< Judges 6 >
1 Àwọn ọmọ Israẹli sì túnṣe ohun tí ó burú ní ojú Olúwa, Ó sì fi wọ́n lé àwọn ará Midiani lọ́wọ́ fún ọdún méje.
Isarelnaw ni BAWIPA mithmu vah hno kahawihoehe a sak awh, hatdawkvah, BAWIPA ni Midian kut dawk kum 7 touh san a toung sak.
2 Agbára àwọn ará Midiani sì pọ̀ púpọ̀ lórí àwọn Israẹli, wọ́n sì hùwà ipá sí wọn, nítorí ìdí èyí, àwọn Israẹli sálọ sí àwọn orí òkè, wọ́n sì kọ́ àgọ́ fún ara wọn nínú ihò àpáta, àti nínú ọ̀gbun àti ní ibi agbára nínú àpáta.
Midiannaw ni Isarelnaw teh a rektap dawkvah, Isarelnaw ni kâhro nahanlah mon dawk talai kâkhu ka cak poung lah a tai awh.
3 Ní ìgbàkúgbà tí àwọn ọmọ Israẹli bá ti gbin ọ̀gbìn wọn, àwọn ará Midiani, àwọn ará Amaleki àti àwọn ará ìlà-oòrùn mìíràn yóò wá láti bá wọn jà.
Bangkongtetpawiteh, Isarelnaw ni law a sak awh nah tangkuem koe Midiannaw, Amaleknaw, hoi Kanîtholae taminaw ni pou a tho sin awh teh, pou a tuk awh.
4 Wọn yóò tẹ̀dó sí orí ilẹ̀ náà, wọn a sì bá irúgbìn wọ̀nyí jẹ́ títí dé Gasa, wọn kì í sì í fi ohun alààyè kankan sílẹ̀ fún àwọn ọmọ Israẹli, kì bá à ṣe àgùntàn, màlúù tàbí kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́.
Isarel ram thungvah tungpup rim a sak awh teh, talai dawk e ka paw e caticamu pueng Gaza totouh a raphoe pouh awh. Isarelnaw ni kâkawknae banghai tat pout laipalah, tu, maito, la totouh pek pouh awh hoeh.
5 Wọn a máa wá pẹ̀lú ohun ọ̀sìn wọn àti àwọn àgọ́ wọn, wọn a sì dàbí eṣú nítorí i púpọ̀ wọn. Ènìyàn kò sì lè ka iye àwọn ènìyàn náà bẹ́ẹ̀ ni àwọn ìbákasẹ, wọ́n pọ̀ dé bi pé wọn kò ṣe é kà ní iye, wọn a bo ilẹ̀ náà wọn a sì jẹ ẹ́ run.
Bangkongtetpawiteh, ahnimouh ni saring hoi rim khuehoi samtong yit touh ka phat lah a tho awh. Amamouh hoi kalauknaw teh touk thai lah awm hoeh. Isarel ram raphoe hanelah a tho awh.
6 Àwọn ará Midiani sì pọ́n àwọn ọmọ Israẹli lójú, wọ́n sọ wọ́n di òtòṣì àti aláìní, fún ìdí èyí wọ́n ké pe Olúwa nínú àdúrà fún ìrànlọ́wọ́.
Midian kecu dawk Isarel teh puenghoi roedeng a khang awh dawkvah, BAWIPA a kaw awh.
7 Nígbà tí àwọn ọmọ Israẹli ké pe Olúwa nítorí àwọn ará Midiani.
Midiannaw kecu dawk Isarel ni BAWIPA a kaw toteh,
8 Olúwa fi etí sí igbe wọn, ó sì rán wòlíì kan sí wọn, ẹni tí ó wí pé, “Èyí ni ohun tí Olúwa Ọlọ́run Israẹli wí: mo mú yín gòkè ti Ejibiti wá, láti oko ẹrú.
Isarelnaw koe BAWIPA ni profet buet touh a tha pouh.
9 Mo gbà yín kúrò nínú agbára Ejibiti àti kúrò ní ọwọ́ gbogbo àwọn aninilára yín. Mo lé wọn kúrò ní iwájú yín, mo sì fi ilẹ̀ wọn fún yín.
Na ka rektap e Izip kut dawk hoi thoseh, na ka pacekpahleknaw kut dawk hoi thoseh, nangmanaw na taran ahawi awh teh, ahnimanaw hah nangmouh hmalah ka pâlei vaiteh, a ram roup na poe awh han.
