< Judges 17 >

1 Nígbà náà ni ọkùnrin kan tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Mika láti agbègbè òkè Efraimu
Te vaengah Ephraim tlang lamkah hlang pakhat, a ming ah Mikhaiah te om.
2 sọ fún ìyá rẹ̀ pé, “Ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀fà ṣékélì fàdákà èyí tí wọ́n jí mọ́ ọ lọ́wọ́, àti nípa èyí tí mo gbọ́ tí ìwọ ń ṣẹ́ èpè. Kíyèsi fàdákà náà wà ní ọ̀dọ̀ mi, èmi ni mo kó o.” Nígbà náà ni ìyá rẹ̀ dáhùn pé, “Kí Olúwa bùkún ọ ọmọ mi!”
Te vaengah a manu taengah, “Nang taengkah cak thawngkhat yakhat a loh dongah nang n'tap coeng. Ka hna ah khaw, 'Cak te kamah taengla ka loh ne,’ a ti,” a ti nah. Te dongah a manu loh, “BOEIPA rhangneh ka ca a yoethen,” a ti.
3 Nígbà tí ó da ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀fà ṣékélì fàdákà náà padà fún ìyá rẹ̀, ìyá rẹ̀ dáhùn pé, “Èmi ti fi òtítọ́ inú ya sílífà náà sọ́tọ̀ sí Olúwa fún ọmọ mi láti fi dá ère dídá àti ère gbígbẹ́. Èmi yóò dá a padà fún ọ.”
Te dongah cak thawngkhat yakhat te a manu taengla a bal hatah a manu loh, “Ka kut lamkah cak te ka ca kah mueithuk neh mueihlawn saii nah ham BOEIPA taengah ka hoep rhoela ka hoep coeng. Te dongah namah taengla kam mael pawn ni,” a ti nah.
4 Nítorí náà òun dá sílífà náà padà fún ìyá rẹ̀, ìyá rẹ̀ sì mú igba ṣékélì fàdákà, ó sì fún alágbẹ̀dẹ fàdákà ẹni tí ó fi wọ́n rọ ère fínfín àti ère dídà. Wọ́n sì kó wọn sí ilé Mika.
Te dongah a manu taengla a mael tangtae cak te a manu loh a loh. Cak yakhat te, mueithuk aka saii tih mueihlawn aka hlawn, Mikhaiah im kah aka om taengah a paek.
5 Ọkùnrin náà, Mika sì ní ojúbọ kan. Òun sì ra ẹ̀wù efodu kan, ó sì ṣe àwọn ère kan, ó sì fi ọ̀kan nínú àwọn ọmọ rẹ̀ ọkùnrin ṣe àlùfáà rẹ̀.
Tekah hlang Maikah amah taengah pathen im pakhat om. Te dongah hnisui neh sithui te a saii tih a ca rhoek khui lamkah pakhat kut dongah a poem sak phoeiah amah kah khosoih la a khueh.
6 Ní ọjọ́ wọ̀n-ọn-nì àwọn ọmọ Israẹli kò ní ọba; olúkúlùkù ṣe bí ó ti rò pé ó tọ́ ní ojú ara rẹ́.
Te vaeng tue ah Israel he manghai a khueh pawt dongah hlang boeih loh a mik dongkah a thuem sak bangla a saii.
7 Ọ̀dọ́mọkùnrin kan sì ti Bẹtilẹhẹmu ti Juda wá, tí í ṣe ìdílé Juda, ẹni tí í ṣe ẹ̀yà Lefi, òun sì ṣe àtìpó níbẹ̀,
Te vaengah Judah kho Bethlehem lamkah Judah koca cadong pakhat om tih anih khaw Levi la a om dongah te ah te pah van.
8 ọkùnrin náà sì ti ìlú Bẹtilẹhẹmu ti Juda lọ, láti ṣe àtìpó ní ibikíbi tí ó bá rí. Ní ojú ọ̀nà àjò rẹ̀, ó dé ilẹ̀ Mika nínú àwọn ilẹ̀ òkè Efraimu.
Judah Bethlehem khopuei lamkah hlang te cet tih a pah nah te a toem tih a longpuei a thuep hatah Ephraim tlang kah Maikah im la pawk.
9 Mika bi í pé, “Níbo ni ó ti ń bọ̀?” Ó dáhùn pé, “Ọmọ Lefi ni mí láti Bẹtilẹhẹmu Juda, mo sì ń wá ibi tí èmi yóò máa gbé.”
Te vaengah anih te Maikah loh, “Me lamkah lae na thoeng,” a ti nah hatah, “Kai he Judah Bethlehem lamkah Levi ni, te dongah pah nah te toem ham ka caeh dae he,” a ti nah.
10 Mika sì sọ fún un wí pé, “Dúró lọ́dọ̀ mi kí ìwọ sì jẹ́ baba mi àti àlùfáà fún mi, èmi ó sì máa fún ọ ní ṣékélì mẹ́wàá fàdákà ní ọdọọdún, pẹ̀lú aṣọ àti oúnjẹ rẹ̀.”
Te dongah anih te Maikah loh, “Kai taengah khosa mai lamtah kai hamla a pa banghui neh khosoih lam khaw om mai. Nang te kamah loh kum khat ah cak a laang, himbai phu, na thahuelnah khaw kam paek bitni,” a ti nah. Te dongah Levi te khaw pahoi kun.
11 Ọmọ Lefi náà sì gbà láti máa bá a gbé, ọ̀dọ́mọkùnrin náà sì dàbí ọ̀kan nínú àwọn ọmọ rẹ̀.
Levi khaw hlang neh khosak ham a mulmet coeng dongah a capa pakhat bangla anih taengah cadong la a om pah.
12 Nígbà náà ni Mika ya ará Lefi náà sí mímọ́, ọ̀dọ́mọkùnrin náà sì di àlùfáà rẹ̀, ó sì ń gbé ilé rẹ̀.
Levi kut te khaw Maikah loh a khueh pah coeng dongah cadong khaw anih kah khosoih la a om pah tih Maikah im ah kho a sak.
13 Mika sì wí pé, “Báyìí, èmi mọ̀ pé Olúwa yóò ṣe mi ní oore nítorí pé mo ní ọmọ Lefi ní àlùfáà mi.”
Te daengah Maikah loh, “Levi he ka khosoih la om coeng tih kai hamla BOEIPA then tila ka ming coeng,” a ti.

< Judges 17 >