< Judges 4 >

1 Lẹ́yìn ikú Ehudu, àwọn ènìyàn Israẹli sì tún ṣẹ̀, wọ́n ṣe ohun tí ó burú ní ojú Olúwa.
Ihade da bogobeba: le, Isala: ili dunu da bu eno Hina Godema wadela: i hou hamosu.
2 Nítorí náà Olúwa jẹ́ kí Jabini, ọba àwọn Kenaani, ẹni tí ó jẹ ọba ní Hasori, ṣẹ́gun wọn. Orúkọ olórí ogun rẹ̀ ni Sisera ẹni tí ń gbé Haroseti-Hagoyimu.
Amaiba: le, Hina Gode da logo doasibiba: le, Ya: ibini (Ga: ina: ne hina bagade amo da Ha: iso moilai bai bagade ouligisu) da ili hasali. Ya: ibini ea dadi gagui ouligisu da Sisela. E da Halosede Dienadaile moilaiga esalu.
3 Nítorí tí ó ní ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀rún kẹ̀kẹ́ ogun irin, ó sì ń pọ́n Israẹli lójú gidigidi fún ogún ọdún, Israẹli ké pe Olúwa fún ìrànlọ́wọ́.
Ya: ibini da sa: liode ouliga hamoi amo 900 gagui galu. E da ougiwane gasafiwane ode 20 amoga Isala: ili dunu ouligisu. Amalalu, Isala: ili dunu da Hina Godema fidima: ne wele sia: i dagoi.
4 Debora, wòlíì obìnrin, aya Lapidoti ni olórí àti aṣíwájú àwọn ará Israẹli ní àsìkò náà.
Uda afae amo ea dio Debola (La: bidode idua) da balofede uda (Gode Sia: alofesu uda) esalu. E da Isala: ili dunu ilima fofada: su ouligisu esalu.
5 Òun a máa jókòó ṣe ìdájọ́ ní abẹ́ igi ọ̀pẹ tí a sọ orúkọ rẹ̀ ní ọ̀pẹ Debora láàrín Rama àti Beteli ní ilẹ̀ òkè Efraimu, àwọn ará Israẹli a sì máa wá sí ọ̀dọ̀ rẹ̀ láti yanjú èdè-àìyedè tí wọ́n bá ní sí ara wọn, tàbí láti gbọ́ ohùn Olúwa láti ẹnu rẹ̀.
Ea hou da agoane. Lama amola Bedele moilai gilisisu Ifala: ime agolo soge ganodini gala, amo dogoa sogebi gumudi agoai ifa ea ougia e da fili, Isala: ili dunu da ea fidisu sia: lamusa: masu
6 Ní ọjọ́ kan, ó ránṣẹ́ pe Baraki ọmọ Abinoamu, ẹni tí ń gbé ní Kedeṣi ní ilẹ̀ Naftali, ó sì wí fún un pé, “Olúwa, Ọlọ́run Israẹli pa á ní àṣẹ fún un pé, ‘Kí ó kó ẹgbẹ̀rún mẹ́wàá àwọn akọni ọkùnrin jọ láti ẹ̀yà Naftali àti ẹ̀yà Sebuluni bí ẹgbẹ́ ogun, kí o sì síwájú wọn lọ sí òkè Tabori.
Eso afaega, e da Bela: ge (Abinoa: me egefe. E da Gidese moilai bai bagade, Na: fadalai soge ganodini esalu) amo ema misa: ne sia: i. Debola da ema amane sia: i, “Hina Gode, Isala: ili dunu ilia Gode, da dima amane hamoma: ne sia: sa, ‘Di da Na: fadalai fi amola Sebiula: ne fi amoga dunu 10,000 lale, ili Da: ibo Goumiga oule masa.
7 Èmi yóò sì fa Sisera olórí ogun Jabini, pẹ̀lú kẹ̀kẹ́ ogun rẹ àti àwọn ogun rẹ, sí odò Kiṣoni èmi yóò sì fi lé ọ lọ́wọ́ ìwọ yóò sì ṣẹ́gun wọn níbẹ̀.’”
Na da Ya: ibini ea dadi gagui hina ouligisu Sisela amo dilima gegema: ne Gisione Hano amoga oule misunu. E da sa: liode amola dadi gagui bagohame gagui dialebe ba: mu. Be Na da di fidimuba: le, di da e hasalimu.’”
8 Baraki sì dá a lóhùn pé, “Èmi yóò lọ tí ìwọ ó bá bá mi lọ, ṣùgbọ́n tí ìwọ kì yóò bá bá mi lọ, èmi kì yóò lọ.”
Amalalu, Bela: ge da Debolama bu adole i, “Di da na sigi ahoasea, na da masunu. Be di da hame sigi ahoasea, na da hame masunu.”
