< Judges 20 >

1 Gbogbo àwọn ọmọ Israẹli láti Dani dé Beerṣeba, àti láti ilẹ̀ Gileadi jáde bí ẹnìkan ṣoṣo wọ́n sì péjọ síwájú Olúwa ni Mispa.
Na rĩrĩ, andũ a Isiraeli othe kuuma Dani nginya Birishiba, na kuuma bũrũri wothe wa Gileadi magĩũka o taarĩ mũndũ ũmwe, makĩũngana mbere ya Jehova kũu Mizipa.
2 Àwọn olórí gbogbo àwọn ènìyàn láti gbogbo ẹ̀yà Israẹli dúró ní ipò wọn ní àpéjọ àwọn ènìyàn Ọlọ́run, ogún ọ̀kẹ́ ọkùnrin ológun ti àwọn àti idà wọn.
Atongoria a andũ othe a mĩhĩrĩga ya Isiraeli makĩrũgama handũ hao kũu kĩũngano-inĩ kĩa andũ a Ngai, marĩ thigari ngiri magana mana meeohete hiũ cia njora.
3 (Àwọn ẹ̀yà Benjamini gbọ́ wí pé àwọn ọmọ Israẹli yòókù ti gòkè lọ sí Mispa.) Nígbà náà ni àwọn ọmọ Israẹli wí pé, “Ẹ sọ fún wa báwo ni iṣẹ́ búburú ṣe ṣẹlẹ̀.”
(Nao andũ Benjamini makĩigua atĩ andũ a Isiraeli nĩmambatĩte nginya Mizipa.) Hĩndĩ ĩyo andũ a Isiraeli makiuga atĩrĩ, “Ta twĩre ũrĩa ũndũ ũcio mũũru wekĩkire.”
4 Ará Lefi náà, ọkọ obìnrin tí wọ́n pa fèsì pé, “Èmi àti àlè mi wá sí Gibeah ti àwọn ará Benjamini láti sùn di ilẹ̀ mọ́ níbẹ̀.
Nĩ ũndũ ũcio Mũlawii ũcio mũthuuri wa mũtumia ũrĩa woragĩtwo akiuga atĩrĩ, “Niĩ na thuriya yakwa tuokire Gibea ya andũ a Benjamini tũraarĩrĩre kuo.
5 Ṣùgbọ́n ní òru àwọn ọkùnrin Gibeah lépa mi wọ́n sì yí ilé náà po pẹ̀lú èrò láti pa mí. Wọ́n fi ipá bá àlè mi lòpọ̀, òun sì kú.
Ũtukũ ũcio andũ a Gibea nĩmaanũmĩrĩire, na magĩthiũrũrũkĩria nyũmba, mehaarĩirie kũnjũraga. Makĩnyiita thuriya yakwa na hinya, nginya ĩgĩkua.
6 Mo mú àlè mi náà, mo sì gé e sí ekìrí ekìrí, mo sì fi ekìrí kọ̀ọ̀kan ránṣẹ́ sí agbègbè ìní Israẹli kọ̀ọ̀kan, nítorí pé wọ́n ti ṣe ohun tí ó jẹ́ èèwọ̀ àti ohun ìtìjú yìí ní ilẹ̀ Israẹli.
Ngĩoya thuriya yakwa, ngĩmĩtinaangia icunjĩ, na ngĩtũma o gĩcunjĩ o rũgongo rwa igai rĩa Isiraeli, nĩ ũndũ nĩmekĩte ũndũ wa thoni na wa gĩconoko thĩinĩ wa Isiraeli.
7 Nísinsin yìí, gbogbo ẹ̀yin ọmọ Israẹli, ẹ sọ ìmọ̀ràn yín, kí ẹ sì ṣe ìdájọ́ yín.”
Atĩrĩrĩ, inyuĩ andũ a Isiraeli inyuothe, kĩariei, mũheane itua rĩanyu.”
