< Judges 14 >

1 Nígbà kan Samsoni gòkè lọ sí Timna níbẹ̀ ni ó ti rí ọmọbìnrin Filistini kan.
Eso afaega, Sa: masane da Dimina moilaiga asili, Filisidini a: fini afadafa ba: i.
2 Nígbà tí ó darí dé, ó sọ fún àwọn òbí rẹ̀ pé, “Mo rí obìnrin Filistini kan ní Timna: báyìí ẹ fẹ́ ẹ fún mi bí aya mi.”
E da ea diasuga buhagili, ea eda amola ame elama amane sia: i, “Na da Dimina moilaiga Filisidini a: fini ba: i dagoi. Na da amo lamu hanai galebe. Amo lamusa: , ali amo a: fini nagili logela masa.”
3 Baba àti ìyá rẹ̀ dáhùn pé, “Ṣé kò sí obìnrin tí ó dára tí ó sì tẹ́ ọ lọ́rùn ní àárín àwọn ìbátan rẹ, tàbí láàrín gbogbo àwọn ènìyàn wa? Ṣé ó di dandan fún ọ láti lọ sí àárín àwọn Filistini aláìkọlà kí o tó fẹ́ ìyàwó?” Ṣùgbọ́n Samsoni wí fún baba rẹ̀ pé, “Fẹ́ ẹ fún mi torí pé inú mi yọ́ sí i púpọ̀púpọ̀.”
Be ea eda amola ame ela da amane sia: i, “Di da abuliba: le Gode Ea Hou hame lalegagui Filisidini fi uda lamusa: hanabela: ? Ninia fi amoga uda hogole lamu da defea!” Be Sa: masane da bu adole i, “Na da amo a: fini hanai. Na da e fawane lamusa: dawa:”
4 (Àwọn òbí rẹ̀ kò mọ̀ pé ọ̀dọ̀ Olúwa ni nǹkan yìí ti wá, ẹni tí ń wá ọ̀nà àti bá Filistini jà; nítorí àwọn ni ń ṣe àkóso Israẹli ní àkókò náà.)
Hina Gode da hame lalegagui Filisidini dunu ilima gegemusa: logo hogoi helebeba: le, E da Sa: masane ea asigi dawa: su ganodini agoane hamosu. Bai amo esoga, Filisidini dunu da Isala: ili soge ouligisu. Be Sa: masane eda amola ame da amo hou hame dawa: iou.
5 Samsoni sọ̀kalẹ̀ lọ sí Timna òun àti baba àti ìyá rẹ̀. Bí wọ́n ṣe ń súnmọ́ àwọn ọgbà àjàrà tí ó wà ní Timna, láìròtẹ́lẹ̀, ọ̀dọ́ kìnnìún kan jáde síta tí ń ké ramúramù bọ̀ wá sí ọ̀dọ̀ rẹ̀.
Amaiba: le Sa: masane da ea eda amola ame Dimina moilaiga sigi asi. Ilia da waini sagai ganodini asili, Sa: masane da laione wa: me waha debe gasala amo ea gesenenanebe nabi.
6 Ẹ̀mí Olúwa sì bà lé e pẹ̀lú agbára tó bẹ́ẹ̀ tí ó fi fa kìnnìún náà ya pẹ̀lú ọwọ́ rẹ̀ lásán bí ẹní ya ọmọ ewúrẹ́, ṣùgbọ́n òun kò sọ ohun tí ó ṣe fún baba tàbí ìyá rẹ̀.
Hedolowane, Sa: masane da Hina Gode Ea gasa bagade lai. E da amo laione amo goudi mano defele, ea loboga medole legele, magado gowa: i. Be amo hou e da ea ada amola ea ame elama hame adole i.
7 Ó sì lọ bá obìnrin náà sọ̀rọ̀, inú Samsoni sì yọ́ sí i.
Amalalu, e da amo a: fini amoma asili, sia: sa: i. E da amo a: fini hanai.
8 Lẹ́yìn ìgbà díẹ̀, nígbà tí ó padà lọ láti gbé e níyàwó, ó yà lọ láti wo òkú kìnnìún náà. Inú rẹ̀ ni ó ti bá ọ̀pọ̀ ìṣù oyin àti oyin,
Eso didia asili, e da amo a: fini lamusa: bu asi. E da logoga asili, amo logo fisili, laione wa: me e da medole legei amo ba: la asi. E da laione ea da: i hodo ganodini agime fila heda: i amola agime hano dialebe fofogadigili ba: i.