9 Debora dá a lóhùn pé, “ó dára, èmi yóò bá ọ lọ. Ṣùgbọ́n ọlá ìṣẹ́gun tí o ń lọ yìí kò ní jẹ́ tìrẹ, nítorí Olúwa yóò fi Sisera lé obìnrin lọ́wọ́,” báyìí Debora bá Baraki lọ sí Kedeṣi.
Debola da amane sia: i, “Defea! Na da ani masunu. Be di da Sisela amoma hasali, ilia da hame sia: mu. Bai Hina Gode da Sisela amo uda afae amoma medole legema: ne imunu.” Amaiba: le, Debola da Bela: ge sigi asili, Gedese moilai bai bagadega doaga: musa: asi.
10 Nígbà tí Baraki pe ẹ̀yà Sebuluni àti ẹ̀yà Naftali sí Kedeṣi ẹgbẹ̀rún mẹ́wàá akíkanjú ọkùnrin ogun tẹ̀lé e, Debora pẹ̀lú bá wọn lọ.
Bela: ge da Sebiula: ne fi amola Na: fadalai fi amo Gedese moilai bai bagadega misa: ne wele sia: i. Amola dunu 10,000 da ema fa: no bobogei. Debola da e sigi asi.
11 Ǹjẹ́ Heberi ọmọ Keni, ti ya ara rẹ́ kúrò lọ́dọ̀ àwọn ọmọ Keni, àní àwọn ọmọ Hobabu, àna Mose, ó sì pa àgọ́ rẹ̀ títí dé ibi igi óákù Saananimu, tí ó wà ni agbègbè Kedeṣi.
Amo esoha, Ginaide dunu ea dio amo Hibe da Ginaide dunu eno fisili, ea hawa: i fisu diasu amo Gidese moilai gadenene gagui. E da ouge ifa Sa: na: nimi sogega amo gadenene falifai. Ginaide dunu da Houba: be (Mousese ea bai) amo egaga fi.
12 Nígbà tí a sọ fún Sisera pé Baraki ọmọ Abinoamu ti kó ogun jọ sí òkè Tabori,
Sisela da Bela: ge da Da: ibo Goumiga asi, amo nabi dagoi.
13 Sisera kó gbogbo kẹ̀kẹ́ ogun irin rẹ̀ tí ṣe ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀rún àti gbogbo àwọn ọmọ-ogun tí ó wà pẹ̀lú rẹ̀, láti Haroseti tí àwọn orílẹ̀-èdè wá sí odò Kiṣoni.
Amalalu, e da ea sa: liode 900 agoane amola ea dadi gagui dunu huluane Halosede Dienadaile amoma misa: ne wele sia: i. Amalalu, e da ili Gisione Hano amoga asunasi.
14 Debora sì wí fún Baraki pé, “Lọ! Lónìí ni Olúwa fi Sisera lé ọ lọ́wọ́, Olúwa ti lọ síwájú rẹ.” Baraki sì síwájú, àwọn ọmọ-ogun rẹ̀ ẹgbẹ̀rún mẹ́wàá sì tẹ̀lé e lẹ́yìn, wọ́n sì kọjá sí òkè Tabori.
Amalalu, Debola da Bela: gema amane sia: i, “Masa! Hina Gode da di oule bisili ahoa. Wali eso E da Sisela hasalima: ne hou dima i dagoi.” Amaiba: le, Bela: ge da ea 10,000 dunu amo Da: ibo Goumi hagudu amoga oule asi.
15 Olúwa sì mú ìdàrúdàpọ̀ wá sí àárín ogun Sisera, Olúwa sì fi ojú idà ṣẹ́gun Sisera àti àwọn oníkẹ̀kẹ́ ogun àti ọmọ-ogun orí ilẹ̀ ní iwájú Baraki. Sisera sì sọ̀kalẹ̀ lórí kẹ̀kẹ́-ẹṣin rẹ̀ ó sì fi ẹsẹ̀ sálọ.
Bela: ge amola ea dadi gagui da Siselama doagala: loba, Hina Gode da hamobeba: le, Sisela, ea sa: liode amola dadi gagui da beda: iba: le uguguli doula agoane asi. Sisela da ea sa: liode amo fisili, emoga hobea: i.
16 Baraki àti àwọn ogun rẹ̀ sì lé àwọn ọ̀tá náà, àwọn ọmọ-ogun orílẹ̀ àti àwọn kẹ̀kẹ́ ogun wọn títí dé Haroseti ti àwọn orílẹ̀-èdè, gbogbo ogun Sisera sì ti ojú idà ṣubú, kò sí ọ̀kan tí ó lè sálà tàbí tí ó wà láààyè.
Bela: ge da sa: liode amola dadi gagui huluane sefasili, Halosiede Dienadaile amoga doaga: i. E da Sisela ea dadi gagui dunu huluane medole legei. Dunu afae esalebe hame ba: i.