8 Gbogbo àwọn ènìyàn náà sì dìde bí ẹnìkan pẹ̀lú gbólóhùn kan wí pé, “Kò sí ẹnikẹ́ni nínú wa tí yóò lọ sí àgọ́ rẹ̀. Rárá o, kò sí ẹyọ ẹnìkan tí yóò padà lọ sí ilé rẹ̀.
Andũ acio othe magĩũkĩra o taarĩ mũndũ ũmwe, makiuga atĩrĩ, “Gũtirĩ mũndũ o na ũmwe witũ ũkũinũka. Aca, gũtirĩ o na ũmwe witũ ũgũcooka gwake mũciĩ.
9 Ṣùgbọ́n nísinsin yìí, ohun tí àwa yóò ṣe sí Gibeah ní yìí. Àwa yóò lọ kọlù ú bí ìbò bá ṣe darí wa.
No rĩrĩ, ũndũ ũrĩa tũgwĩka Gibea nĩ ũyũ: Tũkwambata kuo tũmookĩrĩre o ta ũrĩa ũcuuki wa mĩtĩ ũgũtuonia.
10 A yóò mú ọkùnrin mẹ́wàá nínú ọgọ́rùn-ún nínú gbogbo ẹ̀yà Israẹli àti ọgọ́rùn-ún láti inú ẹgbẹ̀rún kan àti ẹgbẹ̀rún kan láti inú ẹgbẹ̀rún mẹ́wàá láti máa pèsè oúnjẹ fún àwọn ọmọ-ogun. Yóò sì ṣe nígbà tí àwọn jagunjagun bá dé Gibeah ti àwọn ará Benjamini, wọn yóò fún wọn ní ohun tí ó bá tọ́ sí wọn fún gbogbo ìwà búburú àti ìwà ìtìjú tí wọ́n ṣe yìí ní ilẹ̀ Israẹli.”
Tũkũruta andũ ikũmi thĩinĩ wa o andũ igana a mĩhĩrĩga yothe ya Isiraeli, na andũ igana thĩinĩ wa o andũ ngiri, na andũ ngiri thĩinĩ wa o andũ ngiri ikũmi, nĩguo magĩĩrĩre mbũtũ cia ita irio. Nĩgeetha rĩrĩa mbũtũ cia ita igaakinya Gibea ya Benjamini, ikaameka maũndũ maringaine na waganu wa andũ akuo ũrĩa meekĩte thĩinĩ wa Isiraeli.”
11 Báyìí ni gbogbo àwọn ọkùnrin Israẹli parapọ̀ ṣọ̀kan bí ọkùnrin kan ṣoṣo wọ́n sì dìde sí ìlú náà.
Tondũ ũcio andũ othe a Isiraeli makĩũngana na makĩnyiitana o ta maarĩ mũndũ ũmwe mahũũre itũũra rĩu inene.
12 Àwọn ẹ̀yà Israẹli rán àwọn ọkùnrin sí gbogbo ẹ̀yà Benjamini wí pé, “Kí ni ẹ̀rí sí ìwà búburú yìí tí ó ṣẹlẹ̀ ní àárín yín?
Mĩhĩrĩga ya Isiraeli ĩgĩtũma andũ mathiĩ kũrĩ mũhĩrĩga wothe wa Benjamini, makamoorie atĩrĩ, “Nĩ ngero ĩrĩkũ ĩno njũru ũũ ĩĩkĩtwo gatagatĩ-inĩ kanyu?
13 Nítorí náà ẹ mú àwọn ẹni ibi ti Gibeah yìí wá fún wa, kí àwa lé pa, kí a sì fọ ìṣe búburú yìí mọ́ kúrò ní Israẹli.” Ṣùgbọ́n àwọn ẹ̀yà Benjamini kò fetí sí ti àwọn arákùnrin wọn ọmọ Israẹli.
Na rĩrĩ, tũnengerei andũ acio aaganu a Gibea nĩgeetha tũmoorage tweherie ũũru ũcio thĩinĩ wa Isiraeli.” No andũ a Benjamini matiigana kũigua andũ acio angĩ a Isiraeli.
14 Àwọn ẹ̀yà Benjamini sì kó ara wọn jọ láti àwọn ìlú wọn sí Gibeah láti bá àwọn ọmọ Israẹli jà.