10 Mo wí fún un yín pé, ‘Èmi ni Olúwa Ọlọ́run yín; ẹ má ṣe sin àwọn òrìṣà àwọn ará Amori, ní ilẹ̀ ẹni tí ẹ̀yin ń gbé.’ Ṣùgbọ́n ẹ̀yin kò gbọ́rọ̀ sí ohun tí mo sọ.”
Kai teh nangmae BAWIPA Cathut doeh. Nangmouh na onae dawk kaawm e Amonnaw e cathutnaw hah taket awh hanh, ka ti eiteh, ka lawk hah na ngai awh hoeh atipouh.
11 Ní ọjọ́ kan angẹli Olúwa wá, ó sì jókòó ní abẹ́ igi óákù Ofira èyí ti ṣe ti Joaṣi ará Abieseri, níbi tí Gideoni ọmọ rẹ̀ ti ń lu ọkà jéró, níbi ìpọntí wáìnì láti fi pamọ́ kúrò níwájú àwọn ará Midiani.
Hahoi BAWIPA e kalvantami a tho pouh teh, Ophrah kho, Abiezrit capa Joash e kathen kung rahim vah a tahung. Joash e capa Gideon teh amae cang hah Midiannaw ni a pâphawng hoeh nahanelah, misur katinnae teng vah a katin pouh.
12 Nígbà tí angẹli Olúwa fi ara han Gideoni, ó wí fún un pé, “Olúwa wà pẹ̀lú rẹ, akọni ológun.”
BAWIPA e kalvantami ni ahni koe a kamphawng pouh teh, athakaawme ransa, BAWIPA teh nang koe ao atipouh navah,
13 Gideoni dáhùn pé, “Alàgbà, bí Olúwa bá wà pẹ̀lú wa, kí ló dé tí gbogbo ìwọ̀nyí fi ń ṣẹlẹ̀ sí wa? Níbi gbogbo àwọn iṣẹ́ ìyanu rẹ tí àwọn baba wa ròyìn rẹ̀ fún wa nígbà tí wọ́n wí pé, ‘Olúwa kò ha mú wa gòkè láti ilẹ̀ Ejibiti wá?’ Ṣùgbọ́n nísinsin yìí Olúwa ti kọ̀ wá sílẹ̀, ó sì ti fi wá lé àwọn ará Midiani lọ́wọ́.”
Oe BAWIPA Cathut teh maimouh koe awm pawiteh, bangkongmaw hete hnonaw teh maimouh koe a pha sak vaw. Mintoenaw teh BAWIPA ni Izip ram hoi a tâco sak awh nahoehmaw, kai koe ouk a dei awh e kângairuhnonaw te nâne. Hatei, atuteh BAWIPA ni na pahnawt teh, Midian kut dawk na poe toe khe telah a ti.
14 Olúwa sì yípadà sí i, ó sì wí fún un pé, “Lọ nínú agbára tí o ní yìí, kí o sì gba àwọn ará Israẹli sílẹ̀ kúrò lọ́wọ́ àwọn ará Midiani. Èmi ni ó ń rán ọ lọ.”
Hahoi Bawipa ni a kamlang sin teh, atu na tawn e thaonae kâuep hoi cet haw, Midian kut dawk hoi Isarel teh rasat haw, Kai ni na patoun e nahoehmaw atipouh.
15 Gideoni sì dáhùn pé, “Yéè olúwa mi, ọ̀nà wo ni èmi yóò fi gba Israẹli là? Ìdílé mi ni ó jẹ́ aláìlera jù ní Manase, àti pé èmi ni ó sì kéré jù ní ìdílé baba mi.”
Hahoi teh Gideon ni, BAWIPA kaimouh ni Isarelnaw bangtelah hoi maw ka rasa thai awh han vaw. Ka miphun teh Manasseh thung dawk hoe ka mathoe e, kama hai thoseh ka hmaunawngha thung dawk kathoungpounge lah ka o.
16 Olúwa sì dáhùn pé, “Èmi yóò wà pẹ̀lú rẹ, ìwọ yóò sì pa gbogbo àwọn ará Midiani láì ku ẹnìkankan.”
Hahoi BAWIPA ni a pato teh, hatei nang koe ka o han, Midiannaw teh tami buet touh na thei e patetlah na thei han doeh atipouh.
17 Gideoni sì dáhùn pé, nísinsin yìí tí mo bá bá ojúrere rẹ pàdé, fún mi ní àmì pé ìwọ ni ń bá mi sọ̀rọ̀.
Gideon ni nang koehoi minhmai kahawi ka hmawt pawiteh, nang hoi atu kâpatonae panue nahanelah, kamnuenae hno buet touh na hmawt sak haw.
