ni Abimeleki tàbí ta ni Ṣekemu tí àwa ó fi sìn ín? Ọmọ Jerubbaali kọ́ ní ṣe tàbí Sebulu kọ́ ní igbákejì rẹ̀? Ẹ má sin àwọn ará Hamori baba àwọn ará Ṣekemu, èéṣe tí a ó fi sin Abimeleki?
Nake Gaali mũrũ wa Ebedi akiuga atĩrĩ, “Abimeleku nũũ, na Shekemu nũũ, nĩguo tũtuĩke ndungata ciake? Githĩ ti mũrũ wa Jerubu-Baali, nake Zebuli githĩ tiwe mũnini wake? Tungatĩrai andũ a Hamoru, ithe wa Shekemu! Tũgũgĩtungatĩra Abimeleku nĩkĩ?
29 Ìbá se pé àwọn ènìyàn yìí wà ní abẹ́ ìṣàkóso mi ni! Èmi ìbá bọ́ àjàgà rẹ̀ kúrò ní ọrùn yín. Èmi yóò wí fún Abimeleki pé, ‘Kó gbogbo àwọn ogun rẹ jáde láti jà.’”
Naarĩ korwo andũ aya me rungu rwa wathani wakwa! Hĩndĩ ĩyo niĩ no ndĩmweherie. No njĩĩre Abimeleku atĩrĩ, ‘Ĩta ita rĩaku rĩothe!’”
30 Nígbà tí Sebulu, alákòóso ìlú náà gbọ́ ohun tí Gaali ọmọ Ebedi sọ, inú bí i gidigidi.
Rĩrĩa Zebuli ũcio mwathi wa itũũra aiguire ũrĩa Gaali mũrũ wa Ebedi oigĩte-rĩ, akĩrakario nĩ ũhoro ũcio mũno.
31 Ó ránṣẹ́ sí Abimeleki pé, “Gaali ọmọ Ebedi àti àwọn arákùnrin rẹ̀ wá láti máa gbé ní Ṣekemu ṣùgbọ́n, wọ́n ń rú àwọn ènìyàn sókè láti ṣọ̀tẹ̀ sí ọ.
Agĩtũmĩra Abimeleku andũ na hitho, akĩmwĩra atĩrĩ, “Gaali mũrũ wa Ebedi na ariũ a ithe nĩmokĩte gũkũ Shekemu, na nĩmararahũra andũ a itũũra magũũkĩrĩre.
32 Wá ní òru kí ìwọ àti àwọn ogun rẹ sá pamọ́ dè wọ́n nínú igbó.
Nĩ ũndũ wa ũguo-rĩ, ũtukũ wakinya wee na andũ aku mũũke mũmoohie mĩgũnda-inĩ.
33 Ní òwúrọ̀ kùtùkùtù bí oòrùn ti ń yọ ìwọ yóò wọ inú ìlú náà lọ láti bá a jà. Yóò sì ṣe nígbà tí Gaali àti àwọn ogun rẹ̀ tí ó wà pẹ̀lú rẹ̀ bá jáde sí ọ láti bá ọ jà, ìwọ yóò ṣe ohunkóhun tí o bá fẹ́ sí wọn.”
Rũciinĩ tene riũa rĩkĩratha-rĩ, ũthiĩ ũtharĩkĩre itũũra inene. Na rĩrĩa Gaali na andũ ake mariumĩra magũtharĩkĩre-rĩ, ĩka ũrĩa wothe guoko gwaku kũngĩhota gwĩka.”
34 Abimeleki àti gbogbo àwọn ogun rẹ̀ sì jáde ní òru, wọ́n sì sá pamọ́ sí ọ̀nà mẹ́rin yí Ṣekemu ká.
Nĩ ũndũ ũcio Abimeleku marĩ hamwe na mbũtũ ciake ciothe cia ita makiumagara ũtukũ, makĩĩhitha gũkuhĩ na Shekemu marĩ ikundi inya.
35 Gaali ọmọ Ebedi jáde síta, ó sì dúró ní ẹnu-ọ̀nà ibodè ìlú náà ní àkókò tí Abimeleki àti àwọn ọmọ-ogun rẹ̀ jáde kúrò níbi tí wọn sá pamọ́ sí.