17 Ṣùgbọ́n Sisera ti fi ẹsẹ̀ sálọ sí àgọ́ Jaeli aya Heberi ẹ̀yà Keni: nítorí ìbá dá ọ̀rẹ́ àlàáfíà wà láàrín Jabini ọba Hasori àti ìdílé Heberi ti ẹ̀yà Keni.
Sisela da hobeale, Ya: iele (Ginaide dunu Hibe amo idua) amo ea abula diasuga doaga: i. Bai Ha: iso hina bagade Ya: ibini amola Hibe ea sosogo fi da olofoiwane esalu.
18 Jaeli sì jáde síta láti pàdé Sisera, ó sì wí fún un pé, “Wọlé sínú àgọ́ mi, Olúwa mi, wọlé wá má ṣe bẹ̀rù nítorí pé ààbò ń bẹ fún ọ.” Ó sì yà sínú àgọ́ rẹ̀, ó sì fi aṣọ bò ó.
Ya: iele da gadili asili, Sisela amoma amane sia: i, “Na abula diasu ganodini golili misa. Mae beda: ma!” Amaiba: le, e da ganodini golili sa: ili, Ya: iele da e wamoaligimusa: , abulaga dedeboi.
19 Sisera wí pé, “Òrùngbẹ ń gbẹ́ mí, jọ̀wọ́ fún mi ní omi mu.” Ó sì ṣí awọ wàrà kan, ó sì fún un mu ó sì tún daṣọ bò ó padà.
E da Ya: ielema amane sia: i, “Na da hano hanai galebe. Hano nama ima.” Ya: iele da goudi gadofo nodomeiga gebo dodo maga: me disu amo doasili, ema dodo maga: me i. Amalalu, e da Sisela wamoaligima: ne, bu dedebosi.
20 Sisera sọ fún Jaeli pé, “Kí ó dúró ní ẹnu-ọ̀nà àgọ́, àti pé bí ẹnikẹ́ni bá béèrè bóyá òun wà níbẹ̀ kí ó sọ pé, ‘Kò sí ẹnìkankan ní ibẹ̀.’”
E da Ya: ielema amane sia: i, “Di da abula diasu logo ga: su amogawi ouleloma. Dunu da misini amola ‘dunu da esalabela: iya’ adole ba: sea, ‘hameyeiya’ fawane sia: ma.”
21 Ṣùgbọ́n Jaeli ìyàwó Heberi mú ìṣó àgọ́ tí ó mú àti òòlù ní ọwọ́ rẹ̀, ó sì yọ́ wọ inú ibi tí ó sùn, nígbà tí ó ti sùn fọnfọn, nígbà náà ni ó kan ìṣó náà mọ́ òkè ìpéǹpéjú rẹ̀, ó sì wọlé ṣinṣin, ó sì kú.
Sisela e da bagadewane helebeba: le, gola dialebe ba: i. Amalalu, Ya: iele e da wamo gogoli misini, ha: ma amola abula diasu gagumusa: goge agei lale, Sisela ea dialuma gele dabaga dabasalili, osoboga doasa: i ba: i.
22 Nígbà tí Baraki dé bí ó ti ń lépa Sisera, Jaeli láti pàdé rẹ̀, wá, èmi yóò fi ẹni tí ìwọ ń wá hàn ọ́, báyìí ni ó tẹ̀lé e wọ inú àgọ́ lọ, kíyèsi Sisera dùbúlẹ̀ síbẹ̀ pẹ̀lú ìṣó àgọ́ ní agbárí rẹ̀ tí a ti kàn mọ́lẹ̀ ṣinṣin tí ó sì ti kú.
Bela: ge da Sisela hogomusa: manoba, Ya: iele da ema gadili yosia: musa: ahoanoba, amane sia: i, “Guiguda: misa! Na da dunu di hogosa, amo dima olelemu.” Amaiba: le, e da abula diasu ganodini golili sa: ili, Sisela amo ea dialuma sone osoboga dabagala: le, bogoi dagoi dialebe ba: i.
23 Ní ọjọ́ náà ni Ọlọ́run ṣẹ́gun Jabini ọba àwọn ará Kenaani ní iwájú àwọn ẹ̀yà Israẹli.
Amo esohaga, Gode da fidiba: le, Isala: ili dunu da Ya: ibini, Ga: ina: ne hina bagade amo hasalasi.
24 Ọwọ́ àwọn ọmọ Israẹli sì le, ó sì ń lágbára síwájú àti síwájú sí i lára Jabini ọba Kenaani, títí wọ́n fi run òun àti àwọn ènìyàn rẹ̀.
Ilia da mae yolesili gebe minibagei ahoanawane, ilia ha lai dunu da huluane gugunufinisi dagoi ba: i.

< Judges 4 >