< Judges 18 >

1 Ní ọjọ́ wọ̀n-ọn-nì, àwọn ọmọ Israẹli kò ní ọba. Ní ọjọ́ wọ̀n-ọn-nì, àwọn ẹ̀yà Dani ń wá ilẹ̀ tiwọn, níbi tí wọn yóò máa gbé, nítorí pé títí di àkókò náà wọn kò ì tí ì pín ogún ilẹ̀ fún wọn ní ìní láàrín àwọn ọmọ Israẹli.
I aua ra kahore o Iharaira kingi: i aua ra hoki e rapu ana te iwi o nga Rani i tetahi kainga mo ratou hei nohoanga; kihai hoki tetahi kainga tupu i tau ki a ratou i roto i nga iwi o Iharaira a tae noa ki taua ra.
2 Nítorí náà àwọn ẹ̀yà Dani rán àwọn jagunjagun márùn-ún lọ láti Sora àti Eṣtaoli láti yọ́ ilẹ̀ náà wò àti láti rìn ín wò. Àwọn ènìyàn wọ̀nyí ṣe ojú fún gbogbo àwọn ẹ̀yà wọn. Wọ́n wí fún wọn pé, “Ẹ lọ kí ẹ rin ilẹ̀ náà ká, kí ẹ sì wò ó fínní fínní.” Àwọn ọkùnrin náà wọ àwọn ìlú tí ó wà ní agbègbè òkè Efraimu, wọ́n sì dé ilé Mika, níbi tí wọ́n sùn ní òru náà.
Na ka tono nga tamariki a Rana i etahi tangata tokorima o to ratou hapu, he hunga maia, i roto i o ratou rohe, i Toraha, i Ehetaoro, hei tutei i te whenua, hei titiro hoki: i mea hoki ki a ratou, Tikina, tirohia te whenua. Na ka tae ratou ki te w henua pukepuke o Eparaima, ki te whare o Mika, noho ana i reira.
3 Nígbà tí wọ́n súnmọ́ tòsí ilé e Mika, wọ́n dá ohùn ọ̀dọ́mọkùnrin Lefi náà mọ̀, torí náà wọ́n yípadà, wọ́n sì wọ inú ilé náà lọ wọ́n sì bi í pé, “Tá ni ó mú ọ wa sí ibi? Kí ni ìwọ ń ṣe níhìn-ín yìí? Èéṣe tí o fi wà ní ibí?”
I a ratou i te whare o Mika, ka mohiotia e ratou te reo o taua taitamariki, o te Riwaiti: na peka ana ki reira, a ka mea ki a ia, Na wai koe i kawe mai ki konei? e aha ana hoki koe i konei? a he aha tau i konei?
4 Ó sọ ohun tí Mika ti ṣe fún un, ó fi kún un fún wọn pé, “Ó gbà mí sí iṣẹ́, èmi sì ni àlùfáà rẹ̀.”
Na ka mea ia ki a ratou, Ko nga mea tenei i meatia e Mika ki ahau; nana hoki ahau i utu, na hei tohunga ano ahau ki a ia.
5 Wọ́n wí fún un pé, “Jọ̀wọ́ béèrè ní ọwọ́ Ọlọ́run, kí àwa lè mọ̀ bí ìrìnàjò wa yóò yọrí sí rere.”
A ka mea ratou ki a ia, Tena, ui atu ki te Atua kia mohio ai matou ka tika ranei to matou ara e haere nei matou.
6 Àlùfáà náà dá wọn lóhùn pé, “Ẹ máa lọ ní àlàáfíà. Ìrìnàjò yín tí ẹ̀yin ń rìn bá ojúrere Olúwa pàdé.”
Na ka mea te tohunga ki a ratou, Haere marie, kei te aroaro o Ihowa to koutou ara e haere na koutou.
7 Àwọn ọkùnrin márààrún náà kúrò, wọ́n sì wá sí Laiṣi, níbi tí wọ́n ti rí i pé àwọn ènìyàn tí ń gbé ibẹ̀ ní ààbò, bí àwọn ará Sidoni, láìsí ìfòyà àti ní ìpamọ́. Ní ìgbà tí ilẹ̀ wọn kò ṣe aláìní ohunkóhun, wọ́n ní ọrọ̀ púpọ̀. Ibùgbé wọn tún jìnnà sí ti àwọn ará Sidoni, wọn kò fi ohunkóhun bá ẹnikẹ́ni dàpọ̀.
