< Judges 19 >

1 Ní ọjọ́ wọ̀n-ọn-nì Israẹli kò ní ọba. Ọ̀kan nínú àwọn ọmọ Lefi tí ń gbé ibi tí ó sá pamọ́ nínú àwọn agbègbè òkè Efraimu, mú àlè kan láti Bẹtilẹhẹmu ní Juda.
Te vaeng tue ah khaw Israel ah he manghai tal pueng. Te dongah Ephraim tlang hlaep ah aka kuep Levi hlang loh Judah Bethlehem lamkah huta pakhat te yula la a loh.
2 Ṣùgbọ́n àlè rẹ̀ náà sì ṣe panṣágà sí i, òun fi sílẹ̀, ó sì padà lọ sí ilé baba rẹ̀ ní Bẹtilẹhẹmu ti Juda, ó sì wà ní ibẹ̀ ní ìwọ̀n oṣù mẹ́rin,
Tedae anih taengkah a yula tah a cukhalh dongah a va taeng lamloh a napa im Judah Bethlehem la cet tih hla li om.
3 ọkọ rẹ̀ lọ sí ibẹ̀ láti rọ̀ ọ́ pé kí ó padà sí ọ̀dọ̀ òun. Nígbà tí ó ń lọ ó mú ìránṣẹ́ àti kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ méjì lọ́wọ́, obìnrin náà mú un wọ inú ilé baba rẹ̀ lọ, nígbà tí baba obìnrin náà rí i ó fi tayọ̀tayọ̀ gbà á.
Te dongah a yuu te ha mael khaw ha mael laeh saeh tila a lungbuei te yam pah ham a va te thoo tih a yuu taengla cet. Te vaengah amah taengkah cadong pakhat neh laak rhoi te a khuen. A va te a napa im a paan puei tih huta kah a napa loh a hmuh hatah anih doe ham a kohoe.
4 Àna rẹ̀, baba ọmọbìnrin náà rọ̀ ọ́, ó sì borí rẹ̀ láti dá a dúró fún ìgbà díẹ̀, òun sì dúró fún ọjọ́ mẹ́ta, ó ń jẹ, ó ń mu, ó sì ń sùn níbẹ̀.
Tedae huta kah a napa, khosoih masae loh a parhaeng. Te dongah hnin thum a om puei hatah a caak a ok uh tih rhaeh uh.
5 Ní ọjọ́ kẹrin, wọ́n dìde ní òwúrọ̀ kùtùkùtù òun sì múra láti padà lọ, ṣùgbọ́n baba ọmọbìnrin náà wí fún àna rẹ̀ pé, “Fi ohun jíjẹ díẹ̀ gbé inú ró nígbà náà kí ìwọ máa lọ.”
Hnin li a om nen tah mincang ah thoo tih caeh hamla hlah uh bal. Tedae huta kah a napa loh a cava te, “Buh kamat nen khaw na lungbuei duel lamtah a hnuk la cet mai,” a ti nah.
6 Àwọn méjèèjì sì jùmọ̀ jókòó láti jọ jẹun àti láti jọ mu. Lẹ́yìn èyí ni baba ọmọbìnrin wí pé, “Jọ̀wọ́ dúró ní alẹ́ yìí kí o sì gbádùn ara rẹ.”
Te dongah ngol rhoi tih thikat la a caak a ok rhoi. Te vaengah tekah hlang te huta kah a napa loh, “Ueh mai lamtah na lungbuei voelphoeng la rhaeh rhoi mai dae,” a ti nah.
7 Nígbà tí ọkùnrin náà dìde láti máa lọ, baba ìyàwó rẹ̀ rọ̀ ọ́, torí náà ó sùn níbẹ̀ ní alẹ́ ọjọ́ náà.
Tekah hlang loh caeh hamla thoo bal coeng dae a masae loh a hloep dongah mael tih hnap rhaeh.
8 Ní òwúrọ̀ ọjọ́ karùn-ún nígbà tí ó dìde láti lọ, baba ọmọbìnrin wí pé, “Fi oúnjẹ gbé ara ró. Dúró de ọ̀sán!” Àwọn méjèèjì sì jùmọ̀ jọ jẹun.
A hnin nga mincang ah caeh hamla thoo bal. Te vaengah huta kah a napa loh, “Na thinko duel rhoi dae lamatah khovoei duela rhing rhoi mai,” a ti nah. Te dongah amih rhoi long te buh koep a caak rhoi bal.