Nake Gaali mũrũ wa Ebedi nĩoimagarĩte akarũgama itoonyero-inĩ rĩa kĩhingo gĩa itũũra inene, o hĩndĩ ĩyo Abimeleku na thigari ciake moimagĩra kũrĩa meehithĩte.
36 Nígbà tí Gaali rí àwọn ènìyàn náà, ó sọ fún Sebulu pé, “Wò ó, àwọn ènìyàn ń ti orí òkè sọ̀kalẹ̀ wá!” Sebulu sì wí fún un pé, “Òjìji òkè wọ̀n-ọn-nì ni ìwọ rí bi ẹni pé ènìyàn.”
Rĩrĩa Gaali aamoonire-rĩ, akĩĩra Zebuli atĩrĩ, “Ta rora, harĩ na andũ maroka maikũrũkĩte kuuma irĩma igũrũ!” Nake Zebuli agĩcookia atĩrĩ, “Wee ũroona ciĩruru cia irĩma taarĩ andũ.”
37 Gaali ké ó ní, “Wòkè, àwọn ènìyàn ń tọ̀ wá bọ̀ láti agbede-méjì ilẹ̀ wá àti ẹ̀gbẹ́ kan sì ń ti ọ̀nà igi óákù Meonenimu wá.”
No Gaali akĩaria rĩngĩ, akiuga atĩrĩ: “Ta rora wone andũ maroka maikũrũkĩte moimĩte gatagatĩ ka bũrũri, na mbũtũ ĩrĩa ĩngĩ yũkĩte yumĩte na mwena wa mũtĩ wa mũragũri.”
38 Nígbà náà ni Sebulu dá a lóhùn pé, “Níbo ni ẹnu tí ó ń ṣe ni wà báyìí. Ṣe bí o wí pé, ‘Ta ni Abimeleki tí àwa ó fi máa sìn ín?’ Àwọn ẹni tí ó gàn án kọ́ nìyí? Jáde lọ kí o sì bá wọn jà!”
Ningĩ Zebuli akĩmwĩra atĩrĩ, “Mwĩgaatho waku ũkĩrĩ ha rĩu, wee woigire atĩrĩ, ‘Abimeleku nũũ atĩ nĩguo atwathe?’ Githĩ andũ aya ti o wanyũrũririe. Umagara ũkarũe nao!”
39 Gaali sì síwájú àwọn ogun ará Ṣekemu lọ kọjú Abimeleki láti bá wọn jagun.
Nĩ ũndũ ũcio Gaali agĩtongoria atũũri a Shekemu makĩhũũrana na Abimeleku.
40 Abimeleki sì lé e, ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn ọmọ-ogun ṣubú wọ́n sì gbọgbẹ́ bí wọ́n ṣe ń sálọ, títí dé ẹnu-ọ̀nà ibùdó ìlú náà.
Abimeleku akĩmũtengʼeria, nao andũ aingĩ makĩgũa magurarĩtio makĩũra kũu guothe o nginya itoonyero-inĩ rĩa kĩhingo.
41 Abimeleki dúró sí Aruma, nígbà tí Sebulu lé Gaali àti àwọn arákùnrin rẹ̀ kúrò ni Ṣekemu, kò sì jẹ́ kí wọ́n gbé Ṣekemu mọ́.
Abimeleku agĩtũũra Aruma, nake Zebuli akĩrutũrũra Gaali hamwe na ariũ a ithe kuuma Shekemu.
42 Ní ọjọ́ kejì àwọn ará Ṣekemu sì jà lọ́ sí oko, ẹnìkan ló ṣe òfófó rẹ̀ fún Abimeleki.
Mũthenya ũyũ ũngĩ andũ a Shekemu magĩthiĩ mĩgũnda-inĩ, nake Abimeleku akĩmenyithio ũhoro ũcio.
43 Ó kó àwọn ènìyàn rẹ̀, ó pín wọn sí ẹgbẹ́ mẹ́ta ó sì sá pamọ́ sí inú oko. Nígbà tí ó sì rí tí àwọn ènìyàn náà ń jáde kúrò nínú ìlú, ó dìde ó gbóguntì wọ́n.