Na ka haere aua tangata tokorima, ka tae ki Raihi, a ka kite i nga tangata o reira, i te pai o ta ratou noho, rite tonu ki a nga Haironi, te ata noho, te mau; kahore hoki he tangata whai mana o te whenua hei mea kia whakama ratou ki tetahi mea, a e matara mai ana ratou i nga Haironi, kahore hoki a ratou aha ki tetahi tangata.
8 Nígbà tí wọ́n padà sí Sora àti Eṣtaoli, àwọn arákùnrin wọn bi wọ́n léèrè pé, “Báwo ni ibi tí ẹ lọ ti rí? Kí ni ìròyìn tí ẹ mú wá?”
Na ka tae ratou ki o ratou tuakana, ki Toraha, ki Ehetaoro; a ka mea o ratou tuakana ki a ratou, He aha ta koutou korero?
9 Wọ́n dáhùn pé, “Ẹ dìde ẹ jẹ́ kí a lọ kọlù wọ́n! A wá rí i pé ilẹ̀ náà dára gidigidi. Ṣé ẹ̀yin ó sì jókòó láìsí nǹkan nípa rẹ̀? Ẹ má ṣe lọ́ra láti lọ síbẹ̀ kí ẹ sì gba ilẹ̀ náà.
Katahi ratou ka mea atu, Whakatika, kia whakaekea ratou e tatou; kua kite hoki matou i te whenua, na he pai rawa; a me ata noho ano ranei koutou? kaua ra e mangere, ki te haere ki te tango i tera whenua:
10 Nígbà tí ẹ̀yin bá dé ibẹ̀, ẹ yóò rí àwọn ènìyàn tí ọkàn wọn balẹ̀ àti ilẹ̀ tí ó tẹ́jú tí Ọlọ́run ti fi fún yín, ilẹ̀ tí kò ṣe aláìní nǹkan kan.”
Ka haere koutou, ka tae atu koutou ki tetahi iwi e noho tatu ana, a he nui hoki te whenua; kua homai nei hoki e te Atua ki o koutou ringa; he wahi, kahore nei i hapa i tetahi mea o te whenua.
11 Nígbà náà ni ẹgbẹ̀ta ọkùnrin tí ó múra ogun láti ìran Dani, jáde lọ láti Sora àti Eṣtaoli ní mímú ra láti jagun.
Na turia atu ana i reira e te hapu o nga Rani, i roto i Toraha, i Ehetaoro, e ono rau tangata, whitiki rawa ki nga rakau o te whawhai.
12 Wọ́n sì jáde lọ, ní ojú ọ̀nà wọn, wọ́n tẹ̀dó ogun sí ẹ̀bá Kiriati-Jearimu ní Juda. Ìdí nìyí tí wọ́n fi ń gbé ìwọ̀-oòrùn Kiriati-Jearimu ni Mahane-Dani títí di òní yìí.
Na ka haere ratou, a ka pupahi ki Kiriata Tearimi, ki Hura; koia i huaina ai te ingoa o tera wahi, ko Mahanerana a mohoa noa nei: koia tena i tua atu o Kiriata Tearimi.
13 Láti ibẹ̀ wọ́n kọjá lọ sí àwọn ìlú agbègbè òkè Efraimu, wọ́n sì dé ilé Mika.
Na, i haere atu ratou i reira ki te whenua pukepuke o Eparaima, a ka tae ki te whare o Mika.
14 Nígbà náà ni àwọn ọkùnrin márùn-ún tí ó lọ yọ́ ilẹ̀ Laiṣi wò sọ fún àwọn arákùnrin wọn pé, “Ǹjẹ́ ẹ̀yin mọ̀ pé ọ̀kan nínú àwọn ilé yìí ní ẹ̀wù efodu, àwọn yòókù ní òrìṣà, ère gbígbẹ́ àti ère dídà? Ẹ mọ ohun tí ó yẹ kí ẹ ṣe báyìí.”
Na ko te ohonga o nga tangata tokorima i haere nei ki te tutei i te whenua o Raihi, ka mea ki o ratou tuakana, E mohio ana ranei koutou kei enei whare he epora, he terapimi, he whakapakoko whaowhao, me tetahi mea whakarewa? na ma koutou te whaka aro ki ta koutou e mea ai.
