< Judges 3 >

1 Àwọn wọ̀nyí ni àwọn orílẹ̀-èdè tí Olúwa fi sílẹ̀ láti dán àwọn ìran tuntun ní Israẹli wò, àwọn ìran tí kò ì tí ì ní ìrírí ogun àwọn ará Kenaani.
Na ko nga iwi enei i waiho e Ihowa ko ratou hei whakamatautau i a Iharaira, ara ko nga mea o Iharaira kihai i mohio ki nga pakanga katoa o Kanaana;
2 (Ó ṣe èyí láti fi kọ́ àwọn ìran Israẹli tí kò rí ogun rí níbí a ti ṣe ń jagun).
Mo nga whakatupuranga ano ia o nga tamariki a Iharaira kia mohio, kia ako ki te whawhai, ara mo te hunga kihai i mohio ki tera i mua;
3 Àwọn ìjòyè ìlú Filistini márààrún, gbogbo àwọn ará Kenaani, àwọn ará Sidoni, àti àwọn ará Hifi tí ń gbé ní àwọn òkè Lebanoni bẹ̀rẹ̀ láti òkè Baali-Hermoni títí dé Lebo-Hamati.
Na, ko nga rangatira tokorima o nga Pirihitini, ko nga Kanaani katoa, ko nga Haironi ratou ko nga Hiwi i noho i Maunga Repanona, i Maunga Paaraheremona a tae noa ki te haerenga atu ki Hamata.
4 A fi àwọn ènìyàn náà sílẹ̀ láti dán àwọn Israẹli wò bóyá wọn yóò gbọ́rọ̀ sí àwọn òfin Olúwa, èyí tí ó ti fi fún àwọn baba wọn láti ipasẹ̀ Mose.
Ko ratou hei whakamatautau mo Iharaira, kia mohiotia ai e rongo ranei ratou ki nga whakahau a Ihowa i whakahaua e ia ki o ratou matua, he mea whakapuaki na Mohi.
5 Àwọn ọmọ Israẹli gbé láàrín àwọn ará Kenaani, àwọn ará Hiti àwọn ará Amori, àwọn ará Peresi, àwọn ará Hifi àti àwọn ará Jebusi.
Na ka noho nga tamariki a Iharaira ki waenganui o nga Kanaani, o nga Hiti, o nga Amori, o nga Perihi, o nga Hiwi, o nga Iepuhi:
6 Dípò kí wọ́n run àwọn ènìyàn wọ̀nyí, Israẹli ń fẹ́ àwọn ọmọbìnrin wọn, wọ́n sì ń fi àwọn ọmọbìnrin Israẹli fún àwọn ará ilẹ̀ náà ní aya, wọ́n sì ń sin àwọn òrìṣà wọn.
A ka tango i a ratou tamahine hei wahine ma ratou, ka hoatu hoki i a ratou tamahine ki a ratou tama, ka mahi ano hoki ki o ratou atua.
7 Àwọn ọmọ Israẹli sì ṣe èyí tí ó burú níwájú Olúwa, wọ́n gbàgbé Olúwa Ọlọ́run wọn, wọ́n sì ń sin Baali àti Aṣerah.
Na kua mahi nga tamariki a Iharaira i te kino i te tirohanga o Ihowa, wareware ake ki a Ihowa, ki to ratou Atua, mahi ana hoki ki nga Paara, ki te Ahataroto.
8 Ìbínú Olúwa sì ru sí Israẹli tó bẹ́ẹ̀ tí ó fi jẹ́ kí Kuṣani-Riṣataimu ọba Aramu-Naharaimu bá wọn jà kí ó sì ṣẹ́gun wọn, Israẹli sì ṣe ẹrú rẹ̀ fún ọdún mẹ́jọ.
Na ka mura te riri o Ihowa ki a Iharaira, a hokona atu ana ratou e ia ki te ringa o Kuhanarihataimi kingi o Mehopotamia. Na e waru nga tau i mahi ai nga tama a Iharaira ki a Kuhanarihataimi.
9 Ṣùgbọ́n nígbà tí Israẹli kígbe sí Olúwa, Òun gbé olùgbàlà kan dìde fún wọn, ẹni náà ni Otnieli ọmọ Kenasi àbúrò Kalebu tí ó jẹ́ ọkùnrin, ẹni tí ó gbà wọ́n sílẹ̀.
A, no te tangihanga a nga tamariki a Iharaira ki a Ihowa, ka whakaarahia ake e Ihowa he kaiwhakaora mo nga tamariki a Iharaira, nana ratou i whakaora; ara a Otoniere tama a Kenaha teina o Karepe.
10 Ẹ̀mí Olúwa bà lé e, òun sì ṣe ìdájọ́ Israẹli, ó sì síwájú wọn lọ sí ogun. Olúwa sì fi Kuṣani-Riṣataimu ọba Aramu lé Otnieli lọ́wọ́, ẹni tí ọwọ́ rẹ̀ sì borí Kuṣani-Riṣataimu.