Moimire matũũra-inĩ mao, makĩũngana hamwe kũu Gibea nĩguo mahũũrane na andũ a Isiraeli.
15 Ní ẹsẹ̀kẹsẹ̀ àwọn ará Benjamini kó ẹgbàá mẹ́tàlá àwọn ọmọ-ogun tí ń lọ dájọ́ láti àwọn ìlú wọn, yàtọ̀ sí àwọn ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀rin àṣàyàn ọkùnrin nínú àwọn tí ń gbé Gibeah.
O ro rĩmwe andũ a Benjamini magĩcookanĩrĩria andũ arĩa marũaga na hiũ cia njora 20,060 kuuma matũũra-inĩ mao, mongereirwo harĩ andũ magana mũgwanja arĩa maathuurĩtwo kuuma kũrĩ andũ arĩa maatũũraga kũu Gibea.
16 Ní àárín àwọn ọmọ-ogun wọ̀nyí ni ó ti ní àwọn ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀rin àṣàyàn ọkùnrin tí wọ́n ń lo ọwọ́ òsì, tí ọ̀kọ̀ọ̀kan wọn dára dé bi pé wọ́n lè fi kànnàkànnà ba fọ́nrán òwú ní àìtàsé (wọ́n jẹ́ atamọ́tàsé).
Gatagatĩ-inĩ ga thigari icio ciothe nĩ kwarĩ na andũ magana mũgwanja maathuurĩtwo a kĩmotho, na o ũmwe wao nĩahotaga gũikia ihiga na kĩgũtha ũndũ angĩringa rũcuĩrĩ na ndahĩtie.
17 Àwọn ọkùnrin Israẹli, yàtọ̀ sí àwọn ará Benjamini, ka ogún ọ̀kẹ́ àwọn tí ń fi idà jagun, gbogbo wọn jẹ́ akọni ní ogun jíjà.
Tiga andũ a Benjamini-rĩ, Isiraeli nĩmacookanĩrĩirie thigari 400 arĩa marũaga na hiũ cia njora, na othe maarĩ andũ a ita.
18 Àwọn ọmọ Israẹli lọ sí Beteli, wọ́n sì béèrè lọ́wọ́ Ọlọ́run. Wọ́n wí pé, “Ta ni nínú wa tí yóò kọ́ kojú àwọn ará Benjamini láti bá wọn jà?” Olúwa dáhùn pé, “Juda ni yóò kọ́ lọ.”
Andũ a Isiraeli makĩambata nginya Betheli na magĩtuĩria ũhoro harĩ Ngai makĩũria atĩrĩ, “Nũũ thĩinĩ witũ ũkwambĩrĩria kũhũũrana na andũ aya a Benjamini?” Nake Jehova agĩcookia atĩrĩ, “Juda nĩwe ũkwambĩrĩria.”
19 Àwọn ọmọ Israẹli dìde ní òwúrọ̀ ọjọ́ kejì, wọ́n sì dó ti Gibeah (wọ́n tẹ̀gùn sí ẹ̀bá Gibeah).
Rũciinĩ rũrũ rũngĩ andũ a Isiraeli magĩũkĩra na makĩamba hema ciao gũkuhĩ na Gibea.
20 Àwọn ọkùnrin Israẹli jáde lọ láti bá àwọn ará Benjamini jà wọ́n sì dúró ní ipò ogun sí wọn ní Gibeah.
Andũ a Isiraeli makiumagara makahũũrane na andũ a Benjamini, na makĩiga andũ o handũ hao mbaara-inĩ marũe nao kũu Gibea.
21 Àwọn ọmọ Benjamini sì jáde láti Gibeah wá wọ́n sì pa àwọn ọmọ ẹgbẹ̀rún méjìlélógún ọkùnrin nínú àwọn ọmọ Israẹli ní ojú ogun ní ọjọ́ náà.
Nao andũ a Benjamini makiuma kũu Gibea na makĩũraga andũ a Isiraeli 22,000 kũu mbaara-inĩ mũthenya ũcio.
