< Judges 13 >
1 Àwọn ọmọ Israẹli sì túnṣe ohun tí ó burú ní ojú Olúwa, Olúwa sì fi wọ́n lé àwọn ará Filistini lọ́wọ́ fún ogójì ọdún.
Isala: ili dunu da bu Hina Godema wadela: le hamoi. Amaiba: le, E da ilima se iasu. Gode da Filisidini dunu fidibiba: le, ilia da Isala: ili fi ilima ode 40 amoga hinawane esalu.
2 Ọkùnrin ará Sora kan wà, orúkọ rẹ̀ a máa jẹ́ Manoa láti ẹ̀yà Dani. Aya rẹ̀ yàgàn kò sì bímọ.
Amogalu, dunu ea dio amo Manoua esalu, e da Soula moilai bai bagadega esalu. E da Da: ne fi dunu. Ea uda da mano mae lalewane, aligime esalu.
3 Angẹli Olúwa fi ara han obìnrin náà, ó sì wí fún un pé, “Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ìwọ yàgàn, ìwọ kò sì tí ì bímọ, ìwọ yóò lóyún, ìwọ yóò sì bí ọmọkùnrin kan.
Hina Gode Ea a: igele dunu da ema misini, amane sia: i, “Di da aligime esalu, be wali di da abula aguni, mano lalelegemu.
4 Báyìí rí i dájúdájú pé ìwọ kò mu wáìnì tàbí ọtí líle kankan àti pé ìwọ kò jẹ ohun aláìmọ́ kankan,
Dawa: ma! Waini hano, adini amola sema ha: i manu mae moma.
5 nítorí ìwọ yóò lóyún, ìwọ yóò sì bí ọmọkùnrin kan. Má ṣe fi abẹ kan orí rẹ̀, nítorí pé Nasiri, ẹni ìyàsọ́tọ̀ fún Ọlọ́run ni ọmọ náà yóò jẹ́ láti ọjọ́ ìbí rẹ̀. Òun ni yóò bẹ̀rẹ̀ ìdáǹdè àwọn ọmọ Israẹli kúrò ní ọwọ́ àwọn ará Filistini.”
Dia mano lalelegesea, ea dialuma hinabo mae damuma. Eso huluane yolesi dialoma. Bai e da eno dunuma afafane, Gode Ea ilegele momogili gagai Na: salaide dunu esalumu. E da Isala: ili dunuma gaga: su dunu ba: mu. Ilia da Filisidini ouligisu fisili, hahawane laloma: ne, e da hamomu.”
6 Nígbà náà ni obìnrin náà tọ ọkọ rẹ̀ lọ, o sì sọ fún un wí pé, “Ènìyàn Ọlọ́run kan tọ̀ mí wá. Ó jọ angẹli Ọlọ́run, ó ba ènìyàn lẹ́rù gidigidi. Èmi kò béèrè ibi tí ó ti wá, òun náà kò sì sọ orúkọ rẹ̀ fún mi.
Amalalu, amo uda da asili, egoa amoma amane sia: i, “Gode Ea hawa: hamosu dunu da nama misi. E da Gode Ea a: igele dunu, gasa bagade agoane ba: i. E da habidili misi, na da ema hame adole ba: i. Amola e da ea dio amo nama hame adole i.
7 Ṣùgbọ́n ó sọ fún mi wí pé, ‘Ìwọ yóò lóyún, ìwọ yóò sì bí ọmọkùnrin kan, fún ìdí èyí, má ṣe mu wáìnì tàbí àwọn ọtí líle mìíràn bẹ́ẹ̀ ni kí ìwọ má ṣe jẹ ohunkóhun tí í ṣe aláìmọ́, nítorí pé Nasiri Ọlọ́run ni ọmọ náà yóò jẹ́ láti ọjọ́ ìbí rẹ̀ títí di ọjọ́ ikú rẹ̀.’”
Be e da nama agoane olelei. Na da abula agui ba: mu, amola dunu mano lalelegemu. E da nama, na da waini hano amola adini mae moma: ne sia: i, amola sema ha: i manu mae nawane sia: i. Bai amo dunu mano lalelegemu da Godema i mano, e da ea esalebe eso huluane amoga momogili gagai Na: salaide dunu esalumu.”