15 Wọ́n sì yà sí ibẹ̀, wọ́n sì wọ ilé ọ̀dọ́mọkùnrin Lefi náà, sí ilé Mika, wọ́n sì béèrè àlàáfíà rẹ̀.
Na ka peka ratou ki reira, a ka tae ki te whare o taua taitamariki, o te Riwaiti, ara ki te whare o Mika, a oha atu ana ki a ia.
16 Àwọn ẹgbẹ̀ta ọkùnrin ará Dani náà tí ó hámọ́ra ogun, dúró ní àbáwọlé ẹnu odi.
A, ko nga tangata e ono rau o nga tama a Rana me a ratou rakau whawhai, tu tonu i te tomokanga o te kuwaha.
17 Àwọn ọkùnrin márùn-ún tí wọ́n lọ yọ́ ilẹ̀ náà wò wọlé lọ wọ́n sì kó ère gbígbẹ́ náà, efodu náà, àwọn òrìṣà ìdílé àti ère dídà náà nígbà tí àlùfáà náà àti àwọn ẹgbẹ̀ta ọkùnrin tí ó hámọ́ra ogun dúró ní à bá wọ ẹnu odi náà.
Na haere atu ana nga tangata tokorima i haere ra ki te tutei i te whenua, a ka tae ki reira; kei te tango i te whakapakoko whakairo, i te epora, i nga terapimi, i te whakapakoko hoki i whakarewaina: na ko te tohunga i te tomokanga ki te kuwaha e tu ana, ratou ko nga tangata e ono rau, me a ratou rakau whawhai, whitiki tonu.
18 Nígbà tí àwọn ọkùnrin yìí wọ ilé e Mika lọ tí wọ́n sì kó ère fínfín náà, efodu náà, àwọn òrìṣà ìdílé mìíràn àti ère dídà náà, àlùfáà náà béèrè lọ́wọ́ wọn wí pé, “Kí ni ẹ̀yin ń ṣe?”
A, no te haerenga o era ki te whare o Mika, no te tangohanga i te whakapakoko whakairo, i te epora, i nga terapimi, i te mea hoki i whakarewaina, ka mea te tohunga ki a ratou, E aha ana koutou?
19 Wọ́n dá a lóhùn pé, “Dákẹ́! Ma sọ nǹkan kan, tẹ̀lé wa kí o sì di baba àti àlùfáà wa. Kò ha sàn fún ọ láti máa ṣe ìránṣẹ́ ẹ̀yà àti ìdílé kan tí ó wá láti Israẹli bí àlùfáà ju ilé ẹnìkan ṣoṣo lọ?”
Ano ra ko ratou ki a ia, Whakarongoa, kopania atu tou ringa ki tou mangai, a haere mai tatou, hei matua hoki koe mo matou, hei tohunga. Ko tehea te mea pai? kia waiho koe hei tohunga mo te whare o te tangata kotahi, kia waiho ranei hei tohunga m o tetahi iwi, mo tetahi hapu hoki o Iharaira?
20 Nígbà náà ni inú àlùfáà náà sì dùn, òun mú efodu náà, àwọn òrìṣà ìdílé mìíràn àti ère fínfín náà, ó sì bá àwọn ènìyàn náà lọ.
Na ka koa te ngakau o te tohunga, a ka mau ia ki te epora, ki nga terapimi, ki te whakapakoko whakairo, a haere ana i roto i taua hunga.
21 Wọ́n kó àwọn ọmọdé wọn, àwọn ohun ọ̀sìn wọn àti gbogbo ohun ìní wọn síwájú, wọ́n yípadà wọ́n sì lọ.
Katahi ratou ka tahuri, ka haere; a maka ana e ratou nga tamariki, nga kararehe, me nga taonga ki mua i a ratou.
22 Nígbà tí wọ́n ti rìn jìnnà díẹ̀ sí ilé Mika, àwọn ọkùnrin tí ó wà ní agbègbè Mika kó ara wọn jọ, wọ́n sì lé àwọn ará Dani bá.
Ka matara atu ratou i te whare o Mika, na ka huihuia nga tangata o nga whare i tata ki te whare o Mika, a ka mau atu i a ratou nga tama a Rana.
23 Bí wọ́n ṣe ń pariwo tẹ̀lé wọn lẹ́yìn, àwọn ará Dani yípadà wọ́n sì bi Mika pé, “Kí ló ṣe ọ́ tí o fi pe àwọn ọkùnrin rẹ jáde láti jà?”
Na ka karanga ratou ki nga tama a Rana. A ka tahuri mai nga aroaro o era, ka mea ki a Mika, He aha tau i huihui tangata mai ai koe?