22 Ṣùgbọ́n àwọn ọkùnrin Israẹli mú ara wọn lọ́kàn le, wọ́n sì tún dúró sí ipò wọn ní ibi tí wọ́n dúró sí ní ọjọ́ àkọ́kọ́.
No andũ a Isiraeli makĩũmanĩrĩria mũndũ na ũrĩa ũngĩ na makĩrũgama handũ hao rĩngĩ o harĩa meigĩte mũthenya wa mbere.
23 Àwọn ọmọ Israẹli sì lọ wọ́n sọkún ní iwájú Olúwa títí oòrùn fi wọ̀, wọ́n sì béèrè lọ́wọ́ Olúwa. Wọ́n ni, “Ṣé kí àwa tún gòkè lọ kí a sì bá àwọn ará Benjamini arákùnrin wa jà?” Olúwa dáhùn pé, “Lọ bá wọn jà.”
Nao andũ a Isiraeli makĩambata makĩrĩrĩra mbere ya Jehova nginya hwaĩ-inĩ, nao magĩtuĩria ũhoro harĩ Jehova atĩrĩ, “Hihi twambate rĩngĩ tũkahũũrane na andũ a Benjamini, aya ariũ a ithe witũ?” Nake Jehova akĩmacookeria atĩrĩ, “Ambatai mũkahũũrane nao.”
24 Àwọn ọmọ Israẹli sì tún súnmọ́ tòsí àwọn ará Benjamini ní ọjọ́ kejì.
Hĩndĩ ĩyo andũ a Isiraeli magĩkuhĩrĩria andũ a Benjamini mũthenya wa keerĩ.
25 Ní ọjọ́ yìí nígbà tí ará Benjamini jáde sí wọn láti Gibeah, láti dojúkọ wọn, wọ́n pa ẹgbàá mẹ́sàn ọkùnrin Israẹli, gbogbo wọn jẹ́ jagunjagun tí ń lo idà.
Mũthenya ũcio, rĩrĩa Abenjamini mookire moimĩte Gibea mahũũrane nao-rĩ, makĩũraga andũ a Isiraeli angĩ 18,000, othe meeohete hiũ cia njora.
26 Nígbà náà ni gbogbo àwọn ọmọ Israẹli àní gbogbo àwọn ènìyàn, gòkè lọ sí Beteli, níbẹ̀ ni wọ́n jókòó tí wọ́n sì ń sọkún níwájú Olúwa. Wọ́n gbààwẹ̀ ní ọjọ́ náà títí di àṣálẹ́, wọ́n sì rú ọrẹ ẹbọ sísun àti ọrẹ àlàáfíà sí Olúwa.
Ningĩ andũ a Isiraeli, marĩ othe, makĩambata nginya Betheli, na kũu magĩikara kuo makĩrĩra marĩ mbere ya Jehova. Makĩĩhinga kũrĩa irio mũthenya ũcio o nginya hwaĩ-inĩ, na makĩruta maruta ma njino na maruta ma ũiguano kũrĩ Jehova.
27 Àwọn ọmọ Israẹli sì béèrè lọ́wọ́ Olúwa. (Ní ọjọ́ wọ̀n-ọn-nì àpótí ẹ̀rí Ọlọ́run wà níbẹ̀,
Nao andũ a Isiraeli, magĩtuĩria ũhoro harĩ Jehova. (Matukũ-inĩ macio ithandũkũ rĩa kĩrĩkanĩro kĩa Ngai rĩarĩ kũu,
28 Finehasi ọmọ Eleasari ọmọ Aaroni, ní ń ṣe iṣẹ́ ìránṣẹ́ ní iwájú rẹ̀.) wọ́n béèrè pé, “Ṣe àwa tún le lọ sí ogun pẹ̀lú Benjamini arákùnrin wa tàbí kí a má lọ?” Olúwa dáhùn pé, “Ẹ lọ nítorí ní ọ̀la ni èmi yóò fi wọ́n lé e yín lọ́wọ́.”
nake Finehasi mũrũ wa Eleazaru, mũrũ wa Harũni, nĩwe watungataga mbere yarĩo.) Nao makĩũria atĩrĩ, “Nĩtũkwambata rĩngĩ tũkahũũrane na Abenjamini ariũ a ithe witũ, kana tũtige?” Jehova akĩmacookeria atĩrĩ, “Thiĩi, nĩ ũndũ rũciũ nĩngamaneana moko-inĩ manyu.”