8 Nígbà náà ni Manoa gbàdúrà sí Olúwa wí pé, “Háà Olúwa, èmi bẹ̀ ọ́, jẹ́ kí ènìyàn Ọlọ́run tí ìwọ rán sí wa padà tọ̀ wá wá láti kọ́ wa bí àwa yóò ti ṣe tọ́ ọmọ tí àwa yóò bí náà.”
Amalalu, Manoua da Godema sia: ne gadoi, amane, “Hina Gode na da Dima adole ba: sa. Dia hawa: hamosu dunu Di da asunasi, amo ania mano lalelegesea ani da adi hamoma: bela: , amo anima olema: ne, dia hawa: hamosu dunu bu asunasima.”
9 Ọlọ́run fetí sí ohùn Manoa, angẹli Ọlọ́run náà tún padà tọ obìnrin náà wá nígbà tí ó wà ní oko ṣùgbọ́n ọkọ rẹ̀ Manoa kò sí ní ọ̀dọ̀ rẹ̀.
Gode da Manoua ea adole ba: i defele hamoi dagoi. Manoua idua da ifabia ga esalu, amola a: igele dunu da ema misi. Be Manoua da amoga hame lelu.
10 Nítorí náà ni obìnrin náà ṣe yára lọ sọ fún ọkọ rẹ̀ pé, “Ọkùnrin tí ó fi ara hàn mí ní ọjọ́sí ti tún padà wá.”
Amaiba: le, uda da hehenane, ema amane sia: i, “Ba: la misa! Dunu da gasida nama misi, amo da nama bu misi dagoi.”
11 Manoa yára dìde, ó sì tẹ̀lé aya rẹ̀, nígbà tí ó dé ọ̀dọ̀ ọkùnrin náà ó ní, “Ǹjẹ́ ìwọ ni o bá obìnrin yìí sọ̀rọ̀?” Ọkùnrin náà dáhùn pé, “Èmi ni.”
Manoua da wa: legadole, idua asi fa: no bobogei. E da a: igele dunu ema amane sia: i, “Na uda amoma sia: dalu, amo dunu da dila: ?” A: igele da bu adole i, “Ma!”
12 Manoa bi ọkùnrin náà pé, “Nígbà tí ọ̀rọ̀ rẹ bá ṣẹ kí ni yóò jẹ́ ìlànà fún ìgbé ayé àti iṣẹ́ ọmọ náà?”
Amalalu, Manoua da amane sia: i, “Dia sia: i amo didibi ania ba: sea, amo dunu mano da adi hamoma: bela: ? Ea esalebe ahoanusu hou da haboda: i esaloma: bela: ?”
13 Angẹli Olúwa náà dáhùn wí pé, “Aya rẹ gbọdọ̀ ṣe gbogbo ohun tí mo ti sọ fún un
A: igele da bu adole i, “Dia uda da na sia: i huluane defele hamoma: mu.
14 kò gbọdọ̀ jẹ ohunkóhun tí ó bá ti inú èso àjàrà jáde wá, bẹ́ẹ̀ ni kò gbọdọ̀ mu wáìnì tàbí àwọn ọtí líle mìíràn tàbí jẹ ohunkóhun tí ó bá jẹ́ aláìmọ́. Ó ní láti ṣe ohun gbogbo tí mo ti pàṣẹ fún un.”
Waini efe fage ha: i manu liligi huluane mae moma: ne, na da sia: i. E da waini hano amola adini sema ha: i manu maedafa moma: ne, na sia: i. Na sia: i liligi huluanedafa, ea hamoma: ne sia: ma.”
15 Manoa sọ fún angẹli Olúwa náà pé, “Jọ̀wọ́ dára dúró títí àwa yóò fi pèsè ọ̀dọ́ ewúrẹ́ kan fún ọ.”
16 Angẹli Olúwa náà dá Manoa lóhùn pé, “Bí ẹ̀yin tilẹ̀ dá mi dúró, èmi kì yóò jẹ ọ̀kankan nínú oúnjẹ tí ẹ̀yin yóò pèsè. Ṣùgbọ́n tí ẹ̀yin bá fẹ́ ẹ pèsè ọrẹ ẹbọ sísun, kí ẹ sì fi rú ẹbọ sí Olúwa.” (Manoa kò mọ̀ pé angẹli Olúwa ní i ṣe.)
Manoua da amo dunu da Gode Ea a: igele dunu amo hame dawa: i. Amaiba: le, e da ema amane sia: i, “Wahadafa mae masa. Ania da goudi mano dima imunusa: , gobemu.” Be a: igele dunu da bu adole i, “Na da hame ahoasea, dia ha: i manu hame manu. Be di da goudi mano gobemusa: dawa: sea, defea, amo Hina Godema imunusa: gobele salima.”