Na i tau iho ki runga i a ia te wairua o Ihowa, a i whakawa ia mo Iharaira; i haere hoki ki te whawhai; a homai ana e Ihowa ki tona ringa a Kuhanarihataimi kingi o Mehopotamia: na kua kaha tona ringa ki te whawhai ki a Kuhanarihataimi.
11 Ilẹ̀ náà sì wà ní àlàáfíà fún ogójì ọdún títí tí Otnieli ọmọ Kenasi sì kú.
A e wha tekau nga tau i okioki ai te whenua i te whawhai. Na ka mate a Otoniere, tama a Kenaha.
12 Àwọn ọmọ Israẹli sì tún padà sí ìwà ẹ̀ṣẹ̀ wọn, wọ́n sì ṣe èyí tí ó burú ní iwájú Olúwa, fún ìdí iṣẹ́ búburú yìí, Olúwa fún Egloni, ọba àwọn Moabu ní agbára ní orí Israẹli.
Na ka mahi kino ano nga tama a Iharaira i te tirohanga a Ihowa, a ka whakakahangia e Ihowa a Ekerona kingi o Moapa ki te whawhai ki a Iharaira, mo ratou i mahi kino i te tirohanga a Ihowa.
13 Pẹ̀lú ìfi ọwọ́ ṣowọ́pọ̀ ogun àwọn Ammoni àti àwọn ọmọ-ogun Amaleki ní Egloni gbógun ti àwọn ọmọ Israẹli, wọ́n sì gba ìlú Ọ̀pẹ tí i se Jeriko.
Na ka huihuia e ia ki a ia nga tamariki a Amona ratou ko Amareke, a haere ana, patua ana e ia a Iharaira, a tangohia ana e ia te pa nikau.
14 Àwọn ọmọ Israẹli sì sin Egloni ọba Moabu fún ọdún méjìdínlógún.
A kotahi tekau ma waru nga tau i mahi ai nga tamariki a Iharaira ki a Ekerona, kingi o Moapa.
15 Ṣùgbọ́n nígbà tí Israẹli tún ké pe Olúwa, Olúwa rán olùgbàlà kan sí wọn, Ehudu ẹni tí ń lo ọwọ́ òsì, ọmọ Gera ti ẹ̀yà Benjamini. Àwọn ọmọ Israẹli fi ẹ̀bùn rán sí Egloni ọba Moabu.
No te tangihanga ia a nga tama a Iharaira ki a Ihowa, ka whakaarahia ake e Ihowa he kaiwhakaora mo ratou, a Ehuru tama a Kera, he Pineamini, he tangata ringa maui; na ka hoatu e nga tama a Iharaira he takoha kia kawea e ia ki a Ekerona kingi o M oapa.
16 Ehudu sì rọ idà kan olójú méjì, ìgbọ̀nwọ́ kan ní gígùn; òun sì sán an ní abẹ́ aṣọ rẹ̀ ní itan rẹ̀ ọ̀tún.
Otiia kua oti i a Ehuru tetahi hoari te hanga mana; e rua ona mata, kotahi whatianga te roa; na ka whitikiria e ia i roto i ona kakahu ki tona huha matau.
17 Ó sì mú ọrẹ náà wá fún Egloni ọba Moabu, Egloni ẹni tí ó sanra púpọ̀.
Na ko tana tukunga i te takoha ki a Ekerona kingi o Moapa; na he tangata tetere rawa a Ekerona.
18 Lẹ́yìn tí Ehudu ti fi ẹ̀bùn náà fún ọba tan, ó rán àwọn tí ó kó ẹrú náà wá lọ sí ọ̀nà wọn.
A ka mutu ta tera tuku i te takoha ka tonoa atu e ia te hunga i mauria mai ai te takoha.
19 Ṣùgbọ́n nígbà tí òun fúnra rẹ̀ dé ibi ère fínfín tí ó wà létí Gilgali, ó padà sí Egloni, ó sì wí pé, “Ọba, mo ní ọ̀rọ̀ àṣírí láti bá ọ sọ.” Ọba sì wí pé, “Ẹ dákẹ́!” Gbogbo àwọn tí ń ṣọ sì jáde síta kúrò ní ọ̀dọ̀ rẹ̀.
Ko ia tonu ia i hoki whakamuri atu i nga whakapakoko i Kirikara, ka mea, He kupu huna taku ki a koe, e te kingi. Na ka mea tera, Whakarongoa! Na mawehe atu ana i a ia te hunga katoa e tu ana i tona taha.
20 Ehudu lọ sí ọ̀dọ̀ rẹ̀ níbi tí ó ti jókòó ní iyàrá ìtura rẹ̀, Ehudu sì wí fún un pé, “Mo ní ọ̀rọ̀ kan fún ọ láti ọ̀dọ̀ Ọlọ́run.” Bí ọba sì ti dìde ní orí ìtẹ́ rẹ̀,
Na ka haere atu a Ehuru ki a ia; a e noho ana ia ko ia anake i tona ruma raumati. Na ka mea a Ehuru, He kupu na te Atua taku ki a koe. Na ka whakatika ia i tona nohoanga.