18 Jọ̀wọ́ má ṣe kúrò níbí títí èmi yóò fi mú ọrẹ wá fún ọ kí n sì gbé e sí iwájú rẹ. Olúwa sì wí pé, “Èmi yóò dúró títí ìwọ yóò fi dé.”
Hno buetbuet touh ka sin vaiteh, na hmalah ka thokhai hoehroukrak hete hmuen koehoi na kampuen pouh hanh ei a telah ka kâhei navah ahni ni, na ban hoehroukrak ka o han a ti.
19 Gideoni sì yára wọ ilé lọ, ó sì pa ọ̀dọ́ ewúrẹ́ kan, wọ́n sì sè é, ó sì mú ìyẹ̀fun efa kan, ó fi ṣe àkàrà aláìwú. Ó gbé ẹran náà sínú agbọ̀n, ṣùgbọ́n ó fi ọbẹ̀ rẹ̀ sínú ìkòkò, ó gbé wọn jáde tọ angẹli náà wá bí ọrẹ lábẹ́ igi óákù.
Gideon ni a cei teh, hmaeca buet touh, tavai ephah buet touh, tonphuenhoehe vaiyeinaw hah a sin teh, hmae moi hah tangthung dawk a pâseng teh, hmae moi hang teh hlaam dawk a ta teh, kalvantami aonae koe bengkengkung rahim a sin teh a poe.
20 Angẹli Ọlọ́run náà sì wí fún un pé, “Gbé ẹran náà àti àkàrà àìwú náà, sí orí àpáta yìí, kí o sì da omi ọbẹ̀ rẹ̀ sí orí rẹ̀.” Gideoni sì ṣe bẹ́ẹ̀.
Hahoi Cathut e kalvantami ni ahni koe, moi hoi tonphuenhoehe hah lat loe, hete talung van hrueng loe, a hang hoi awi loe atipouh. Hottelah a sak pouh.
21 Angẹli Olúwa sì fi orí ọ̀pá tí ó wà ní ọwọ́ rẹ̀ kan ẹran àti àkàrà àìwú náà. Iná sì jáde láti inú àpáta, ó sì jó ẹran àti àkàrà náà, kò sì rí angẹli náà mọ́.
Hahoi teh, BAWIPA e kalvantami ni a kut dawk a sin e sonron a dâw teh, moi hoi tonphuenhoehe vaiyei hah a nep. Hahoi talung thung hoi a tâco teh, moi hoi tonphuenhoehe vaiyei hmai he a kak pouh. BAWIPA e kalvantami teh yout a kahma pouh.
22 Nígbà tí Gideoni sì ti mọ̀ dájúdájú pé angẹli Olúwa ni, ó ké wí pé, “Háà! Olúwa Olódùmarè! Mo ti rí angẹli Olúwa ní ojúkorojú!”
Hat torei teh, Gideon ni BAWIPA e kalvantami tie a panue. Hahoi teh, Oe Bawipa Jehovah, atuteh BAWIPA e kalvantami minhmai rek ka hmu toe a ti.
23 Ṣùgbọ́n Olúwa wí fún un pé, “Àlàáfíà! Má ṣe bẹ̀rù, ìwọ kì yóò kùú.”
BAWIPA ni na lungpuen hanh. Yawhawinae awmseh. Nang teh na dout mahoeh.
24 Báyìí ni Gideoni mọ pẹpẹ kan fún Olúwa níbẹ̀, ó sì pe orúkọ rẹ̀ ní “Àlàáfíà ni Olúwa.” Ó sì wà ní Ofira ti Abieseri títí di òní.
Hote hmuen koe Gideon ni Bawipa hanlah thuengnae a sak teh, BAWIPA teh roumnae (Jehovah-shaloam) telah a phung. Abiezrit capa e hmuen koe Ophrah kho dawk sahnin ditouh ao.
25 Ní òru ọjọ́ náà Olúwa wí fún un pé, mú akọ màlúù baba rẹ, àní akọ màlúù kejì ọlọ́dún méje. Wó pẹpẹ Baali baba rẹ lulẹ̀, kí o sì bẹ́ igi ère òrìṣà Aṣerah tí ó wà ní ẹ̀gbẹ́ rẹ̀ lulẹ̀.