9 ó fi ọwọ́ ha jáde, ó sì ń jẹ ẹ́ bí ó ti ń lọ. Nígbà tí ó dé ọ̀dọ̀ àwọn òbí rẹ̀, ó fún wọn ní díẹ̀, àwọn náà sì jẹ, ṣùgbọ́n kò sọ fún wọn pé ara òkú kìnnìún ni òun ti rí oyin náà.
E da amo agime hano lale, logoga ahoa nana asi. Amalalu, e da ea ada amola ame elama asili, agime hano mogili elama i. Ela da mai dagoi. Be Sa: masane da amo agime hano laione bogoi ea da: i hodo amoga lai, e da elama hame olelei.
10 Baba rẹ̀ sì sọ̀kalẹ̀ lọ láti kí obìnrin náà. Samsoni sì ṣe àsè gẹ́gẹ́ bí àṣà ọkọ ìyàwó ní àkókò náà.
Ea eda da a: fini ea diasuga asi. Amola amoga Sa: masane da lolo nasu hamoi. Bai amo esoga, ayeligi dunu da amo hou hamonanusu.
11 Nígbà tí ó fi ara hàn, tí àwọn ènìyàn náà rí i wọ́n fún un ní ọgbọ̀n àwọn ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ láti wá bá a kẹ́gbẹ́.
Filisidini dunu da Sa: masane ba: beba: le, ilia da Filisidini ayeligi 30 agoane e sigi esaloma: ne, asunasi.
12 Samsoni sọ fún wọn pé, “Ẹ jẹ́ kí n pa àlọ́ kan fún un yín, bí ẹ̀yin bá lè fún mi ní ìtumọ̀ rẹ̀ láàrín ọjọ́ méje àsè yìí, tàbí ṣe àwárí àlọ́ náà èmi yóò fún un yín ní ọgbọ̀n aṣọ tí a fi òwú ọ̀gbọ̀ hun, àti ọgbọ̀n ìpààrọ̀ aṣọ ìyàwó.
13 Ṣùgbọ́n tí ẹ̀yin kò bá le sọ ìtumọ̀ rẹ̀ fún mi, ẹ̀yin yóò fún mi ní ọgbọ̀n aṣọ tí a fi òwú ọ̀gbọ̀ hun àti ọgbọ̀n ìpààrọ̀ aṣọ ìgbéyàwó.” Wọ́n dáhùn pé, “Sọ àlọ́ rẹ fún wa jẹ́ kí a gbọ́.”
Sa: masane da ilima amane sia: i, “Na da dilima idinamasu adole ba: ma: bela: ? Uda lasu lolo nasu eso fesuale amoga, dilia da amo sia: ea bai nama adole iasea, na da dilima afae afae dilima abula noga: i amola abula salasu imunu. Be dilia amo ea bai hame dawa: sea, dilia da nama afae afae abula amola abula salasu noga: iwane ima.” Ilia da ema bu adole i, “Defea! Dia idinamasu ninima adole ima. Ninia nabimu hanai.”
14 Ó dáhùn pé, “Láti inú ọ̀jẹun ni ohun jíjẹ ti jáde wá; láti inú alágbára ni ohun dídùn ti jáde wá.” Ṣùgbọ́n fún odidi ọjọ́ mẹ́ta ni wọn kò fi rí ìtumọ̀ sí àlọ́ náà.
E da ilima amane sia: i, “Liligi da ha: i manu naha amo ea hagomodini amoga ha: i manu da misi. Amola gasa bagade liligi amo ea hagomodini amoga da hedai liligi misi.” Eso udiana da asili, be amo idinamasu ea bai ilia da hogoi helele hame dawa: i.
15 Ní ọjọ́ kẹrin, wọ́n wí fún ìyàwó Samsoni, pé, “Tan ọkọ rẹ kí ó lè ṣe àlàyé àlọ́ náà fún wa, bí bẹ́ẹ̀ kọ́ àwa yóò sun ìwọ àti ìdílé baba rẹ̀ ní iná. Tàbí ṣe o pè wá sí ibi àsè yìí láti sọ wá di òtòṣì tàbí kó wa lẹ́rú ni?”