24 Ó dáhùn pé, “Ẹ̀yin kó àwọn ère tí mo ṣe, àti àlùfáà mi lọ. Kí ni ó kù tí mo ní? Báwo ni ẹ̀yin ò ṣe béèrè pé, ‘Kí ló ṣe ọ́?’”
Na ka mea ia, Kua tangohia atu ra e koutou aku atua i hanga ai, me te tohunga, a kua haere atu; a he aha atu ano taku? he aha hoki kia ki mai koutou ki ahau, He aha tau?
25 Àwọn ọkùnrin Dani náà dáhùn pé, “Má ṣe bá wa jiyàn, tàbí àwọn oníbìínú fùfù ènìyàn lè kọlù yín, ìwọ àti àwọn ìdílé yóò sì sọ ẹ̀mí yín nù.”
A ka mea nga tama a Rana ki a ia, Kei rangona tou reo e matou, kei torere atu ki a koe te hunga ngakau aritarita, a ka mate koe me tou whare katoa.
26 Àwọn ọkùnrin Dani náà sì bá ọ̀nà wọn lọ. Nígbà tí Mika rí í pé wọ́n lágbára púpọ̀ fún òun, ó sì padà sí ilé rẹ̀.
Na haere ana nga tama a Rana i to ratou ara, i te kitenga hoki o Mika he kaha rawa ratou i a ia, ka tahuri ia, a hoki ana ki tona whare.
27 Wọ́n sì kó àwọn ohun tí Mika ti ṣe àti àlùfáà rẹ̀, wọ́n sì kọjá lọ sí Laiṣi, ní ọ̀dọ̀ àwọn ènìyàn tí ó ní ìbàlẹ̀ ọkàn tí wọ́n sì wà ní àlàáfíà. Wọ́n fi ojú idà kọlù wọ́n, wọ́n sì jó ìlú wọn run.
A maua atu ana e ratou nga mea i hanga e Mika, me te tohunga i noho ki a ia, a haere ana ki Raihi, ki tetahi iwi e ata noho ana, kahore ona whakaohooho; na patua iho e ratou ki te mata o te hoari, tahuna ake hoki e ratou te pa ki te ahi.
28 Kò sì sí ẹnikẹ́ni tí yóò gbà wọ́n sílẹ̀ nítorí pé ibi tí wọ́n ń gbé jìnà sí àwọn ará Sidoni, wọn kò sì ní àṣepọ̀ pẹ̀lú ẹnikẹ́ni. Ìlú náà wà ní inú àfonífojì lẹ́bàá a Beti-Rehobu. Àwọn ará Dani sì tún ìlú náà kọ́, wọ́n sì ń gbé inú rẹ̀.
Kahore hoki he tangata hei whakaora; no te mea he matara a reira i Harona, kahore ano a ratou aha ki tetahi tangata: i te raorao hoki a reira, i Peterehopo. Na hanga ana e ratou te pa, a noho ana i reira.
29 Wọ́n sọ orúkọ ìlú náà ní Dani gẹ́gẹ́ bí orúkọ baba ńlá wọn Dani, ẹni tí wọ́n bí fún Israẹli: bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé Laiṣi ni orúkọ ìlú náà tẹ́lẹ̀ rí.
A huaina ana e ratou te ingoa o te pa ko Rana, ko te ingoa o to ratou matua, o Rana, i whanau nei ma Iharaira: ko Raihi ia te ingoa o te pa i mua.
30 Àwọn ọmọ Dani sì gbé àwọn ère kalẹ̀ fún ara wọn níbẹ̀; Jonatani ọmọ Gerṣomu, ọmọ Mose, àti àwọn ọmọ rẹ̀ ni àlùfáà fún àwọn ẹ̀yà Dani títí di àkókò tí a kó ilẹ̀ náà ní ìgbèkùn.
Na whakaturia ana e nga tama a Rana mo ratou te whakapakoko whaowhao, a ko Honatana hoki tama a Kerehoma, tama a Mohi, ratou ko ana tama nga tohunga o te iwi o nga Rana tae noa ki te ra i whakaraua ai te whenua.
31 Wọ́n tẹ̀síwájú láti lo àwọn ère tí Mika ṣe, ní gbogbo àkókò tí ilé Ọlọ́run wà ní Ṣilo.
A tu tonu ta ratou whakapakoko whakairo, ta Mika i hanga ra, i nga ra katoa o te whare o te Atua i Hiro.

< Judges 18 >