17 Manoa sì béèrè lọ́wọ́ angẹli Olúwa náà pé, “Kí ni orúkọ rẹ, kí àwa bá à lè fi ọlá fún ọ nígbà tí ọ̀rọ̀ rẹ bá ṣẹ?”
Manoua da a: igele dunuma amane sia: i, “Dia dio anima adoma. Bai dia sia: da dafawaneyale ba: sea, ania da dia dio amoma nodomusa: adomu.”
18 Ṣùgbọ́n angẹli Olúwa náà dáhùn pé, “Èéṣe tí ìwọ ń béèrè orúkọ mi? Ìyanu ni, ó kọjá ìmọ̀.”
Be a: igele dunu da bu adole i, “Dia da abuli na dio dawa: musa: hanabela: Na dio da fofogadigisu bagade liligi.”
19 Lẹ́yìn náà ni Manoa mú ọ̀dọ́ ewúrẹ́, pẹ̀lú ẹbọ ọkà, ó sì fi rú ẹbọ lórí àpáta kan sí Olúwa. Nígbà tí Manoa àti ìyàwó dúró tí wọn ń wò Olúwa ṣe ohun ìyanu kan.
Amalalu, Manoua da goudi mano lale, amo amola gagoma gilisili oloda da: iya Hina Godema ima: ne, gobele sali. Amalalu, Manoua amola idua da balalebe lelu, Hina Gode da gasa bagade musa: hame ba: i hou hamoi.
20 Bí ẹ̀là ahọ́n iná ti là jáde láti ibi pẹpẹ ìrúbọ náà sí ọ̀run, angẹli Olúwa gòkè re ọ̀run láàrín ahọ́n iná náà. Nígbà tí wọ́n rí ìṣẹ̀lẹ̀ yìí, Manoa àti aya rẹ̀ wólẹ̀ wọ́n sì dojúbolẹ̀.
21 Nígbà tí angẹli Olúwa náà kò tún fi ara rẹ̀ han Manoa àti aya rẹ̀ mọ́, Manoa wá mọ̀ pé angẹli Olúwa ni.
Lalu gona: su da oloda amoga heda: lebe ba: loba, Manoua amola idua da agoane ba: i. Hina Gode Ea a: igele dunu da lalu gona: su amo ganodini Hebene diasuga heda: lebe ba: i. Amalalu, Manoua da amo dunu da Hina Gode Ea a: igele dunu dawa: iou. E amola ea uda da osoboga diasa: ili, ilia odagi da osoboga doaga: i. Ela da amo a: igele dunu bu hame ba: i.
22 Manoa sọ fún aya rẹ̀ pé, “Dájúdájú àwa yóò kú nítorí àwa ti fi ojú rí Ọlọ́run.”
Manoua da iduama amane sia: i, “Ania da dafawane bogomu galebe. Bai ania da Gode ba: i dagoi.”
23 Ṣùgbọ́n ìyàwó rẹ̀ dáhùn pé, “Bí Olúwa bá ní èrò àti pa wá kò bá tí gba ẹbọ sísun àti ọrẹ ọkà wa, tàbí fi gbogbo nǹkan wọ̀nyí hàn wá tó sọ nǹkan ìyanu yìí fún wa.”
Be ea uda da amane sia: i, “Hina Gode da ani medomu hanai ganiaba, E da ania gobele salasu hame lala: loba. Amola E da Ea adoi liligi amola hou anima hame olelela: loba.”
24 Obìnrin náà sì bí ọmọkùnrin kan, ó sì sọ orúkọ rẹ̀ ní Samsoni. Ọmọ náà dàgbà Olúwa sì bùkún un.
Uda da dunu mano lalelegei. E da ema Sa: masane dio asuli. Amo mano da asigilalu, amola Hina Gode da e hahawane dogolegelewane fidisu.
25 Ẹ̀mí Olúwa sì bẹ̀rẹ̀ sí ru sókè nígbà tí ó wà ní Mahane-Dani ní agbede-méjì Sora àti Eṣtaoli.
E da Da: ne ea fifilasu moilai amo ganodini esaloba (amo sogebi da Soula amola Esadoule dogoa dialu) amoga Hina Gode da Ea gasaga ema muni gasa bagade iasu.