< Judges 14 >

1 Nígbà kan Samsoni gòkè lọ sí Timna níbẹ̀ ni ó ti rí ọmọbìnrin Filistini kan.
Samson teh Timnah kho vah a cei teh, Filistinnaw e a canu napui buet touh a hmu.
2 Nígbà tí ó darí dé, ó sọ fún àwọn òbí rẹ̀ pé, “Mo rí obìnrin Filistini kan ní Timna: báyìí ẹ fẹ́ ẹ fún mi bí aya mi.”
A manu hoi na pa koe a dei pouh. Timnah vah, Filistin tami napui buet touh ka hmu. Hatdawkvah, ka yu lah na lat pouh loe telah atipouh.
3 Baba àti ìyá rẹ̀ dáhùn pé, “Ṣé kò sí obìnrin tí ó dára tí ó sì tẹ́ ọ lọ́rùn ní àárín àwọn ìbátan rẹ, tàbí láàrín gbogbo àwọn ènìyàn wa? Ṣé ó di dandan fún ọ láti lọ sí àárín àwọn Filistini aláìkọlà kí o tó fẹ́ ìyàwó?” Ṣùgbọ́n Samsoni wí fún baba rẹ̀ pé, “Fẹ́ ẹ fún mi torí pé inú mi yọ́ sí i púpọ̀púpọ̀.”
A manu hoi na pa niyah, na hmaunawnghanaw ni canu a tawn hoeh dawk maw, vuensom ka a hoeh e Filistin tami thung dawk e hah na yu lah khuet na tawng, telah atipouh. Samson ni, na lat pouh awh. Bangkongtetpawiteh, ahni teh ka ngai poung telah atipouh.
4 (Àwọn òbí rẹ̀ kò mọ̀ pé ọ̀dọ̀ Olúwa ni nǹkan yìí ti wá, ẹni tí ń wá ọ̀nà àti bá Filistini jà; nítorí àwọn ni ń ṣe àkóso Israẹli ní àkókò náà.)
Hatei, a manu hoi na pa ni hot teh, BAWIPA koehoi e doeh tie hah panuek roi hoeh. Bangkongtetpawiteh, Filistinnaw hanelah atueng a kâremnae a tawngnae doeh. Bangkongtetpawiteh, hatnae tueng nah Filistinnaw ni Isarelnaw hah a uk.
5 Samsoni sọ̀kalẹ̀ lọ sí Timna òun àti baba àti ìyá rẹ̀. Bí wọ́n ṣe ń súnmọ́ àwọn ọgbà àjàrà tí ó wà ní Timna, láìròtẹ́lẹ̀, ọ̀dọ́ kìnnìún kan jáde síta tí ń ké ramúramù bọ̀ wá sí ọ̀dọ̀ rẹ̀.
Hottelah, Samson teh a manu hoi na pa hoi Timnah vah a cei awh. Timnah misur hmuen koe a pha awh navah, sendektan ni hramki laihoi a cusin awh.
6 Ẹ̀mí Olúwa sì bà lé e pẹ̀lú agbára tó bẹ́ẹ̀ tí ó fi fa kìnnìún náà ya pẹ̀lú ọwọ́ rẹ̀ lásán bí ẹní ya ọmọ ewúrẹ́, ṣùgbọ́n òun kò sọ ohun tí ó ṣe fún baba tàbí ìyá rẹ̀.
BAWIPA Muitha ni a tha kaawm poung lahoi a tak dawk a pha. A kut dawk banghai sin hoeh ei, hmaeca raphei e patetlah a raphei teh a thei. Hatei, a sak e hah a manu hoi na pa koe banghai dei pouh hoeh.
7 Ó sì lọ bá obìnrin náà sọ̀rọ̀, inú Samsoni sì yọ́ sí i.
A cei teh hote tangla hoi a kâpan roi teh Samson mit dawk hote napui teh atueng.
8 Lẹ́yìn ìgbà díẹ̀, nígbà tí ó padà lọ láti gbé e níyàwó, ó yà lọ láti wo òkú kìnnìún náà. Inú rẹ̀ ni ó ti bá ọ̀pọ̀ ìṣù oyin àti oyin,
Hathnukkhu hoi la hanelah a cei navah, Sendek e ro teh khet hanelah a phen teh, khenhaw! Sendek e a ro dawkvah khoi ao, a ratui hai ao.