9 Nígbà tí ọkùnrin náà, pẹ̀lú àlè àti ìránṣẹ́ rẹ̀, dìde láti máa lọ, àna rẹ̀, baba ọmọbìnrin náà ní, “Wò ó ilẹ̀ ti ń ṣú lọ, dúró níbí, ọjọ́ ti lọ. Dúró kí o sì gbádùn ara rẹ. Ìwọ lè jí ní àárọ̀ kùtùkùtù ọ̀la kí ìwọ sì máa lọ ilé.”
Te phoeiah caeh hamla a yula neh cadong te a thoh puei hatah hula kah a napa, a napa loh, “Kholaeh ham khohnin loh khum coeng ta, khohnin loh thok coeng tih pahoi rhaeh rhoi mai lamtah na thinko voelphoeng sak rhoi mai, na longpuei te thangvuen ah na thoh thil vetih na dap khaw na paan bitni,” a ti nah.
10 Ṣùgbọ́n nítorí pé òun kò fẹ́ dúró mọ́ níbẹ̀ ní òru náà ọkùnrin náà kúrò ó sì gba ọ̀nà Jebusi: ọ̀nà Jerusalẹmu pẹ̀lú àwọn kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ rẹ̀ méjèèjì tí ó fi dì í ní gàárì àti àlè rẹ̀.
Tedae rhaeh hamla hlang loh a huem pawt dongah thoo tih nong. Te vaengah amah taengah a khih laak rhoi neh a taengkah a yula te Jerusalem kah Jebus dan la a pawk puei.
11 Nígbà tí wọ́n súnmọ́ Jebusi tí ilẹ̀ ti fẹ́ ṣú tan, ìránṣẹ́ náà sọ fún ọ̀gá rẹ̀ pé, “Ẹ wá, ẹ jẹ́ kí a dúró ní ìlú yìí tí í ṣe ti àwọn ará Jebusi kí a sì sùn níbẹ̀.”
Jebus taengah tah khohnin khaw dalh thok tih a boei te cadong loh, “Cet uh sih lamtah Jebusi khopuei la ng'ael phoeiah rhaeh uh sih,” a ti nah.
12 Ọ̀gá rẹ̀ dá a lóhùn pé, “Rárá o, àwa kì yóò wọ ìlú àwọn àjèjì, àwọn tí olùgbé ibẹ̀ kì í ṣe ọmọ Israẹli, a yóò dé Gibeah.”
Tedae anih te a boei loh, “Kholong kho la ael boel sih, amih te Israel ca moenih, te dongah Gibeah la cet uh mai sih,” a ti nah.
13 Ó fi kún un pé, ẹ wá ẹ jẹ́ kí a gbìyànjú kí a dé Gibeah tàbí Rama kí a sùn ní ọ̀kan nínú wọn.
Te phoeiah cadong te, “Cet sih lamtah a hmuen pakhat te moeh sih, Gibeah ah khaw Ramah ah khaw rhaeh uh mai sih,” a ti nah.
14 Wọ́n sì tẹ̀síwájú nínú ìrìnàjò wọn, oòrùn wọ̀ bí wọ́n ti súnmọ́ Gibeah tí ṣe ti àwọn Benjamini.
Te dongah cet uh tih Benjamin khuikah Gibeah taengah a pha tom ah kho tla coeng.
15 Wọ́n yípadà wọ́n lọ sí inú ìlú Gibeah láti wọ̀ síbẹ̀ ní òru náà, wọ́n lọ wọ́n sì jókòó níbi gbọ̀ngàn ìlú náà, ṣùgbọ́n kò sí ẹni tí ó gbà wọ́n sínú ilé rẹ̀ láti wọ̀ sí.
Te dongah pahoi kun ham neh Gibeah ah rhaeh ham khaw paa uh. Te phoeiah cet uh tih khopuei toltung ah ngol uh. Tedae im khuila pah sak ham amih te hlang loh voek pawh.
16 Ní alẹ́ ọjọ́ náà ọkùnrin arúgbó kan láti àwọn òkè Efraimu, ṣùgbọ́n tí ń gbé ní Gibeah (ibẹ̀ ni àwọn ẹ̀yà Benjamini ń gbé) ń ti ibi iṣẹ́ rẹ̀ bọ̀ láti inú oko.
Hlaem vaengah patong pakhat tah lohma lamkah a bibi lamkah lawt halo. Tedae anih khaw Benjamin ca rhoek kah hmuen Gibeah ah aka bakuep Ephraim tlang lamkah hlang van ni.