21 Ehudu fi ọwọ́ òsì rẹ̀ yọ idà láti ibi itan ọ̀tún rẹ̀ ó sì fi gún ọba nínú ikùn rẹ̀.
Na ka torona e Ehuru tona ringa maui, ka mau ki te hoari i tona huha matau, werohia ana ki tona kopu.
22 Àti idà àti èèkù rẹ̀ sì wọlé ó sì yọ ní ẹ̀yìn rẹ̀. Ehudu kò yọ idà náà, ọ̀rá sì bo idà náà.
A ngoto tahi atu ana te kakau me te mata, a tutakina iho te mata e te ngako, kihai i unuhia mai te hoari i roto i tona kopu, a puta atu ana ki muri.
23 Ehudu ti àwọn ìlẹ̀kùn ní àtì-sínú òun sì bá yàrá òkè jáde, ó sì sálọ.
Na ka haere atu a Ehuru na te whakamahau, a tutakina atu ana e ia nga tatau o te ruma ki a ia, kiia iho hoki.
24 Lẹ́yìn tí ó ti lọ àwọn ìránṣẹ́ ọba dé, ṣùgbọ́n nígbà tí wọ́n rí ìlẹ̀kùn yàrá òkè ní títì, wọ́n rò pé, “Bóyá ó wà ní ilé ìyàgbẹ́ ní yàrá nínú ilé.”
A, i tona haerenga atu, ka haere mai nga pononga a tera, na, i to ratou kitenga kua kiia nga tatau o te ruma, ka mea ratou, He pono kei te uhi ia i ona waewae i te ruma raumati.
25 Nígbà tí wọ́n dúró dé ibi pé ó jẹ́ ìyanu fún wọn, wọ́n mú kọ́kọ́rọ́, wọ́n sì ṣí ìlẹ̀kùn. Níbẹ̀ ni wọ́n ti rí Olúwa wọn tí ó ti ṣubú, ó sì ti kú.
Tatari noa ratou a ka whakama: na, kihai ia i whakapuare i nga tatau o te ruma; katahi ratou ka mau ki te ki, a whakapuaretia ana. Na, ko to ratou ariki kua hinga ki te whenua, kua mate.
26 Nígbà tí wọ́n dúró tí wọn sì ń retí, Ehudu ti sálọ. Ó ti gba ibi tí wọ́n ti ń gbẹ́ òkúta lére, ó sì sálọ sí Seira.
Ko Ehuru ia i mawhiti i a ratou e tatari roa ana, a kua tae ki tua i nga whakapakoko, kua mawhiti ki Heirata.
27 Nígbà tí ó dé ibẹ̀, ó fọn ìpè ní orí òkè Efraimu, àwọn ọmọ Israẹli sì ba sọ̀kalẹ̀ lọ láti òkè náà wá, òun sì wà níwájú wọn.
A, no tona taenga, ka whakatangihia e ia te tetere ki te whenua maunga o Eparaima, a heke ana nga tamariki a Iharaira i runga i te maunga hei hoa mona, ko ia hoki i mua i a ratou.
28 Ó sì wí fún wọn pé, “Ẹ máa tẹ̀lé mi, nítorí Olúwa ti fi Moabu ọ̀tá yín lé yín lọ́wọ́.” Wọ́n sì tẹ̀lé e, wọ́n sì gba ìwọdò Jordani tí ó lọ sí ilẹ̀ Moabu, wọn ò jẹ́ kí ẹnikẹ́ni kọjá.
Na ka mea ia ki a ratou, Haere mai i muri i ahau, kua homai hoki e Ihowa nga Moapi, o koutou hoariri ki o koutou ringa. Na heke ana ratou i muri i a ia, a ka riro mai i a ratou nga whitinga atu o Horano i nga Moapi; kihai hoki i tukua tetahi tan gata kia whiti atu.
29 Ní báyìí, wọ́n ti pa tó ẹgbẹ̀rún mẹ́wàá ọkùnrin ará Moabu tí wọ́n jẹ́ alágbára àti onígboyà ènìyàn, kò sí ènìyàn tí ó sálà.
Na patua iho e ratou nga Moapi i taua wa, me te mea tekau mano nga tangata, te hunga pakari anake, nga marohirohi katoa; kihai hoki tetahi i mawhiti.
30 Ní ọjọ́ náà ni Israẹli ṣẹ́gun àwọn ará Moabu, ilẹ̀ náà sì wà ní àlàáfíà fún ọgọ́rin ọdún.
Na ka hinga a Moapa i taua ra i te ringa o Iharaira. A e waru tekau nga tau i okioki ai te whenua i te pakanga.
31 Lẹ́yìn Ehudu, ni Ṣamgari ọmọ Anati ẹni tí ó pa ẹgbẹ̀ta Filistini pẹ̀lú ọ̀pá tí a fi ń da akọ màlúù, òun pẹ̀lú sì gba Israẹli kúrò nínú ìpọ́njú.
A i muri i a ia ko Hamakara tama a Anata, a patua iho e ia nga Pirihitini, e ono rau tangata, ki te wero kau: na ka ora ano a Iharaira i a ia.

< Judges 3 >