< Judges 10 >

1 Lẹ́yìn ikú Abimeleki, ọkùnrin kan láti ẹ̀yà Isakari tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Tola ọmọ Pua, ọmọ Dodo, dìde láti gba Israẹli sílẹ̀. Ní Ṣamiri tí ó wà ní òkè Efraimu ni ó gbé.
Abimelege da bogoi dagoloba, Doula (Bua ea mano amola Doudou ea aowa) da Isala: ili dunu amo gaga: musa: misi. Doula da Isaga fi dunu galu. E da Sia: ime moilai bai bagade Ifala: ime agolo soge ganodini esalu.
2 Ó ṣe àkóso Israẹli ní ọdún mẹ́tàlélógún. Nígbà tí ó kú wọ́n sìn ín sí Ṣamiri.
E da Isala: ili dunu huluane ode 23 amanega ouligisu. Amanoba, e da bogole, Sia: ime moilai bai bagade amo ganodini uli dogone sali.
3 Jairi ti ẹ̀yà Gileadi ni ó dìde lẹ́yìn rẹ̀, ó ṣàkóso Israẹli ní ọdún méjìlélógún.
Doula da bogobeba: le, Gilia: de dunu ea dio amo Ya: ie, da Isala: ili fi ouligima: ne misi. E da Isala: ili dunu ode 22 amoga ouligisu.
4 Àwọn ọgbọ̀n ọmọ tí ó n gun ọgbọ̀n kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́. Wọ́n ṣe àkóso ọgbọ̀n ìlú ní Gileadi, tí a pe orúkọ wọn ní Hafoti-Jairi títí di òní.
Ea dunu mano 30 agoane esalu. Ilia da dougi 30 amo da: iya fila heda: su. Ilia da Gilia: de soge amo ganodini moilai bai bagade 30 agoane lai. Amo moilai bai bagade da wali amola da Ya: ie ea moilai ilia da sia: sa.
5 Nígbà tí Jairi kú wọ́n sin ín sí Kamoni.
Ya: ie da bogole, ilia da ea da: i hodo Ga: imone sogega uli dogone sali.
6 Àwọn ọmọ Israẹli sì túnṣe ohun tí ó burú lójú Olúwa. Wọ́n sin Baali àti Aṣtoreti àti àwọn òrìṣà Aramu, òrìṣà Sidoni, òrìṣà Moabu, òrìṣà àwọn ará Ammoni àti òrìṣà àwọn ará Filistini. Nítorí àwọn ará Israẹli kọ Olúwa sílẹ̀ tí wọn kò sì sìn ín mọ́,
Isala: ili dunu da Hina Godema bu wadela: le hamoi. Ilia da ogogosu ‘gode’ liligi amo Ba: ile amola A: sadade elama nodone sia: ne gadoi. Amola ilia da Silia, Saidone, Moua: be, A:mone amola Filisidia dunu fi ilia ogogosu ‘gode’ ilima nodone sia: ne gadoi. Ilia Hina Gode amo fisili, Ema hame nodone sia: ne gadoi.
7 ó bínú sí wọn, ó fi wọ́n sílẹ̀ fún àwọn ará Filistini àti Ammoni láti jẹ ẹ́ ní ìyà.
Amaiba: le, Hina Gode da Isala: ili dunu ilima ougi galu. E da Filisidini dunu amola A: mounaide dunu ili hasalima: ne, logo doasi dagoi.
8 Ní ọdún náà, wọ́n tú wọn ká wọ́n sì pọ́n wọn lójú. Fún ọdún méjìdínlógún ni wọ́n fi ni gbogbo àwọn ọmọ Israẹli tí ó wà ní ìlà-oòrùn odò Jordani ní ilẹ̀ àwọn ará Amori lára (èyí nì ní Gileadi).
Amo dunu da ode 18 amoga, Isala: ili dunu da A: moulaide soge Yodane Hano eso mabadili la: idi Gilia: de soge ganodini esalu, ilima gegene, se bagade iasu.
9 Àwọn ará Ammoni sì la odò Jordani kọjá láti bá Juda, Benjamini àti àwọn ará ilé Efraimu jagun: Israẹli sì dojúkọ ìpọ́njú tó lágbára.
Amo hou baligili, A:mounaide dunu da Yodane Hano degele, Yuda fi, Bediamini fi amola Ifala: ime fi ilima gegesu. Isala: ili dunu da se bagade nabasu.
10 Nígbà tí èyí ti ṣẹlẹ̀ àwọn ọmọ Israẹli ké pe Olúwa wí pé, “Àwa ti ṣẹ̀ sí ọ, nítorí pé àwa ti kọ Ọlọ́run wa sílẹ̀, àwa sì ń sin Baali.”