Nĩ ũndũ ũcio akĩoya andũ ake, akĩmagayania ikundi ithatũ, akĩmaiga moherie andũ mĩgũnda-inĩ. Hĩndĩ ĩrĩa onire andũ acio magĩũka moimĩte itũũra-inĩ rĩrĩa inene, agĩũkĩra amatharĩkĩre.
44 Abimeleki àti àwọn ọmọ-ogun tí ó wà pẹ̀lú rẹ̀ sáré síwájú, wọ́n gba ẹnu ibodè ìlú náà, wọ́n sì dúró níbẹ̀. Àwọn ẹgbẹ́ méjì tókù sì sáré sí àwọn tó wà ní oko wọ́n sì gbóguntì wọ́n.
Abimeleku na ikundi iria aarĩ nacio makĩguthũka mbere nginya hau itoonyero-inĩ rĩa kĩhingo gĩa itũũra inene, nacio ikundi icio ingĩ igĩrĩ ikĩguthũkĩra arĩa maarĩ mĩgũnda-inĩ, ikĩmooraga.
45 Ní gbogbo ọjọ́ náà ni Abimeleki fi bá àwọn ará ìlú náà jà, ó sì ṣẹ́gun wọn, ó sì pa àwọn ènìyàn ìlú náà ó wó ìlú náà palẹ̀ pátápátá ó sì fọ́n iyọ̀ sí i.
Abimeleku akĩhũũrana na itũũra rĩu inene mũthenya wothe nginya akĩrĩtaha na akĩũraga andũ a rĩo othe. Ningĩ akĩananga itũũra rĩu inene, na akĩrĩitĩrĩria cumbĩ.
46 Àwọn ènìyàn ilé ìṣọ́ Ṣekemu gbọ́ ohun tí ó ṣẹlẹ̀, wọ́n sálọ fún ààbò sí inú ilé ìṣọ́ òrìṣà El-Beriti.
Rĩrĩa maiguire ũhoro ũcio, andũ arĩa maatũũraga mũthiringo-inĩ wa Shekemu magĩtoonya kĩĩhitho-inĩ kĩa hinya kĩa hekarũ ya Eli-Berithu.
47 Nígbà tí wọ́n sọ fún Abimeleki pé gbogbo àwọn ènìyàn ilé ìṣọ́ Ṣekemu kó ara wọn jọ pọ̀.
Rĩrĩa Abimeleku aiguire atĩ nĩmacookanĩrĩire kuo-rĩ,
48 Abimeleki àti gbogbo àwọn ọmọ-ogun rẹ̀ gun òkè Salmoni lọ. Ó gé àwọn ẹ̀ka díẹ̀ pẹ̀lú àáké, ó gbé àwọn ẹ̀ka wọ̀nyí sí èjìká rẹ̀. Ó sọ fún àwọn ọmọ-ogun rẹ̀ pé, “Ẹ ṣe ohun tí ẹ rí tí mo ń ṣe yìí ní kíákíá.”
we na andũ ake othe makĩambata Kĩrĩma-inĩ gĩa Zalimuna. Akĩoya ithanwa, agĩtema honge, na agĩciigĩrĩra ciande. Agĩatha andũ arĩa maarĩ nake, akĩmeera atĩrĩ, “Narua! Ĩkai ũguo muona ndeka!”
49 Báyìí gbogbo àwọn ọkùnrin tí ó wà lọ́dọ̀ rẹ̀ gé àwọn ẹ̀ka igi wọn tẹ̀lé Abimeleki. Wọ́n kó wọn ti ilé ìṣọ́ agbára níbi tí àwọn ènìyàn sá pamọ́ sí wọ́n sì fi iná sí i, tóbẹ́ẹ̀ tí gbogbo àwọn ọkùnrin ilé ìṣọ́ Ṣekemu fi kú pẹ̀lú. Gbogbo àwọn ènìyàn náà tí ó tó ẹgbẹ̀rún ènìyàn lọ́kùnrin àti lóbìnrin sì kú.
