< Judges 15 >

1 Lẹ́yìn ìgbà díẹ̀, ní àkókò ìkórè alikama, Samsoni mú ọ̀dọ́ ewúrẹ́ kan láti bẹ ìyàwó rẹ̀ wò. Ó ní, “Èmi yóò wọ yàrá ìyàwó mi lọ.” Ṣùgbọ́n baba rẹ̀ kò gbà á láààyè láti wọlé.
Tok kutu, ke pacl in kosrani lun wheat, Samson el us nani fusr soko ac som in osun nu sin mutan kial ah. El fahk nu sin papa talupal, “Nga lungse utyak nu ke infukil lun mutan kiuk ah.” Tusruktu papa sac tia lela.
2 Baba ìyàwó dá a lóhùn pé, “Ó dá mi lójú pé o kórìíra rẹ̀, torí náà mo ti fi fún ọ̀rẹ́ rẹ, ṣe bí àbúrò rẹ̀ obìnrin kò ha lẹ́wà jùlọ? Fẹ́ ẹ dípò rẹ̀.”
El fahk nu sel Samson, “Nga pangon kom srungalla na pwaye, oru nga eisalang nu sin kawuk se lom ah. Tusruktu tamtael fusr se wial inge el kato lukel. Kom ku in eisal elan aolulla.”
3 Samsoni dáhùn pé, “Ní àkókò yìí tí mo bá ṣe àwọn Filistini ní ibi èmi yóò jẹ́ aláìjẹ̀bi.”
Na Samson el fahk, “Inge, nga finne oru kutu ma upa nu sin mwet Philistia, ac fah wangin mwetik kac.”
4 Samsoni sì jáde lọ, ó mú ọ̀ọ́dúnrún kọ̀lọ̀kọ̀lọ̀ ó so ìrù wọn mọ́ ara wọn ní méjì méjì. Ó mú ètùfù iná, ó so ó mọ́ àwọn ìrù tí ó so pọ̀.
Na el som ac sruokya kosro fox tolfoko ac kapriya pulalos kais lukwa, ac sang kahp in e nu kac.
5 Ó fi iná ran àwọn ètùfù tí ó so náà, ó sì jọ̀wọ́ wọn lọ́wọ́ lọ sínú àwọn oko ọkà àwọn Filistini. Ó jó àwọn pòpóòrò ọkà tí ó dúró àti àwọn tí a dì ní ìtí, ìtí, pẹ̀lú àwọn ọgbà àjàrà àti olifi.
Na el akosak kahp inge ac fuhlelosla in ima in wheat lun mwet Philistia ah. Ouinge wheat ma elos kosrani tari ac wheat ma srakna kapak in ima ah, firiryak nufon, oayapa sak olive wi pac folla.
6 Nígbà tí àwọn Filistini béèrè pé, “Ta ni ó ṣe èyí?” Wọ́n dá wọn lóhùn pé, “Samsoni ará Timna ni, nítorí a gba ìyàwó rẹ̀ fún ọ̀rẹ́ rẹ̀.” Nítorí náà àwọn Filistini lọ wọ́n sì sun obìnrin náà àti baba rẹ̀.
Ke mwet Philistia elos siyuk lah su oru ma inge, na fwackyang nu selos lah Samson pa oru uh, mweyen papa talupal el tuh eisalang mutan kial Samson nu sin kawuk se lal Samson ah. Ouinge mwet Philistia elos som ac esukak lohm sin papa sac, na mutan sac ac sou lal nufon misa.
7 Samsoni sọ fún un pé, “Nítorí pé ẹ̀yin ṣe èyí, èmi ó gbẹ̀san lára yín, lẹ́yìn náà èmi yóò sì dẹ́kun.”
Samson el fahk nu selos, “Fin pa inge orekma lowos uh, nga fulahk lah nga fah tiana tui nwe ke na nga aksafyela foloksak luk nu suwos!”
8 Ó kọlù wọ́n pẹ̀lú ìbínú àti agbára ńlá, ó sì pa ọ̀pọ̀lọpọ̀ nínú wọn. Lẹ́yìn náà ni ó lọ, ó sì dúró nínú ihò àpáta kan nínú àpáta Etamu.
El oru sie mweun na upa, ac onela mwet puspis selos. Na el som ac muta in luf se ke eot fulat in Etam.
9 Àwọn ará Filistini sì dìde ogun sí Juda, wọ́n ti tan ara wọn ká sí agbègbè Lehi.
Mwet Philistia elos tuku ac tulokunak lohm nuknuk selos in acn Judah, ac elos mweuni acn Lehi.
10 Àwọn ọkùnrin Juda sì béèrè pé, “Èéṣe tí ẹ fi wá gbóguntì wá?” Ìdáhùn wọn ni pé, “A wá láti mú Samsoni ní ìgbèkùn, kí a ṣe sí i bí òun ti ṣe sí wa.”
Mwet Judah elos siyuk selos, “Efu ku kowos tuku mweuni kut?” Na elos fahk, “Kut tuku in sruokilya Samson in folokin nu sel ma el oru nu sesr.”
11 Nígbà náà ni ẹgbẹ̀rún mẹ́ta ọkùnrin láti Juda sọ̀kalẹ̀ lọ sí ihò àpáta nínú àpáta Etamu, wọ́n sì sọ fún Samsoni pé, “Kò ti yé ọ pé àwọn Filistini ní ń ṣe alákòóso lórí wa? Kí ni o ṣe sí wa?” Òun sì dáhùn pé, “Ohun tí wọ́n ṣe sí mi ni èmi náà ṣe sí wọn.”