Eso biyaduga ilia da Sa: masane idua ema amane sia: i, “Diguama ogogoma. E da ninima amo idinamasu ea bai ninima olelema: ne agoane hamoma. Be dia agoane hame hamosea, ninia da dia ada diasu amo laluga ulagili salimu, amola di gilisili gobele salimu. Dafawane! Ania da nini liligi wamolamusa: , ninima guiguda: misa: ne sia: i.”
16 Nígbà náà ni ìyàwó Samsoni ṣubú lé e láyà, ó sì sọkún ní iwájú rẹ̀ pé, “O kórìíra mi! O kò sì ní ìfẹ́ mi nítòótọ́, o pàlọ́ fún àwọn ènìyàn mi, ìwọ kò sì sọ ìtumọ̀ rẹ̀ fún mi.” “Èmi kò tí ì ṣe àlàyé rẹ̀ fún baba àti ìyá mi, báwo ni èmi ó ṣe sọ ìtumọ̀ rẹ̀ fún ọ.”
Amalalu, Sa: masane idua da ema digini asili, amane sia: i, “Di da nama hame asigisa. Di da nama higasa. Di da na dogolegei fi dunu amo idinamasu sia: adole ba: i. Be amo ea bai nama hame olelei.” Sa: masane da ema bu adole i, “Na da amo ea bai na ada amola ame elama hame olelei. Amaiba: le, na da abuli dima adole ima: bela: ?”
17 Fún gbogbo ọjọ́ méje tí wọ́n fi ṣe àsè náà ni ó fi sọkún, nítorí náà ní ọjọ́ keje ó sọ ìtumọ̀ àlọ́ fún un nítorí pé ó yọ ọ́ lẹ́nu ní ojoojúmọ́. Òun náà sì sọ ìtumọ̀ àlọ́ náà fún àwọn ènìyàn rẹ̀.
Amo lolo nasu eso fesuale amoga, Sa: masane idua da dinanawane ema adole ba: i. Be eso fesuale gala amoga, e da mae fisili sia: ga gegenabeba: le, Sa: masane da amo idinamasu ea bai ema olelei. Amalalu, e da Filisidini dunuma olelei.
18 Kí ó tó di àṣálẹ́ ọjọ́ keje àwọn ọkùnrin ìlú náà sọ fún un pé, “Kí ni ó dùn ju oyin lọ? Kí ni ó sì lágbára ju kìnnìún lọ?” Samsoni dá wọn lóhùn pé, “Bí kì í bá ṣe pé ẹ fi ọ̀dọ́ abo màlúù mi kọ ilẹ̀, ẹ̀yin kò bá tí mọ ìtumọ̀ sí àlọ́ mi.”
Amalalu, eso fesu ganodini, eso dabe gadenenoba, Filisidini dunu da Sa: masane amoma amane sia: i, “Ha: i manu eno da hani ea hedai hame baligisa. Amola eno liligi ea gasa da laione wa: me ea gasa hame baligisa.” Sa: masane da bu adole i, “Dilia da na uda ea hou amo ganodini hame hamonoba, amo hedesu sia: bai hame dawa: la: loba.”
19 Lẹ́yìn èyí, ẹ̀mí Olúwa bà lé e pẹ̀lú agbára. Ó lọ sí Aṣkeloni, ó pa ọgbọ̀n nínú àwọn ọkùnrin wọn, ó gba àwọn ohun ìní wọn, ó sì fi àwọn aṣọ wọn fún àwọn tí ó sọ ìtumọ̀ àlọ́ náà. Ó sì padà sí ilé baba rẹ̀ pẹ̀lú ìbínú ríru.
Amalalu, hedolowane e da Hina Gode Ea gasa bagade lai. E da A: siegelone moilaiga asili, dunu 30 agoane amo medole legei. E da amo dunu ilia abula gigisa: le sasali, dunu amo da idinamasu ea bai olelei, ilima i dagoi. Amalalu, e da ougiwane hamonanu hi diasuga asi.
20 Wọ́n sì fi ìyàwó Samsoni fún ẹlẹgbẹ́ rẹ̀, tí ó jẹ́ ọ̀rẹ́ tímọ́tímọ́ rẹ̀ nígbà ìgbéyàwó rẹ̀.
Amola fa: no, Filisidini a: fini amo Sa: masane ea lai, amo ea ada da bu dunu eno Sa: masane e uda gaguli lasu lolo nasu fidisu dunu amogili lama: ne i.

< Judges 14 >