29 Àwọn ọmọ Israẹli sì yàn àwọn ènìyàn tí ó sá pamọ́ yí Gibeah ká.
Nao andũ a Isiraeli makĩmoheria mathiũrũrũkĩirie Gibea.
30 Wọ́n jáde tọ àwọn ọmọ Benjamini lọ ní ọjọ́ kẹta wọ́n sì dúró ní ipò wọn, wọ́n sì dìde ogun sí Gibeah bí wọ́n ti ṣe tẹ́lẹ̀ rí.
Nao makĩambata makahũũrane na andũ a Benjamini mũthenya wa gatatũ na makĩrũgama handũ hao nĩguo mahũũrane na Gibea o ta ũrĩa meekĩte hau mbere.
31 Àwọn ọmọ Benjamini sì jáde láti pàdé wọn, àwọn ọmọ Israẹli sì tàn wọ́n jáde kúrò ní ìlú náà. Wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí ní ṣẹ́gun àwọn ọmọ Israẹli bí i ti àtijọ́ dé bi pé wọ́n pa bí ọgbọ̀n ọkùnrin ní pápá àti ní àwọn òpópó náà—àwọn ọ̀nà tí ó lọ sí Beteli àti èkejì sí Gibeah.
Nao Abenjamini makiumĩra mamatũnge na makĩguucĩrĩrio kũraihu na itũũra rĩu inene. Makĩambĩrĩria kũhũũra andũ a Isiraeli o ta mbere ĩyo, na andũ ta mĩrongo ĩtatũ makĩrũndĩrwo werũ-inĩ na njĩra-inĩ ĩrĩa ĩthiiaga Betheli na ĩrĩa ĩngĩ Gibea.
32 Nígbà tí àwọn Benjamini ń wí pé, “Àwa ti ń ṣẹ́gun wọn bí i ti ìṣáájú,” àwọn ọmọ Israẹli ń wí pé, “Ẹ jẹ́ kí a sá kí a lè fà wọ́n kúrò ní ìlú sí ojú òpópó náà.”
Rĩrĩa andũ a Benjamini meeranaga atĩrĩ, “Nĩtũramahoota o ta mbere,” noguo nao andũ a Isiraeli meeranaga atĩrĩ, “Rekei tũcooke na thuutha tũmaguucĩrĩrie moime itũũra-inĩ inene moke njĩra-inĩ.”
33 Gbogbo àwọn ọkùnrin Israẹli dìde kúrò ní ipò wọn, wọ́n sì tẹ̀dó ogun ní Baali-Tamari, àwọn ọmọ-ogun Israẹli tí wọ́n sá pamọ́ sínú igbó jáde kúrò níbi tí wọ́n wà ní ìwọ̀-oòrùn Gibeah.
Andũ othe a Isiraeli makĩehera harĩa maarĩ na makĩrũgama handũ hao kũu Baali-Tamaru, nao andũ a Isiraeli arĩa meehithĩire andũ a Benjamini makiumĩra kũrĩa meehithĩte mwena wa ithũĩro wa Gibea.
34 Nígbà náà ni ẹgbẹ̀rún mẹ́wàá àwọn àṣàyàn ológun àwọn ọmọ Israẹli gbógun ti Gibeah láti iwájú ogun náà le gidigidi dé bí i pé àwọn ẹ̀yà Benjamini kò funra pé ìparun wà nítòsí.
Hĩndĩ ĩyo andũ ngiri ikũmi arĩa maarĩ njamba iria thuure cia Isiraeli magĩtharĩkĩra Gibea kuuma na mbere. Nayo mbaara yarĩ nene ũũ atĩ andũ a Benjamini matiigana gũkũũrana ũrĩa mwanangĩko wamakuhĩrĩirie.