9 ó fi ọwọ́ ha jáde, ó sì ń jẹ ẹ́ bí ó ti ń lọ. Nígbà tí ó dé ọ̀dọ̀ àwọn òbí rẹ̀, ó fún wọn ní díẹ̀, àwọn náà sì jẹ, ṣùgbọ́n kò sọ fún wọn pé ara òkú kìnnìún ni òun ti rí oyin náà.
Hot teh, a la teh, a cei laihoi a ca. A manu hoi na pa hai a poe. Hatei, khoitui teh Sendek dawk e a la e tie hah dei pouh hoeh.
10 Baba rẹ̀ sì sọ̀kalẹ̀ lọ láti kí obìnrin náà. Samsoni sì ṣe àsè gẹ́gẹ́ bí àṣà ọkọ ìyàwó ní àkókò náà.
Hahoi, a na pa teh hote napui koe a cei teh, thoundounnaw ni ouk a sak awh e patetlah, Samson ni pawi bu a paca awh.
11 Nígbà tí ó fi ara hàn, tí àwọn ènìyàn náà rí i wọ́n fún un ní ọgbọ̀n àwọn ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ láti wá bá a kẹ́gbẹ́.
Hahoi teh, hettelah doeh. Haw e taminaw ni Samson a hmu torei teh, a huinaw 30 touh ni a kâbang sin awh.
12 Samsoni sọ fún wọn pé, “Ẹ jẹ́ kí n pa àlọ́ kan fún un yín, bí ẹ̀yin bá lè fún mi ní ìtumọ̀ rẹ̀ láàrín ọjọ́ méje àsè yìí, tàbí ṣe àwárí àlọ́ náà èmi yóò fún un yín ní ọgbọ̀n aṣọ tí a fi òwú ọ̀gbọ̀ hun, àti ọgbọ̀n ìpààrọ̀ aṣọ ìyàwó.
Samson ni kai ni pâveinae lawk buet touh na pacei awh han. Pawi sak hnin hnin sari hnin na dei thai awh pawiteh, kai ni hni yung 30, angki yung 30 na poe awh han.
13 Ṣùgbọ́n tí ẹ̀yin kò bá le sọ ìtumọ̀ rẹ̀ fún mi, ẹ̀yin yóò fún mi ní ọgbọ̀n aṣọ tí a fi òwú ọ̀gbọ̀ hun àti ọgbọ̀n ìpààrọ̀ aṣọ ìgbéyàwó.” Wọ́n dáhùn pé, “Sọ àlọ́ rẹ fún wa jẹ́ kí a gbọ́.”
Hatei, na dei thai awh hoehpawiteh, hnin yung 30, angki yung 30 nangmouh ni kai na poe awh han atipouh. Ahnimouh ni hote ka panuek thai nahanelah, pâveinae lawk hah na dei pouh haw atipouh awh.
14 Ó dáhùn pé, “Láti inú ọ̀jẹun ni ohun jíjẹ ti jáde wá; láti inú alágbára ni ohun dídùn ti jáde wá.” Ṣùgbọ́n fún odidi ọjọ́ mẹ́ta ni wọn kò fi rí ìtumọ̀ sí àlọ́ náà.
Hat toteh, ahni ni a dei pouh, kacatkung thung hoi cakawi a tâco teh, athakaawme dawk hoi ka radip e a tâco. Hote pâveinae hah hnin thum touh thung dei thai awh hoeh.
15 Ní ọjọ́ kẹrin, wọ́n wí fún ìyàwó Samsoni, pé, “Tan ọkọ rẹ kí ó lè ṣe àlàyé àlọ́ náà fún wa, bí bẹ́ẹ̀ kọ́ àwa yóò sun ìwọ àti ìdílé baba rẹ̀ ní iná. Tàbí ṣe o pè wá sí ibi àsè yìí láti sọ wá di òtòṣì tàbí kó wa lẹ́rú ni?”