Hote hnin tangmin vah BAWIPA ni na poe e maito matawng hoi apâhni e kum sari touh e maitotan hah sin nateh, na pa ni a sak e Baal cathut thuengnae khoungroe hah raphoe nateh, khoungroe teng kaawm e Asherah thing hah tâtueng loe.
26 Lẹ́yìn èyí kí o wá mọ pẹpẹ èyí tí ó yẹ fún Olúwa Ọlọ́run rẹ lórí òkè yìí. Kí o sì mú akọ màlúù kejì, kí o sì mú igi ère òrìṣà Aṣerah tí ìwọ bẹ́ lulẹ̀ rú ẹbọ sísun sí Olúwa.
Kai ni ka dei e patetlah hete talung van vah, BAWIPA hanlah thuengnae khoungroe na sak hnukkhu, na tâtueng e thing hoi apâhni e maito hah hmaisawi thuengnae lah sak loe atipouh.
27 Gideoni mú mẹ́wàá nínú àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀, ó sì ṣe bí Olúwa ti pàṣẹ fún un ṣùgbọ́n, nítorí ó bẹ̀rù àwọn ará ilé baba rẹ̀ àti àwọn ènìyàn ìlú náà kò ṣe é ní ọ̀sán, òru ni ó ṣe.
Gideon ni amae sannaw 10 touh a kaw teh, BAWIPA ni a dei e patetlah a sak, a na pa e imthungkhunaw thoseh, khocanaw thoseh a taki teh, kanîthun vah a sak ngam hoeh dawkvah tangmin vah a sak.
28 Nígbà tí ilẹ̀ ọjọ́ kejì mọ́, tí àwọn ènìyàn ìlú náà jí, wọ́n rí i pé àti fọ́ pẹpẹ Baali àti pé a ti bẹ́ igi ère òrìṣà Aṣerah tí ó wà ní ẹ̀gbẹ́ rẹ̀, a sì ti fi akọ màlúù kejì rú ẹbọ lórí pẹpẹ tí a ṣẹ̀ṣẹ̀ mọ.
Amom khocanaw a thaw awh navah, Baal cathut e khoungroe peng a kâraphoe teh, ateng kaawm e Asherah thing hai a rawp teh, a hnukkhu sak e thuengnae khoungroe van vah, apâhni e maitotan thueng e hah a hmu awh.
29 Àwọn ènìyàn ìlú náà bi ara wọn wí pé, “Ta ni ó ṣe èyí?” Lẹ́yìn tí wọn fi ara balẹ̀ ṣe ìwádìí, wọ́n gbọ́ wí pé, “Gideoni ọmọ Joaṣi ni ó ṣe é.”
Hat toteh, hete hno heh apimouh ka sak telah buet touh hoi buet touh akung a kâkhei awh navah, hete hno teh Joash capa Gideon ni a sak telah tami tangawn ni ati awh.
30 Àwọn ọkùnrin ìlú náà sì wí fún Joaṣi wí pé, “Mú ọmọ rẹ jáde wá. Ó ní láti kú nítorí pé ó ti wó pẹpẹ Baali lulẹ̀ ó sì ti ké ère òrìṣà Aṣerah tí ó wà ní ẹ̀bá rẹ̀ lulẹ̀.”
Hattoteh khocanaw ni Joash koe, nange capa ni Baal cathutnaw e khoungroe peng a raphoe teh, ateng kaawm e Asherahkung hah a tâtueng dawkvah, ahni teh thei hanelah tâcawt sak hottelah atipouh awh.
31 Ṣùgbọ́n Joaṣi bi àwọn èrò tí wọ́n fi ìbínú dúró tì í wí pé, “Ẹ̀yin yóò ha gbìjà Baali bí? Ẹ̀yin yóò ha gbà á sílẹ̀ bí? Ẹnikẹ́ni tí ó bá gbìjà rẹ̀ kíkú ni olúwa rẹ̀ yóò kú ní òwúrọ̀. Bí Baali bá ṣe Ọlọ́run nítòótọ́ yóò jà fún ara rẹ̀ bí ẹnikẹ́ni bá wó pẹpẹ rẹ̀ lulẹ̀.”
Hateiteh, Joash ni ahnimouh koe nangmouh teh Baal cathut koelah maw na kampang awh han, hotnaw na rungngang awh han, ahni koelah kampang e tami teh, khodai hoehnahlan dout lawiseh. Baal teh cathut katang pawiteh, ahnie thuengnae khoungroe a raphoe kecu dawk, ama ni a sak e teh amamouh ni khang na lawiseh, telah bout atipouh.