35 Olúwa ṣẹ́gun Benjamini níwájú àwọn ọmọ Israẹli, ní ọjọ́ náà àwọn ọmọ Israẹli pa ẹgbàá méjìlá ó lé lẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀fà ọkùnrin Benjamini, gbogbo wọn fi idà dìhámọ́ra ogun.
Nake Jehova akĩhootera andũ a Benjamini mbere ya Isiraeli, na mũthenya ũcio andũ a Isiraeli makĩũraga andũ a Benjamini 25,100, arĩa meeohete hiũ cia njora.
36 Àwọn ẹ̀yà Benjamini sì rí pé wọ́n ti ṣẹ́gun àwọn. Àwọn ọkùnrin Israẹli fàsẹ́yìn níwájú àwọn ẹ̀yà Benjamini nítorí pé wọ́n fọkàn tán àwọn tí ó wà ní ibùba ní ẹ̀bá Gibeah.
Tondũ ũcio andũ a Benjamini makĩona atĩ nĩmaatooretio. Na rĩrĩ, andũ a Isiraeli nĩmoorĩire andũ a Benjamini, nĩ ũndũ nĩmehokete andũ arĩa maigĩte a kuoheria andũ a Benjamini gũkuhĩ na Gibea.
37 Àwọn ọkùnrin tí wọ́n lúgọ yára jáde wọ́n sì tètè wọ Gibeah, wọ́n fọ́nká wọ́n sì fi idà pa gbogbo àwọn tí ó wà nínú ìlú náà.
Nao andũ acio moohetie andũ makĩguthũka o rĩmwe magĩtoonya Gibea, makĩaragana kuo na makĩhũũra itũũra rĩu inene rĩothe na rũhiũ rwa njora.
38 Àwọn ọkùnrin Israẹli àti àwọn tí o ba ní ibùba sínú igbó ti fún ara wọn ní àmì pé, kí àwọn tí ó ba ní ibùba fi èéfín ṣe ìkùùkuu ńlá láti inú ìlú náà,
Nao andũ a Isiraeli nĩ mabangĩte na andũ acio moohetie andũ atĩ matoogie ndogo nene ĩthiĩ na igũrũ yumĩte itũũra rĩu inene,
39 nígbà náà ni àwọn ọkùnrin Israẹli yípadà, wọ́n sá gun. Àwọn ọmọ Benjamini sì ti bẹ̀rẹ̀ sí ṣẹ́gun àti ní pípa àwọn ọkùnrin Israẹli tí ó to ọgbọ̀n, wọ́n sì wí pé, “Àwa ń ṣẹ́gun wọn bí ìgbà ìjà àkọ́kọ́.”
nĩgeetha hĩndĩ ĩyo andũ a Isiraeli magarũrũke na macooke mbaara-inĩ. Andũ a Benjamini maakorirwo maambĩrĩria kũũraga andũ a Isiraeli (ta andũ mĩrongo ĩtatũ), nao makiuga atĩrĩ, “Ithuĩ nĩtũramatooria o ta ũrĩa twamekire mbaara-inĩ ya mbere.”
40 Ṣùgbọ́n nígbà tí ìkùùkuu èéfín bẹ̀rẹ̀ sí ní rú sókè láti inú ìlú náà wá, àwọn ẹ̀yà Benjamini yípadà wọ́n sì rí èéfín gbogbo ìlú náà ń gòkè sí ojú ọ̀run.
No rĩrĩa ndogo yambĩrĩirie kwambata na igũrũ yumĩte itũũra-inĩ rĩu inene-rĩ, andũ a Benjamini makĩĩhũgũra makĩona ndogo itũũra-inĩ rĩu inene rĩothe yambatĩte na igũrũ matu-inĩ.
41 Àwọn ọkùnrin Israẹli sì yípadà sí wọn, ẹ̀rù gidigidi sì ba àwọn ará Benjamini nítorí pé wọ́n mọ̀ pé àwọn wà nínú ewu.