Hatei, hnin sari hnin Samson e yu koevah, pâveinae hah ka panue thai awh nahan, na vâ hah pasawt haw. Telah hoehpawiteh, nang nama hoi na pa imthungkhu abuemlah hmai ngeng na sawi awh han. Ka tawn awh e hnonaw hah lawp hanelah na coun e namaw telah Samson e yu koe atipouh awh.
16 Nígbà náà ni ìyàwó Samsoni ṣubú lé e láyà, ó sì sọkún ní iwájú rẹ̀ pé, “O kórìíra mi! O kò sì ní ìfẹ́ mi nítòótọ́, o pàlọ́ fún àwọn ènìyàn mi, ìwọ kò sì sọ ìtumọ̀ rẹ̀ fún mi.” “Èmi kò tí ì ṣe àlàyé rẹ̀ fún baba àti ìyá mi, báwo ni èmi ó ṣe sọ ìtumọ̀ rẹ̀ fún ọ.”
Hottelah, Samson e a yu teh, a hmalah thouk a ka teh, kai lung na pataw hoeh teh, na hmawt ngai hoeh toe khe, ka taminaw na pâvei teh, kai koehai na dei kalawn hoeh atipouh. Samson ni anu hoi apa patenghai ka dei pouh hoeh, nang koe khuet ka dei han yaw maw atipouh.
17 Fún gbogbo ọjọ́ méje tí wọ́n fi ṣe àsè náà ni ó fi sọkún, nítorí náà ní ọjọ́ keje ó sọ ìtumọ̀ àlọ́ fún un nítorí pé ó yọ ọ́ lẹ́nu ní ojoojúmọ́. Òun náà sì sọ ìtumọ̀ àlọ́ náà fún àwọn ènìyàn rẹ̀.
Hahoi, pawi ao hoehnahlan, hnin sari touh thung a yu ni a khuika sin. Napui ni kâhat laipalah pou a pacei toteh, napui koe a dei pouh toe. Hahoi teh, napui ni hote pâveinae lawk hah amamouh kho e a taminaw koe a dei pouh toe.
18 Kí ó tó di àṣálẹ́ ọjọ́ keje àwọn ọkùnrin ìlú náà sọ fún un pé, “Kí ni ó dùn ju oyin lọ? Kí ni ó sì lágbára ju kìnnìún lọ?” Samsoni dá wọn lóhùn pé, “Bí kì í bá ṣe pé ẹ fi ọ̀dọ́ abo màlúù mi kọ ilẹ̀, ẹ̀yin kò bá tí mọ ìtumọ̀ sí àlọ́ mi.”
A khocanaw teh asari hnin kanî a loum hoehnahlan a tho awh teh, khoitui hlak bangmaw ka radip, Sendek hlak athakaawme bangmaw kaawm telah a dei pouh awh. Samson ni, nangmouh ni kaie maitola hoi na thawn awh hoeh pawiteh, kaie pâveinae teh na dei thai awh mahoeh, atipouh.
19 Lẹ́yìn èyí, ẹ̀mí Olúwa bà lé e pẹ̀lú agbára. Ó lọ sí Aṣkeloni, ó pa ọgbọ̀n nínú àwọn ọkùnrin wọn, ó gba àwọn ohun ìní wọn, ó sì fi àwọn aṣọ wọn fún àwọn tí ó sọ ìtumọ̀ àlọ́ náà. Ó sì padà sí ilé baba rẹ̀ pẹ̀lú ìbínú ríru.
Hahoi teh, BAWIPA Muitha heh a tha kaawm poung lah Samson koe a pha teh, Askelon vah a cei teh, tami 30 touh a thei. Angki hoi hninaw a lawp teh, pâveinae lawk ka dei thai naw koe a poe. Hahoi a lung puenghoi a phuen teh, a na pa im lah a ban.
20 Wọ́n sì fi ìyàwó Samsoni fún ẹlẹgbẹ́ rẹ̀, tí ó jẹ́ ọ̀rẹ́ tímọ́tímọ́ rẹ̀ nígbà ìgbéyàwó rẹ̀.
Hahoi Samson e a yu teh, a hui hah oun a poe pouh awh.

< Judges 14 >