32 Fún ìdí èyí ní ọjọ́ náà wọ́n pe Gideoni ní “Jerubbaali” wí pé, “Jẹ́ kí Baali bá a jà,” nítorí pé ó ti wó pẹpẹ Baali.
Hottelah Baal cathut e khoungroe ka raphoe e tami teh, amamouh ni a sak e patetlah ahni ni khang sak lawiseh, ati teh, amae capa hah hat hnin vah, Jerubbaal telah a min a phung.
33 Láìpẹ́ jọjọ, àwọn ogun àwọn Midiani, ti àwọn Amaleki àti ti àwọn ènìyàn ìhà ìlà-oòrùn yòókù kó ara wọn jọ pọ̀ ní ìṣọ̀kan, wọ́n sì kọjá Jordani wọ́n sì tẹ̀dó sí àfonífojì Jesreeli.
Hattoteh Midian tami, Amalek tami, Kanîtholae tami pueng a kamkhueng awh teh, Jezreel yawn tanghling dawk a roe awh.
34 Ẹ̀mí Olúwa sì bà lé Gideoni, ó sì fun fèrè ìpè, láti pe àwọn ará Abieseri láti tẹ̀lé òun.
BAWIPA e Muitha teh Gideon koe a pha. Gideon ni mongka a ueng teh, Abiezer capanaw ni a hnuk a kâbang awh.
35 Ó rán àwọn oníṣẹ́ la ilẹ̀ Manase já pé kí wọ́n dira ogun, àti sí Aṣeri, Sebuluni àti Naftali gbogbo pẹ̀lú sì lọ láti pàdé wọn.
A patounenaw hah Manasseh ram pueng dawk a patoun teh, Manasseh miphun pueng ni a kâbang awh. Asher ram, Zebulun ram, Naphtali ram koe lahai a patounenaw bout a patoun teh, ahnimanaw hai kamkhuengnae koe a tho awh.
36 Gideoni wí fún Ọlọ́run pé, “Bí ìwọ yóò bá gba Israẹli là nípasẹ̀ mi bí ìwọ ti ṣe ìlérí—
Gideon ni Cathut koe nang ni na dei e patetlah Isarel miphunnaw hah kaie kut dawk hoi na hlout sak katang han na pawiteh,
37 kíyèsi, èmi yóò fi awọ irun àgùntàn lé ilẹ̀ ìpakà ní alẹ́ òní. Bí ìrì bá sẹ̀ sí orí awọ yìí nìkan tí gbogbo ilẹ̀ yòókù sì gbẹ, nígbà náà ni èmi yóò mọ̀ lóòótọ́ pé ìwọ yóò gba Israẹli là nípasẹ̀ mi bí ìwọ ti sọ.”
kai ni tu buet touh e muen hah thongma dawk ka ta han. Hote tumuen teh tadamtui cukruk bawm boilah, talai remphui pawiteh, na dei e patetlah Isarel miphunnaw kaie kut dawk hoi na rungngang han tie hah ka panue han.
38 Èyí ni ó sì ṣẹlẹ̀. Nígbà tí Gideoni jí ní òwúrọ̀ ọjọ́ kejì, ó sì fún irun àgùntàn náà, ọpọ́n omi kan sì kún.
Hatteh ka hei e patetlah ao. Amom a thaw teh, tumuen a kasu boteh tadamtui kawlung buet touh yikkawi.
39 Gideoni sì tún wí fún Ọlọ́run pé, “Jọ̀wọ́ má ṣe bínú sí mi, ṣùgbọ́n jẹ́ kí n tún wá ìdánilójú kan sí i, èmi bẹ̀ ọ́ jẹ́ kí n fi awọ irun yìí ṣe ìdánwò kan sí i. Ní àsìkò yìí, jẹ́ kí awọ irun yìí gbẹ kí gbogbo ilẹ̀ sì tutù pẹ̀lú ìrì.”
Gideon ni na lung khuek sak hanh ei, vai touh bout ka dei einei. Tu buet touh e muen hoi atu vai touh dueng na tanouk sak ei. Talai pueng tadamtui a duk vaiteh, tumuen remphui naseh, telah Cathut koe a hei e patetlah,
40 Ní òru náà Ọlọ́run ṣe bẹ́ẹ̀, awọ irun àgùntàn nìkan ni ó gbẹ; gbogbo ilẹ̀ yòókù sì tutù nítorí ìrì.
hote karum hai Cathut ni a sak pouh teh, talai pueng a duk teh tumuen remphui lah ao.