Nĩ ũndũ ũcio andũ acio othe magĩtema honge, na makĩrũmĩrĩra Abimeleku. Magĩciũmba hĩba kũnyiitana na kĩĩhitho kĩu kĩa hinya magĩcigwatia mwaki andũ marĩ thĩinĩ. Nĩ ũndũ ũcio andũ acio othe maarĩ thĩinĩ wa mũthiringo ũcio wa Shekemu, ta andũ 1,000, arũme na andũ-a-nja, o nao magĩkua.
50 Abimeleki tún lọ sí Tebesi, ó yí ìlú náà ká pẹ̀lú àwọn ọmọ-ogun, ó sì ṣẹ́gun rẹ̀.
Abimeleku agĩthiĩ itũũra rĩa Thebezu, akĩrĩrigiicĩria na akĩrĩtunyana.
51 Ilé ìṣọ́ kan tí ó ní agbára sì wà nínú ìlú náà. Gbogbo àwọn ènìyàn ìlú náà ọkùnrin àti obìnrin sá sínú ilé ìṣọ́ náà. Wọ́n ti ara wọn mọ́ ibẹ̀ wọ́n sì sálọ sí inú àjà ilé ìṣọ́ náà.
No rĩrĩ, thĩinĩ wa itũũra rĩu inene nĩ kwarĩ na mũthiringo mũrũmu kũrĩa arũme othe na andũ-a-nja, na andũ othe a itũũra rĩu inene, moorĩire. Makĩĩhingĩra thĩinĩ, na makĩhaica mũthiringo igũrũ.
52 Abimeleki lọ sí ìsàlẹ̀ ilé ìṣọ́ náà, ó sì ń bá a jà. Ṣùgbọ́n bí ó ti súnmọ́ ẹnu-ọ̀nà ilé ìṣọ́ náà láti dáná sun ún,
Abimeleku agĩthiĩ mũthiringo-inĩ ũcio, akĩũhithũkĩra. No rĩrĩa akuhĩrĩirie itoonyero rĩa mũthiringo nĩguo aũgwatie mwaki-rĩ,
53 obìnrin kan sọ ọmọ ọlọ lu Abimeleki lórí, ó sì fọ́ ọ ní agbárí.
mũtumia ũmwe akĩmũgũithĩria ihiga rĩa gĩthĩi mũtwe, rĩkĩmũhehenja mũtwe.
54 Ní ojú kan náà ni ó pe ẹni tí ó ru àpáta rẹ̀ pé, “Yára yọ idà rẹ kí o sì pa mí, kí wọn má ba à sọ pé, ‘Obìnrin ni ó pa á.’” Ọ̀dọ́mọkùnrin náà sì fi ọ̀kọ̀ gún un, ó sì kú.
Nake agĩĩta mũkuui wake wa indo cia mbaara na ihenya, akĩmwĩra atĩrĩ, “Comora rũhiũ rwaku rwa njora ũnjũrage, nĩgeetha matikoigage atĩrĩ, ‘Ooragirwo nĩ mũndũ-wa-nja.’” Nĩ ũndũ ũcio ndungata yake ĩkĩmũtheeca, agĩkua.
55 Nígbà tí àwọn ará Israẹli rí i pé Abimeleki kú, olúkúlùkù wọn padà sí ilé rẹ̀.
Hĩndĩ ĩrĩa andũ a Isiraeli moonire atĩ Abimeleku nĩakuĩte-rĩ, makĩĩinũkĩra.
56 Báyìí ni Ọlọ́run san ẹ̀san ìwà búburú ti Abimeleki hù sí baba rẹ̀ ní ti pípa tí ó pa, àwọn àádọ́rin arákùnrin rẹ̀.
Ũguo nĩguo Ngai aarĩhirie Abimeleku nĩ ũndũ wa waganu ũrĩa ekĩte ithe, wa kũũraga ariũ-a-ithe mĩrongo mũgwanja.
57 Ọlọ́run jẹ́ kí ìwà búburú àwọn ará Ṣekemu pẹ̀lú padà sí orí wọn. Ègún Jotamu ọmọ Jerubbaali pàápàá wá sí orí wọn.
Ningĩ Ngai akĩrĩhia andũ a Shekemu nĩ ũndũ wa waganu wao wothe. Kĩrumi kĩa Jothamu mũrũ wa Jerubu-Baali gĩkĩmacookerera.

< Judges 9 >