< Judges 2 >

1 Ní ọjọ́ kan angẹli Olúwa dìde kúrò láti Gilgali lọ sí Bokimu ó sì wí pé, “Èmi mú un yín gòkè láti ilẹ̀ Ejibiti wá, èmi sì síwájú yín wá sí ilẹ̀ tí mo ti búra láti fi fún àwọn baba ńlá yín. Èmi sì wí pé, ‘Èmi kì yóò yẹ májẹ̀mú mi pẹ̀lú yín,
Na ka haere ake te anahera a Ihowa i Kirikara ki Pokimi, a ka mea, Naku koutou i haere mai ai i Ihipa, naku hoki koutou i kawe mai ki te whenua i oati ai ahau ki o koutou matua; i mea ano ahau, E kore e taka taku kawenata ki a koutou.
2 ẹ̀yin kò gbọdọ̀ bá àwọn ènìyàn ilẹ̀ yí dá májẹ̀mú àlàáfíà, ṣùgbọ́n ẹ̀yin yóò wó pẹpẹ ibi ìsin òrìṣà wọn lulẹ̀.’ Síbẹ̀ ẹ̀yin ṣe àìgbọ́ràn sí mi. Èéṣe tí ẹ̀yin fi ṣe èyí?
Kaua ano koutou e whakarite kawenata ki nga tangata o tenei whenua; me pakaru e koutou a ratou aata. Heoi kihai nei koutou i rongo ki toku reo. He aha tenei mahi a koutou?
3 Ní báyìí, èmi wí fún un yín pé, èmi kì yóò lé àwọn ènìyàn jáde kúrò níwájú yín; ṣùgbọ́n wọn yóò jẹ́ ẹ̀gún ní ìhà yín, àwọn òrìṣà wọn yóò sì jẹ́ ìdánwò fún un yín.”
Koia hoki ahau ka mea nei, E kore ahau e pei atu i a ratou i to koutou aroaro; a ka waiho ratou ano he tataramoa ki o koutou kaokao; ko o ratou atua hoki hei rore mo koutou.
4 Bí angẹli Olúwa sì ti sọ gbogbo ọ̀rọ̀ wọ̀nyí fún àwọn ará Israẹli tan, àwọn ènìyàn náà sì gbé ohùn wọn sókè wọ́n sì sọkún kíkorò,
A, no te korerotanga a te anahera a Ihowa i enei kupu ki nga tamariki katoa a Iharaira, ka ara te reo o te iwi, ka tangi.
5 wọ́n sì pe orúkọ ibẹ̀ ní Bokimu (ibi tí àwọn ènìyàn ti sọkún). Wọ́n sì rú ẹbọ sí Olúwa níbẹ̀.
Na huaina iho e ratou te ingoa o taua wahi ko Pokimi: i patu whakahere ano hoki ratou ma Ihowa ki reira.
6 Lẹ́yìn tí Joṣua ti tú àwọn ènìyàn Israẹli ká, àwọn ẹ̀yà Israẹli kọ̀ọ̀kan lọ sí ilẹ̀ tí a fi fún wọn láti lọ gbà á ní ìní wọn.
Na, i ta Hohua tukunga i te iwi kia haere, ka haere nga tamariki a Iharaira ki tona wahi, ki tona wahi, ki te tango i te whenua.
7 Àwọn ènìyàn náà sin Olúwa ní gbogbo ìgbà ayé Joṣua àti ní gbogbo ọjọ́ àwọn àgbàgbà tí ó wà lẹ́yìn ikú rẹ̀ tí wọ́n sì rí gbogbo iṣẹ́ ńlá tí Olúwa ṣe fún Israẹli.
A i mahi te iwi ki a Ihowa i nga ra katoa o Hohua, i nga ra katoa ano o nga kaumatua i roa ake nei o ratou ra i o Hohua, i kite nei i nga mahi nunui katoa a Ihowa i meinga e ia mo Iharaira.
8 Joṣua ọmọ Nuni, ìránṣẹ́ Olúwa, kú ní ẹni àádọ́fà ọdún.
Na ka mate a Hohua tama a Nunu, te pononga a Ihowa, kotahi rau kotahi tekau ona tau.