Amalalu, Isala: ili dunu da Hina Godema se nabawane wele sia: i. Ilia da amane sia: i, “Dafawane! Ninia da Dima wadela: le hamoi. Di da ninia Godedafa, be ninia da Di fisili, ogogosu Ba: ile ‘gode’ ilima nodone sia: ne gadosu.”
11 Olúwa sì dáhùn pé, “Ǹjẹ́ nígbà tí àwọn ará Ejibiti, Amori, Ammoni, Filistini,
Hina Gode da ilia wele sia: i nabi. E da ilima bu adole i, amane, “Musa: , Idibidi dunu, A:moulaide dunu, A:mounaide dunu, Filisidini dunu,
12 àwọn ará Sidoni, Amaleki pẹ̀lú Maoni ni yín lára, tí ẹ sì ké pè mí fún ìrànlọ́wọ́, ǹjẹ́ èmi kò gbà yín sílẹ̀ kúrò ní ọwọ́ wọn?
Saidounia dunu, Ama: legaide dunu amola Ma: ionaide dunu da musa: dilima se bagade iasu. Dilia da Nama wele sia: beba: le, Na da hedolo dili fidila misi amola ili dili mae hasalasima: ne, dili gaga: i.
13 Síbẹ̀síbẹ̀ ẹ̀yin kọ̀ mí sílẹ̀ láti sin àwọn ọlọ́run mìíràn, torí ìdí èyí, èmi kì yóò sì tún gbà yín mọ́.
Be dilia da amo hou mae dawa: le, Na fisili, ogogosu ‘gode’ liligi ilima nodone sia: ne gadosu. Amaiba: le, Na da dili bu hame gaga: mu.
14 Ẹ lọ kí ẹ sì ké pe àwọn òrìṣà tí ẹ̀yin ti yàn fún ara yín. Jẹ́ kí wọn gbà yín sílẹ̀ ní àsìkò ìpọ́njú yín!”
Dilia ogogosu ‘gode’ liligi ilima fa: no bobogemu hanaiba: le, defea, ilima wele sia: ma. Dilia se nabasea, ilia da dili gaga: mu da defea.”
15 Àwọn ọmọ Israẹli sì dá Olúwa lóhùn pé, “Àwa ti ṣẹ̀, ṣe ohun tí ó bá fẹ́ pẹ̀lú wa, ṣùgbọ́n, jọ̀wọ́ gbà wá sílẹ̀ náání àsìkò yìí.”
Be Isala: ili dunu da Hina Godema amane sia: i, “Dafawane! Ninia da wadela: le hamoi dagoi. Dia hanaiga, ninima hamoma. Be wali eso nini gaga: ma.”
16 Nígbà náà ni wọ́n kó gbogbo ọlọ́run àjèjì tí ó wà láàrín wọn kúrò wọ́n sì sin Olúwa nìkan, ọkàn rẹ̀ kò sì le gbàgbé ìrora Israẹli mọ́.
Amalalu, Isala: ili dunu da ga fi ilia ‘gode’ liligi ilia lai, amo fadegale, Hina Godema fawane fa: no bobogei. Amola Hina Gode da ilia se nabasu ba: beba: le, ilima asigiba: le se nabi.
17 Nígbà tí àwọn ará Ammoni kógun jọ ní Gileadi láti bá Israẹli jà, àwọn ọmọ Israẹli gbárajọpọ̀, wọ́n sì tẹ̀dó ogun ní Mispa.
Amalalu, A:mounaide dadi gagui gilisisu da ilima gegemusa: misini, Gilia: de sogega fi dialu. Isala: ili dunu huluane da gilisili, Misiba moilai Gilia: de soge ganodini amoga, ilia awalia ahoasu moilai gagui.
18 Àwọn ìjòyè: aṣíwájú àwọn ará Gileadi wí fún ará wọn pé, “Ẹnikẹ́ni tí yóò kọ́ ṣígun si àwọn ará Ammoni ni yóò jẹ́ orí fún gbogbo àwọn tí ń gbé ní Gileadi.”
Amogawi Isala: ili fi ouligisu dunu huluane da gilisili sia: dasu, amane, “Ninia A: mounaide dunu ilima gegesea, nowa da ninima bisili ilibi gagui hamoma: bela: ? Nowa dunu ninia da ilibi gaguma: ne ilegesea, e da Gilia: de soge ganodini esalebe dunu huluane ilima ouligisu ba: mu.”

< Judges 10 >