< Judges 7 >

1 Ní òwúrọ̀ kùtùkùtù Jerubbaali (èyí ni Gideoni) pẹ̀lú gbogbo àwọn ọmọ-ogun tí ó wà pẹ̀lú rẹ̀ kó ogun jọ lẹ́bàá a orísun Harodi. Àwọn ogun Midiani sì wà ní apá àríwá tí wọ́n ní àfonífojì tí ó wà ní ẹ̀bá òkè More.
Jerub-Baal (Gideon) loe khawnbang khawnthaw ah angthawk moe, angmah ih kaminawk boih hoi nawnto Harod tui longhaih ahmuen ah atai o; Midian kaminawk loe nihcae ataihaih aluek bang, Moreh mae taeng ih tangtling ah atai o.
2 Olúwa wí fún Gideoni pé, “Àwọn ọmọ-ogun tí o kójọ sọ́dọ̀ ti pọ̀jù fún mi láti fi àwọn ogun Midiani lé wọn lọ́wọ́, kí Israẹli má ba à gbé ara rẹ̀ ga sí mi wí pé agbára òun ni ó gbà á là,
Angraeng mah Gideon khaeah, Midian kaminawk nangcae ban ah kang paek hanah, kami paroeai na pop o vop; to tiah nangcae khae kang paek nahaeloe, kaimacae ban thacakhaih hoiah ni kaimacae hoi kaimacae kam hlong o tiah, Israel kaminawk mah ka nuiah amoek o moeng tih.
3 sì kéde sí àwọn ènìyàn nísinsin yìí pé, ‘Ẹnikẹ́ni tí ó bá ń gbọ̀n, tí ó sì ń bẹ̀rù lè padà sẹ́yìn, kí ó sì kúrò lórí òkè Gileadi.’” Báyìí ni Gideoni ṣe ya àwọn ènìyàn náà. Ẹgbẹ̀rún méjìlélógún ọkùnrin sì padà sẹ́yìn àwọn ẹgbẹ̀rún mẹ́wàá sì dúró.
To pongah vaihi kaminawk khaeah, Mi kawbaktih doeh zithaih tawn kami loe Gilead mae hoi amlaem o roep nasoe, tiahg thui paeh, tiah a naa. To pongah kami sang pumphae hnetto amlaem o moe, kami sang hato tang.
4 Olúwa sì tún sọ fún Gideoni pé, “Àwọn ènìyàn yìí sì tún pọ̀jù. Kó wọn lọ sí ibi tí omi wà, èmi yóò sì yọ̀rọ̀ wọn níbẹ̀ fún ọ. Bí mo bá wí pé eléyìí yóò bá ọ lọ yóò lọ, ṣùgbọ́n tí mo bá sọ pé, ‘Eléyìí kò ní bá ọ lọ,’ òun kò gbọdọ̀ lọ.”
Toe Angraeng mah Gideon khaeah, Kami na pop o parai vop pongah, tui ohhaih ahmuen ah caeh haih ah, to ah nihcae to kang tanoek pae han; nang hoi nawnto caeh tih, tiah kang thuih ih kami to ni, nang hoi nawnto caeh tih; toe nang hoi nawnto caeh mak ai, tiah kang thuih ih kami loe, nang hoi nawnto caeh mak ai, tiah a naa.
5 Gideoni sì kó àwọn ọkùnrin náà lọ sí ibi ìsun omi. Níbẹ̀ ni Olúwa ti wí fún un pé, “Kí ó pín àwọn ènìyàn náà sí ọ̀nà méjì. Ya àwọn tí ó fi ahọ́n wọn lá omi bí ajá kúrò lára àwọn tí ó kúnlẹ̀ láti mu omi pẹ̀lú ọwọ́ wọn.”
To pongah Gideon mah kaminawk to tui ohhaih ahmuen ah caeh haih; Angraeng mah anih khaeah, ui baktiah palai hoi tui nae kaminawk hoi khokkhu cangkrawn moe, tui nae kaminawk to tapraek ah, tiah a naa.
6 Ọ̀ọ́dúnrún ọkùnrin ni ó lá omi pẹ̀lú ahọ́n wọn. Gbogbo àwọn ìyókù ni ó kúnlẹ̀ láti mu mi.