Na tausin tolu sin mwet Judah inge som nu ke luf se ke eot fulat in Etam ac fahk nu sel Samson, “Ya kom nikin lah mwet Philistia elos pa leum facsr uh— Mea se kom oru nu sesr inge?” Na el topuk ac fahk nu selos, “Ma na elos oru nu sik ah pa nga oru oapana nu selos.”
12 Wọ́n wí pé, “Àwa wá láti dè ọ́, kí a sì fi ọ́ lé àwọn Filistini lọ́wọ́.” Samsoni wí pé, “Ẹ búra fún mi pé, ẹ̀yin kì yóò fúnra yín pa mí.”
Na elos fahk nu sel, “Kut tuku in kaprikomi tuh kut in eiskomyang nu inpaolos.” Na Samson el fahk, “Fulahk nu sik lah kowos ac tia sifacna uniyuwi.”
13 “Àwa gbà,” ni ìdáhùn wọn. “Àwa yóò kàn dè ọ́, àwa yóò sì fi ọ́ lé wọn lọ́wọ́, àwa kì yóò pa ọ́.” Wọ́n sì dé pẹ̀lú okùn tuntun méjì, wọ́n sì mú u jáde wá láti ihò àpáta náà.
Na elos fahk, “Aok, kut ac tia unikomi. Kut ac kaprikomi na, ac eiskomyang nu selos.” Ouinge elos kaprilya ke sucl sasu lukwa ac pwanulak liki eot fulat sac.
14 Bí ó ti súnmọ́ Lehi, àwọn Filistini ń pariwo bí wọ́n ṣe ń tò bọ̀. Ẹ̀mí Olúwa bà lé e pẹ̀lú agbára. Àwọn okùn ọwọ́ rẹ̀ dàbí òwú tí ó jóná, ìdè ọwọ́ rẹ̀ já kúrò ní ọwọ́ rẹ̀.
Ke el sun acn Lehi, mwet Philistia elos sasa ac kasrusr tuku nu yorol. In kitin pacl ah na, ku lun LEUM GOD putati nu facl, ac el wotyalik sucl ma kapriya paol oana luman turet ma firirla tari, ac mwe kapir putatla liki paol.
15 Nígbà tí ó rí egungun àgbọ̀n ìsàlẹ̀ kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ tuntun kan, ó mú un, ó sì fi pa ẹgbẹ̀rún ọkùnrin.
Na el konauk srin oalin donkey soko ma tufahna misa, ac el srukak ac sang onela sie tausin mwet kac.
16 Samsoni sì wí pé, “Pẹ̀lú egungun àgbọ̀n ìsàlẹ̀ kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ kan, mo sọ wọ́n di òkìtì kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́. Pẹ̀lú egungun àgbọ̀n ìsàlẹ̀ kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ kan, mo ti pa ẹgbẹ̀rún ọkùnrin.”
Na Samson el on ac fahk, “Ke srin oalin donkey soko, nga uniya sie tausin mwet; Ke srin oalin donkey soko, nga elosak yolin mwet.”
17 Nígbà tí ó dákẹ́ ọ̀rọ̀ í sọ, ó ju egungun àgbọ̀n ìsàlẹ̀ náà nù, wọ́n sì pe ibẹ̀ ní Ramati-Lehi (ìtumọ̀ rẹ̀ jẹ́ egungun àgbọ̀n ìsàlẹ̀ pa).
Tukun ma inge, el sisla sri soko ah, na pangpang acn se ma inge sikyak we ah Ramath Lehi.
18 Nítorí tí òǹgbẹ gbẹ ẹ́ gidigidi, ó ké pe Olúwa, wí pé, “Ìwọ ti fún ìránṣẹ́ ní ìṣẹ́gun tí ó tóbi yìí. Ṣé èmi yóò ha kú pẹ̀lú òǹgbẹ, kí èmi sì ṣubú sí ọwọ́ àwọn aláìkọlà ènìyàn?”
Na Samson el arulana malu, ouinge el pang nu sin LEUM GOD ac fahk, “Kom ase kutangla na lulap se inge nu sik. Ya pwaye nga ac misa ke sripen malu, ac putatyang nu inpoun mwet pegan?”
19 Nígbà náà ni Ọlọ́run la kòtò ìsun omi tí ó wà ní Lehi, omi sì tú jáde láti inú rẹ̀. Nígbà tí Samsoni mú mi tan, agbára rẹ̀ sì padà, ọkàn sì sọjí, fún ìdí èyí wọ́n pe ìsun omi náà ni. Ẹni Hakkore (orísun ẹni tí ó pe Ọlọ́run) èyí tí ó sì wà ní Lehi di òní.
Na God El ikaselik sie acn oalal infohk uh in acn Lehi, ac kof unonak kac me. Ke Samson el nimkofi ngunal folokyang, na el sifilpa kui. Ouinge unon in kof se inge pangpang En-Hakkore, ac srakna oasr in acn Lehi nwe misenge.
20 Samsoni ṣe ìdájọ́ Israẹli fún ogún ọdún ní àkókò àwọn ará Filistini.
Samson el tuh nununku mwet Israel yac longoul, ke pacl se mwet Israel elos muta ye poun mwet Philistia.

< Judges 15 >