17 Nígbà tí ó wòkè ó rí arìnrìn-àjò náà ní gbọ̀ngàn ìlú náà, ọkùnrin arúgbó yìí bi í léèrè pé, “Níbo ni ò ń lọ? Níbo ni o ti ń bọ̀?”
Patong loh a mik a huel a sawt hatah khopuei toltung ah yincet hlang pakhat te a hmuh. Te dongah tekah hlang te patong loh, “Me lamkah lae na lo tih melam na caeh eh?,” a ti nah.
18 Ọmọ Lefi náà dá a lóhùn pé, “Bẹtilẹhẹmu ti Juda ni àwa ti ń bọ̀, àwa sì ń lọ sí agbègbè tí ó sá pamọ́ ní àwọn òkè Efraimu níbi ti mo ń gbé. Mo ti lọ sí Bẹtilẹhẹmu ti Juda, èmi sì ń lọ sí ilé Olúwa nísinsin yìí. Kò sí ẹni tí ó gbà mí sí ilé rẹ̀.
Te dongah, “Kaimih tah Judah Bethlehem lamkah Ephraim tlang hlaep la ka cet uh. Te lamkah te Judah Bethlehem la ka cet uh tih BOEIPA im ka paan. Tedae im khuila kai aka pah sak ham hlang om pawh.
19 Àwa ní koríko àti oúnjẹ tó tó fún àwọn kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ wa àti oúnjẹ àti wáìnì fún àwa ìránṣẹ́ rẹ—èmi, ìránṣẹ́bìnrin rẹ àti ọ̀dọ́mọkùnrin tí ó wà pẹ̀lú wa. A ò ṣe aláìní ohun kankan.”
Tahae ah ka laak ham cangkong neh a kamvuelh khaw om pueng. Kamah ham neh na salnu ham khaw, na sal taengkah cadong ham khaw buh neh misurtui om pueng tih hnopai dongah pakhat khaw a tloelnah om pawh,” a ti nah.
20 Ọkùnrin arúgbó náà sì wí pé. “Àlàáfíà fún ọ, bí ó ti wù kí ó rí, èmi yóò pèsè gbogbo ohun tí o nílò, kìkì pé kí ìwọ má ṣe sun ní ìgboro.”
Te dongah tekah hlang te patong loh, “Nang taengah ngaimongnah om saeh. Na tloelnah boeih nen khaw kai taengah om mai toltung ah rhaehba boeh,” a ti nah.
21 Òun sì mú wa sí ilé rẹ̀, ó ń bọ́ àwọn kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ rẹ̀. Lẹ́yìn ìgbà tí wọ́n ti wẹ ẹsẹ̀ wọn, àwọn àlejò náà jẹ, wọ́n mu.
Yin te a im khuila a khuen tih laak a vuelh pah, a kho a silh pah phoeiah a caak a ok uh.
22 Ǹjẹ́ bí wọ́n ti ń ṣe àríyá, kíyèsi i, àwọn ọkùnrin ìlú náà, àwọn ọmọ Beliali kan, yí ilé náà ká, wọ́n sì ń lu ìlẹ̀kùn; wọ́n sì sọ fún baálé ilé náà ọkùnrin arúgbó náà pé, “Mú ọkùnrin tí ó wọ̀ sínú ilé rẹ wá, kí àwa lè mọ̀ ọ́n.”
A lungbuei a voelphoeng uh li vaengah khopuei hlang khui hlang muen ca rhoek loh im te tarha a vael uh tih thohkhaih te a tum uh. Im kung patong te khaw a doek uh uh tih, “Na im la aka pawk hlang te hang khuen lamtah anih ka hmat uh lah eh,” a ti nah.
23 Ọkùnrin, baálé ilé náà sì jáde tọ̀ wọ́n lọ, ó sì wí fún un pé, “Bẹ́ẹ̀ kọ́ ẹ̀yin arákùnrin mi, èmi bẹ̀ yín, ẹ má ṣe hùwà búburú; nítorí tí ọkùnrin yìí ti wọ ilé mi, ẹ má ṣe hùwà òmùgọ̀ yìí.
Tedae im kung te amih taengla ha moe tih, “Ka manuca rhoek nang te tlam moenih, hekah hlang he ka im khuila ha kun coeng dongah thaehuet uh boel mai, boethae halang he tah saii uh boeh.