Hĩndĩ ĩyo andũ a Isiraeli makĩmagarũrũkĩra nao andũ a Benjamini makĩnyiitwo nĩ guoya mũnene, nĩ ũndũ nĩmakũũranire atĩ mwanangĩko nĩwarĩĩkĩtie kũmakora.
42 Wọ́n sì sá níwájú àwọn ọmọ Israẹli sí apá àṣálẹ́, ṣùgbọ́n wọn kò le sálà kúrò lọ́wọ́ ogun náà. Àwọn ọkùnrin Israẹli tí ó jáde láti inú àwọn ìlú wọn wá pa wọ́n run níbẹ̀.
Nĩ ũndũ ũcio makĩũrĩra andũ a Isiraeli marorete na werũ-inĩ, no matingĩahotire kũũrĩra mbaara. Nao andũ a Isiraeli arĩa mookire moimĩte matũũra-inĩ makĩmooragĩra kuo.
43 Wọ́n yí àwọn ẹ̀yà Benjamini ká, wọ́n lépa wọn, wọ́n sì pa wọ́n run pẹ̀lú ìrọ̀rùn ní ibi ìsinmi wọn ní agbègbè ìlà-oòrùn Gibeah.
Magĩthiũrũrũkĩria andũ a Benjamini acio, makĩmatengʼeria, na makĩmakinyĩra na njĩra hũthũ kũu gũkuhĩ na Gibea mwena wa irathĩro.
44 Ẹgbàá mẹ́sàn àwọn ẹ̀yà Benjamini ṣubú, gbogbo wọn jẹ́ akọni jagunjagun.
Andũ a Benjamini ngiri ikũmi na inyanya magĩkua, nao othe maarĩ arũi njamba.
45 Bí wọ́n ṣe síjú padà tí wọ́n sì ń sálọ sí apá ijù lọ sí ọ̀nà àpáta Rimoni ni àwọn ọmọ Israẹli pa ẹgbẹ̀rún márùn-ún ọkùnrin ní àwọn òpópónà. Wọ́n lépa àwọn ẹ̀yà Benjamini títí dé Gidomu, wọ́n sì tún bi ẹgbẹ̀rún méjì ọkùnrin ṣubú.
Na rĩrĩa maagarũrũkire marorete na werũ-inĩ nginya ihiga-inĩ rĩa Rimoni, andũ a Isiraeli makĩũragĩra andũ 5,000 njĩra-inĩ icio. Nao magĩkĩrĩrĩria kũrũmĩrĩra andũ a Benjamini o nginya Gidomu na makĩũraga 2,000.
46 Ní ọjọ́ náà ẹgbàá méjìlá ó lé ẹgbẹ̀rún jagunjagun Benjamini tí ń fi idà jagun ní ó ṣubú, gbogbo wọn jẹ́ akọni ológun.
Mũthenya ũcio andũ a Benjamini 25,000 arĩa maarũaga na hiũ cia njora makĩũragwo, na othe maarĩ arũi njamba.
47 Ṣùgbọ́n ẹgbẹ̀ta ọkùnrin yípadà wọ́n sì sá nínú ààlà lọ sí àpáta Rimoni, níbi tí wọ́n wà fún oṣù mẹ́rin.
No andũ magana matandatũ makĩgarũrũka na makĩũrĩra werũ-inĩ o nginya ihiga-inĩ rĩa Rimoni, na magĩikara kuo mĩeri ĩna.
48 Àwọn ọkùnrin Israẹli sì padà sí àwọn ìlú Benjamini wọn sì fi idà pa gbogbo ohun tí ó wà nínú àwọn ìlú wọn àti àwọn ẹran àti gbogbo ohun tí wọn ba níbẹ̀. Gbogbo ìlú tí wọ́n bá ní ojú ọ̀nà ni wọ́n fi iná sun.
Nao andũ a Isiraeli magĩcooka nginya bũrũri wa andũ a Benjamini na makĩhũũra matũũra mothe na rũhiũ rwa njora, o gwata nyamũ na kĩndũ o gĩothe kĩngĩ kĩrĩa maakorereire. Na matũũra mothe marĩa maakorire makĩmacina na mwaki.

< Judges 20 >