9 Wọ́n sì sìnkú rẹ̀ sí ààlà ilẹ̀ ìní rẹ̀ ní Timnati-Hereki ní ilẹ̀ òkè Efraimu ní àríwá òkè Gaaṣi.
A tanumia iho ia e ratou ki te rohe o tona wahi, ki Timinataherehe, ki te whenua pukepuke o Eparaima, ki te taha ki te raki o Maunga Kaaha.
10 Ní ìgbẹ̀yìn, gbogbo ìran náà sì kú; àwọn ìran tí ó tẹ̀lé wọn kò sì sin Olúwa nítorí wọn kò mọ Olúwa, bẹ́ẹ̀ ni wọn kò mọ ohun tí Olúwa ṣe fún Israẹli.
Na ka kohia ano hoki taua whakatupuranga katoa ki o ratou matua: a ka ara ake tetahi whakatupuranga ke i muri i a ratou, kihai nei i mohio ki a Ihowa, ki nga mahi ano hoki i mahia e ia mo Iharaira.
11 Àwọn ọmọ Israẹli sì ṣe ohun tí ó burú níwájú Olúwa, wọ́n sì ń sin òrìṣà Baali.
Na ka mahi nga tamariki a Iharaira i te kino i te tirohanga a Ihowa, ka mahi hoki ki nga Paara.
12 Wọ́n kọ Olúwa Ọlọ́run àwọn baba wọn sílẹ̀, ẹni tí ó mú wọn jáde kúrò ní ilẹ̀ Ejibiti, wọ́n ń tọ àwọn òrìṣà lẹ́yìn, wọ́n sì ń sin àwọn oríṣìíríṣìí òrìṣà àwọn ará ilẹ̀ ibi tí wọ́n ń gbé, wọ́n sì mú Olúwa bínú,
A whakarerea ake e ratou a Ihowa, te Atua o o ratou matua i whakaputa mai nei i a ratou i te whenua o Ihipa, a haere ana ki te whai i nga atua ke, i nga atua o nga iwi i tetahi taha, i tetahi taha o ratou, a koropiko ana ki a ratou, na ka mea ra tou i a Ihowa kia riri.
13 nítorí tí wọ́n kọ̀ Olúwa sílẹ̀ àti nítorí pé wọ́n ń sin Baali àti Aṣtoreti.
Heoi whakarere ana ratou i a Ihowa, a mahi ana ki a Paara, ki te Ahataroto hoki.
14 Nínú ìbínú rẹ̀ sí àwọn ọmọ Israẹli Olúwa fi wọ́n lé àwọn akónisìn lọ́wọ́ tí ó kó wọn ní ẹrú, tí ó sì bà wọ́n jẹ́. Ó sì tà wọ́n fún àwọn ọ̀tá wọn tí ó yí wọn ká àwọn ẹni tí wọn kò le dúró dè láti kọ ojú ìjà sí.
Na ka mura te riri o Ihowa ki a Iharaira, a tukua ana ratou e ia ki nga ringa o nga kaipahua hei pahua i a ratou, a hokona ana ratou e ia ki te ringa o o ratou hoariri i tetahi taha, i tetahi taha; kihai hoki i taea e ratou i muri iho te tu ake i te aroaro o o ratou hoariri.
15 Nígbàkígbà tí àwọn Israẹli bá jáde lọ sí ojú ogun láti jà, ọwọ́ Olúwa sì wúwo ní ara wọn, àwọn ọ̀tá a sì borí wọn, àní gẹ́gẹ́ bí ó ti búra fún wọn. Wọ́n sì wà nínú ìpọ́njú púpọ̀.
I o ratou haerenga katoa, i runga i a ratou te ringa o Ihowa mo te kino; i rite hoki ki ta Ihowa i korero ai, ki ta Ihowa hoki i oati ai ki a ratou; na te taea to ratou raru.
16 Olúwa sì gbé àwọn onídàájọ́ dìde tí ó gbà wọ́n sílẹ̀ lọ́wọ́ àwọn tí ń kó wọn lẹ́rú.
I whakaara ake ano a Ihowa i etahi kaiwhakarite hei whakaora i a ratou i te ringa o o ratou kaipahua.
17 Síbẹ̀síbẹ̀ wọn kò fi etí sí ti àwọn onídàájọ́ wọn, ṣùgbọ́n wọ́n ṣe àgbèrè, wọ́n ń sin òrìṣà. Wọn kò dàbí àwọn baba wọn, kíákíá ni wọ́n yípadà kúrò lọ́nà tí àwọn baba wọ́n ń tọ̀, ọ̀nà ìgbọ́ràn sí àwọn òfin Olúwa.