24 Kíyèsi i, ọmọbìnrin mi ni èyí, wúńdíá, àti àlè rẹ̀; àwọn ni èmi ó mú jáde wá nísinsin yìí, kí ẹ̀yin tẹ̀ wọ́n lógo, kí ẹ̀yin ṣe sí wọn bí ó ti tọ́ lójú yín: ṣùgbọ́n ọkùnrin yìí ni kí ẹ̀yin má ṣe hùwà òmùgọ̀ yìí sí.”
Ka canu, oila neh ka yula kang khuen mai eh. Amih phaep uh lamtah na mik dongah then na ti uh bangla amih rhoi taengah saii uh. Tedae hekah hlang taengah boethae halang hno te saii uh boeh,” a ti nah.
25 Ṣùgbọ́n àwọn ọkùnrin náà kò fetí sí tirẹ̀. Nítorí náà ọkùnrin náà mú àlè rẹ̀ ó sì tari rẹ̀ jáde sí wọn, wọ́n sì bá a fi ipá lòpọ̀, wọ́n sì fi gbogbo òru náà bá a lòpọ̀, nígbà tí ó di àfẹ̀mọ́júmọ́ wọ́n jọ̀wọ́ rẹ̀ lọ́.
Tedae hlang loh hnatun ham a huem uh pawt dongah khosoih loh a yula te a mawt tih amih taengah poeng la a thak pah. Te vaengah anih te a tholh puei uh tih khoyin khing te mincang duela a poelyoe uh. Khothaih a pha daengah huta te a hlah uh.
26 Nígbà tí ojúmọ́ bẹ̀rẹ̀ sí là obìnrin náà padà lọ sí ilé tí ọ̀gá rẹ̀ wà, ó ṣubú lulẹ̀ lọ́nà, ó sì wà níbẹ̀ títí ó fi di òwúrọ̀.
Mincang a pha vaengah tah huta te cet tih a boei a om nah im kah thohka ah khosae duela hmawk sop uh.
27 Nígbà tí ọ̀gá rẹ̀ jí tí ó sì dìde ní òwúrọ̀ tí ó sì ṣí ìlẹ̀kùn ilé náà, tí ó sì bọ́ sí òde láti tẹ̀síwájú nínú ìrìnàjò rẹ̀, kíyèsi i àlè rẹ̀ wà ní ṣíṣubú ní iwájú ilé, tí ọwọ́ rẹ̀ sì di òpó ẹnu-ọ̀nà ibẹ̀ mú,
A boei te mincang ah thoo tih im thohkhaih te a ong. Amah kho long ah voei ham ha moe phai hatah a yula te im thohka kah cingkhaa dongah kut a tloeng tih lawt ana bakop pah.
28 òun sì wí fún obìnrin náà pé, “Dìde jẹ́ kí a máa bá ọ̀nà wa lọ.” Ṣùgbọ́n òun kò dá a lóhùn. Nígbà náà ni ọkùnrin náà gbé e lé orí kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ rẹ̀, ó sì kọjá lọ sí ilé e rẹ̀.
Te dongah anih te, “Thoo lamtah cet pawn sih,” a ti nah. Tedae a doo voel pawt dongah laak dongla a khueh. Te phoeiah tekah hlang te thoo tih a hmuen a paan.
29 Nígbà tí ó dé ilé, ó mú ọ̀bẹ ó sì gé àlè rẹ̀ ní oríkeríke sí ọ̀nà méjìlá, ó sì fi wọ́n ránṣẹ́ sí gbogbo agbègbè Israẹli.
Amah im la a pawk vaengah tah tumcaca a loh tih a yula te a tloeng. Te phoeiah a rhuh te maehpoel hlai nit la a tloek tih Israel khorhi takuem ah a pat.
30 Gbogbo ẹni tí ó rí i sì wí pé, “A kò ti rí i, bẹ́ẹ̀ a kò tí ì ṣe irú nǹkan yìí rí, kì í ṣe láti ọjọ́ tí Israẹli ti jáde tí Ejibiti wá títí di òní olónìí. Ẹ rò ó wò, ẹ gbìmọ̀ràn, kí ẹ sọ fún wa ohun tí a yóò ṣe!”
Te tla aka om te boeih a hmuh uh vaengah, “Egypt kho lamkah n'thoo uh hnin lamkah loh tihnin duela te bang te Israel ca rhoek taengah om pawt tih hmuh noek bal moenih. He he nangmih loh dueh uh, anih he dawtlet uh lamtah thui uh,” a ti nah.

< Judges 19 >