Kami cumvai thumtonawk loe tui to ban hoiah soh o moe, naek o. Kalah kaminawk boih loe tuinaek hanah cangkrawn o.
7 Olúwa wí fún Gideoni pé, “Àwọn ọ̀ọ́dúnrún ọkùnrin tí ó lá omi ni èmi yóò lò láti gbà yín là àti láti fi ogun Midiani lé yín lọ́wọ́. Jẹ́ kí àwọn tókù padà sí ilé wọn.”
Angraeng mah Gideon khaeah, Ban hoi tui nae kami cumvai thumto hoiah nang to kang pahlong moe, Midian kaminawk to na ban ah kang paek han; kalah kaminawk loe angmacae ohhaih ahmuen ah caehsak boih ah, tiah a naa.
8 Báyìí ni Gideoni ṣe dá àwọn Israẹli tí ó kù padà sí àgọ́ wọn, ṣùgbọ́n ó dá àwọn ọ̀ọ́dúnrún ọkùnrin náà dúró. Àwọn wọ̀nyí sì gba gbogbo ohun èlò àti fèrè àwọn tí ó ti padà. Ibùdó ogun àwọn Midiani wà ní àfonífojì ní ìsàlẹ̀. Ibi tí ó wà.
To pongah Gideon mah kalah Israel kaminawk boih khaeah angmacae ih hmuenmae hoi mongkahnawk to a laksak moe, angmacae ohhaih ahmuen ah patoeh let; anih loe kami cumvai thumto hoiah caeh; to naah Midian kaminawk loe nihcae ohhaih aloih bang ih tangtling ah atai o.
9 Ní òru ọjọ́ náà Olúwa sọ fún Gideoni pé, “Dìde, dojú ogun kọ ibùdó ogun àwọn ará Midiani nítorí èmi yóò fi lé ọ lọ́wọ́.
To na aqum ah Angraeng mah Gideon khaeah, Angthawk loe, misatuh kaminawk ataihaih ahmuen ah caeh tathuk ah, nihcae to na ban ah kang paek boeh.
10 Ṣùgbọ́n bí ẹ̀rù àti kọlù wọ́n bá ń bà ọ́, yọ́ wọ ibùdó wọn lọ kí o mú Pura ìránṣẹ́ rẹ lọ́wọ́
Toe caeh tathuk hanah na zit nahaeloe, misatuh kaminawk ohhaih ahmuen ah na tamna Phurah hoiah nawnto caeh ah;
11 kí o sì fi ara balẹ̀ gbọ́ ohun tí wọ́n ń sọ nínú ibùdó náà. Lẹ́yìn èyí ọkàn rẹ̀ yóò le láti kọlù ibùdó náà.” Báyìí ni òun àti Pura ìránṣẹ́ rẹ̀ wọ ẹnu-ọ̀nà ibùdó yìí.
nihcae mah thuih ih lok to na thaih tih; to pacoengah loe misatuh kaminawk ohhaih ahmuen ah caeh tathuk hanah, na ban thacakhaih to om tih, tiah a naa. To pongah Gideon loe a tamna Phurah hoi nawnto misatuh kaminawk ataihaih tasa bang ih misatoephaih ahmuen ah caeh.
12 Àwọn ará Midiani, àwọn ará Amaleki àti gbogbo ènìyàn ìlà-oòrùn tó lọ ní àfonífojì bí eṣú ni wọ́n rí nítorí púpọ̀ wọn. Àwọn ìbákasẹ wọn kò sì lóǹkà, wọ́n sì pọ̀ bí yanrìn inú Òkun.
Midian kaminawk, Amalek kaminawk hoi ni angyae bangah kaom kaminawk loe azawn ah atai o; nihcae loe kroek laek ai pakhuh zetto oh o; nihcae ih kaengkuu hrangnawk doeh, kroek laek ai savuet zetto pop o.
13 Gideoni dé sí àsìkò tí ọkùnrin kan bẹ̀rẹ̀ sí í rọ́ àlá tí ó lá sí ọ̀kan nínú àwọn ọ̀rẹ́ rẹ̀. Ó ní, “Mo lá àlá kan, nínú àlá náà mo rí àkàrà kan tó ṣe róbótó tí a fi barle ṣe ń yí wọ inú ibùdó àwọn ará Midiani, ó sì kọlu àgọ́ pẹ̀lú agbára ńlá dé bi wí pé àgọ́ náà dojúdé, ó sì ṣubú.”