Heoi kihai ano ratou i whakarongo ki o ratou kaiwhakarite; na kei te puremu, kei te whai ki nga atua ke, kei te koropiko ki a ratou: hohoro tonu to ratou peka ke i te ara i haere ai o ratou matua, ara i te whakarongo ki nga whakahau a Ihowa; kih ai ratou i pera.
18 Nígbà kí ìgbà tí Olúwa bá gbé onídàájọ́ dìde fún wọn, Olúwa máa ń wà pẹ̀lú onídàájọ́ náà, a sì gbà wọ́n kúrò ní ọwọ́ àwọn ọ̀tá wọn ní ìwọ̀n ìgbà tí onídàájọ́ náà bá wà láààyè nítorí àánú Olúwa wà ní ara wọn, nígbà tí wọ́n bá ké ìrora lábẹ́ àwọn tí ń tẹrí wọn ba, tí sì ń fi ìyà jẹ wọ́n.
A i nga wa i whakaara ake ai a Ihowa i nga kaiwhakarite mo ratou, na i te kaiwhakarite a Ihowa, a whakaorangia ake ratou e ia i te ringa o o ratou hoariri i nga ra katoa o te kaiwhakarite: i puta ke hoki te whakaaro o Ihowa i a ratou e aue ana i o ratou kaitukino, i o ratou kaiwhakatoi.
19 Ṣùgbọ́n ní kété tí onídàájọ́ bá ti kú, àwọn ènìyàn náà a sì tún padà sí ọ̀nà ìbàjẹ́ àní ju ti àwọn baba wọn lọ, wọn a tẹ̀lé òrìṣà, wọ́n ń sìn wọ́n, wọn a sì foríbalẹ̀ fún wọn, wọ́n kọ̀ láti yàgò kúrò ní ọ̀nà ibi wọn àti agídí ọkàn wọn.
A, no te matenga o te kaiwhakarite, ka hoki ratou ki muri, nui atu to ratou takanga i to o ratou matua; i haere hoki ki te whai i nga atua ke, mahi ai ki a ratou, koropiko ai ki a ratou; kihai i mutu a ratou mahi, me ta ratou tikanga pakeke.
20 Ìbínú Olúwa yóò sì tún ru sí Israẹli a sì wí pé, “Nítorí tí orílẹ̀-èdè yìí ti yẹ májẹ̀mú tí mo fi lélẹ̀ fún àwọn baba ńlá wọn, tí wọn kò sì fetí sí mi,
Na ka mura te riri o Ihowa ki a Iharaira, a ka mea ia, Na, kua takahia e tenei iwi taku kawenata i whakahaua e ahau ki o ratou matua; kihai ano i rongo ki toku reo;
21 Èmi kì yóò lé ọ̀kankan nínú àwọn orílẹ̀-èdè tí Joṣua fi sílẹ̀ nígbà tí ó kú jáde.
Na, e kore ano ahau e pei atu i tetahi tangata i mua i a ratou o nga iwi i mahue iho i a Hohua i tona matenga.
22 Ṣùgbọ́n dípò bẹ́ẹ̀ èmi yóò lo àwọn orílẹ̀-èdè yìí láti fi dán Israẹli wò, láti mọ̀ bóyá wọ́n yóò pa ọ̀nà Olúwa mọ́ àti pé bóyá wọn ó rìn nínú rẹ̀ bí àwọn baba ńlá wọn ti rìn.”
Kia ai ratou hei whakamatautau maku i a Iharaira, e mau ranei ki te ara o Ihowa haere ai; e rite ranei te mau ki ta o ratou matua, kahore ranei.
23 Nítorí náà Olúwa fi àwọn orílẹ̀-èdè náà sílẹ̀ ní ilẹ̀ náà kò sì lé wọn jáde, tàbí kí ó jẹ́ kí àwọn Israẹli pa wọ́n run, bẹ́ẹ̀ kò sì fi wọ́n lé Joṣua lọ́wọ́.
Na ka waiho era iwi e Ihowa, kihai hoki i hohoro te peia atu; kihai ano hoki i tukua ki te ringa o Hohua.

< Judges 2 >