Gideon phak naah, kami maeto mah angmah ih ampui khaeah amang to thuih pae, khenah, amang ka sak; barli cang hoi sak ih takaw kae loe Midian kaminawk ohhaih ahmuen ah amlet tathuk; kahni im phak naah, kahni im to a taeh phaeng, kahni im loe amtimh rup, tiah a naa.
14 Ọ̀rẹ́ rẹ̀ dá a lóhùn pé, “Èyí kò le túmọ̀ sí ohun mìíràn ju idà Gideoni ọmọ Joaṣi ará Israẹli lọ: Ọlọ́run ti fi àwọn ará Midiani àti gbogbo ogun ibùdó lé e lọ́wọ́.”
Anih ih ampui mah, To hmuen loe kalah hmuen mak ai; Israel kami Joash capa Gideon ih sumsen ni; Sithaw mah Midian kaminawk hoi haeah katai misatuh kaminawk boih, anih ban ah paek boeh, tiah a naa.
15 Nígbà tí Gideoni gbọ́ àlá náà àti ìtumọ̀ rẹ̀, ó wólẹ̀ sin Ọlọ́run: lẹ́yìn náà ni ó padà sí ibùdó àwọn ọmọ Israẹli ó sì pè wọ́n pé, “Ẹ dìde! Nítorí pé Olúwa yóò lò yín láti ṣẹ́gun gbogbo ogun Midiani.”
To ih amang hoi amang lehkung ih lok to Gideon mah thaih naah, Sithaw to bok, Israel kaminawk ataihaih ahmuen ah amlaem let moe, Angthawk oh; Angraeng mah Midian kaminawk to nangcae ban ah paek boeh, tiah a thuih pae.
16 Nígbà tí ó ti pín àwọn ọ̀ọ́dúnrún ọkùnrin wọ̀n-ọn-nì sí ọ̀nà mẹ́ta, ó fi fèrè, pẹ̀lú àwọn òfìfo ìkòkò lé ẹnìkọ̀ọ̀kan wọn lọ́wọ́, iná sì wà nínú àwọn ìkòkò náà.
Kami cumvai thumtonawk to abu thumto ah tapraek pacoengah, mongkah hoi long laom thungah hmai paang pacoengah kaminawk hanah a paek boih.
17 Ó sọ fún wọn pé, “Ẹ máa wò mí, kí ẹ sì máa ṣe ohun tí mo bá ṣe. Nígbà tí mo bá dé igun ibùdó wọn ẹ ṣe ohun tí mo bá ṣe.
Nihcae khaeah, Kai hae na khen oh; ka sak ih baktih toeng ah sah oh; nihcae ohhaih kahni im ka phak naah, ka sak ih baktih toengah sah oh, tiah a naa.
18 Nígbà tí èmi àti àwọn ọkùnrin tí ó wà pẹ̀lú mi bá fun fèrè wa, bẹ́ẹ̀ ni kí ẹ̀yin náà ni gbogbo igun ibùdó tí ẹ̀ bá wà kí ẹ fun àwọn fèrè yín kí ẹ sì hó pé, ‘Fún Olúwa àti fún Gideoni.’”
Kaimah hoi ka taengah kaom kaminawk boih mah mongkah uengh o naah, nihcae ataihaih kahni im taeng boih ah mongkah to ueng o thuih loe, Angraeng hoi Gideon ih sumsen, tiah hang oh, tiah a naa.
19 Gideoni àti àwọn ọgọ́rùn-ún ọkùnrin tí ó wà pẹ̀lú rẹ̀ dé òpin ibùdó àwọn ará Midiani ní nǹkan bí agogo méjìlá padà. Wọ́n fun fèrè wọn, wọ́n sì tún fọ́ àwọn ìkòkò tí ó wà ní ọwọ́ mọ́lẹ̀.
To pongah Gideon hoi a taengah kaom kami cumvaitonawk to angthawk o moe, qum taning ih misatoep angthlaenghaih tue phak naah, nihcae ataihaih kahni imtaeng ah a caeh o; to naah mongkah to uengh o moe, a ban ah sin o ih long laomnawk to vah o phaeng.
20 Àwọn ẹgbẹ́ mẹ́tẹ̀ẹ̀ta fun fèrè wọn, wọ́n tún fọ́ àwọn ìkòkò wọn mọ́lẹ̀. Wọ́n mú àwọn fìtílà iná wọn ní ọwọ́ òsì wọn àti fèrè tí wọ́n ń fun ní ọwọ́ ọ̀tún wọn. Wọ́n pariwo hé è pé, “Idà kan fún Olúwa àti fún Gideoni!”
To naah abu thumto ah tapraek ih kaminawk boih mah mongkah to ueng o; long laomnawk to a vah o phaeng, banqoi bang hoiah hmaithaw to sin o moe, bantang bang hoiah mongkah to a sin o; Angraeng hoi Gideon ih sumsen, tiah a hang o.
21 Nígbà tí ọkùnrin kọ̀ọ̀kan dúró ní ipò rẹ̀ yí ibùdó àwọn Midiani ká, gbogbo àwọn ọmọ-ogun Midiani ń sá káàkiri, wọ́n ń pariwo bí wọ́n ṣe ń sálọ.
Kaminawk boih kahni im taengah angdoet o naah, Midian kaminawk to cawnh o boih; cawnh hoiah a hangh o.
22 Nígbà tí àwọn ọ̀ọ́dúnrún ọkùnrin wọ̀n-ọn-nì fun fèrè wọn, Olúwa sì yí ojú idà ọkùnrin kọ̀ọ̀kan padà sí ẹnìkejì rẹ̀ àti sí gbogbo ogun wọn. Àwọn ọmọ-ogun sì sá títí dé Beti-Sitta ní ọ̀nà Serera títí lọ dé ìpínlẹ̀ Abeli-Mehola ní ẹ̀bá Tabbati.
Kami cumvai thumtonawk mah mongkah uengh o naah, Angraeng mah misatuh kaminawk boih, angmacae ampuinawk to sumsen hoiah tuksak; misatuh kaminawk loe Zererah ahmuen Beth-Shittah vangpui ah, Tabbath vangpui taengah kaom Abel-Meholah ramri karoek to cawnh o.
23 Gbogbo àwọn ọmọ-ogun Israẹli láti ẹ̀yà Naftali, Aṣeri àti gbogbo Manase ni Gideoni ránṣẹ́ si, wọ́n wá wọ́n sì lé àwọn ará Midiani.
Naphtali, Asher hoi Manasseh ih kaminawk boih nawnto amhong o moe, Midian kaminawk to patom o.
24 Gideoni tún ránṣẹ́ sí gbogbo àwọn ìlú tí ó wà ní orí òkè Efraimu wí pé, “Ẹ jáde wá bá àwọn ará Midiani jà, kí ẹ tètè gba àwọn omi Jordani títí dé Beti-Bara kí wọ́n tó dé bẹ̀.” Báyìí ni a ṣe pe gbogbo ọkùnrin ológun Efraimu jáde tí wọ́n sì gba gbogbo àwọn à bá wọ odò Jordani títí dé Beti-Bara.
Midian kaminawk tuk hanah, Jordan vapui hoi Beth-Barah avang khoek to caeh oh loe, a ngang oh tiah, Gideon mah Ephraim mae boih ah laicaeh to patoeh. To pacoengah Ephraim kaminawk boih nawnto amkhueng o moe, Jordan vapui taeng Berth-Barah avang khoek to angang o.
25 Wọ́n mú méjì nínú àwọn olórí àwọn ará Midiani, àwọn náà ni Orebu àti Seebu. Wọ́n pa Horebu nínú àpáta Orebu, wọ́n sì pa Seebu níbi tí àwọn ènìyàn ti mọ̀ fún wáìnì tí a ń pè ní ìfúntí Seebu. Wọ́n lé àwọn ará Midiani, nígbà tí wọ́n gbé orí Orebu àti Seebu tọ Gideoni wá ẹni tí ó wà ní apá kejì Jordani.
Midian kaminawk zaehoikung misatuh angraeng hnetto, Oreb hoi Zeeb to a naeh o; Oreb to Oreb lungsong nuiah a hum o moe, Zeeb to Zeeb misurtui pasawhaih ahmuen ah a hum o. Midian kaminawk to patom o moe, Jordan vapui yaeh ah kaom Gideon khaeah Oreb hoi Zeeb ih lu to a sin pae o.

< Judges 7 >