< Joshua 9 >

1 Nísinsin yìí, nígbà tí gbogbo ọba tó wà ní ìwọ̀-oòrùn Jordani gbọ́ nípa nǹkan wọ̀nyí, àwọn náà tí ó wà ní orí òkè àti àwọn tí ó wà ní ẹsẹ̀ òkè, àti gbogbo àwọn tí ó wà ní agbègbè Òkun Ńlá títí ó fi dé Lebanoni (àwọn ọba Hiti, Amori, Kenaani, Peresi, Hifi àti Jebusi)
Yodane Hano eso dabe la: idi hina bagade dunu huluane da Isala: ili dunu ilia gasa bagade hasalasu hou nabi dagoi. Amo hou ilia da goumi soge ganodini, umi soge Medidela: inia Wayabo Bagade bega: amola soge gano asili Lebanone sogega doaga: i, amo esalebe dunu huluane da Isala: ili dunu ilia hou nabi. Amo hina bagade dunu ilia fi da Hidaide, A:moulaide, Ga: ina: naide, Belesaide, Haifaide amola Yebiusaide.
2 wọ́n sì kó ara wọn jọ láti bá Joṣua àti Israẹli jagun.
Amo hina bagade dunu da gilisili, Yosiua amola Isala: ili dunu ilima gegemusa: gilisi.
3 Ṣùgbọ́n nígbà tí àwọn ènìyàn Gibeoni gbọ́ ohun tí Joṣua ṣe sí Jeriko àti Ai,
Be Gibionaide dunu (ilia da Haifaide fi dunu) ilia da Yosiua ea hou amo Yeligou amola A: iai amoma hamoi nababeba: le,
4 wọ́n dá ọgbọ́n ẹ̀tàn. Wọ́n lọ gẹ́gẹ́ bí aṣojú tí kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ wọn kún fún ẹrù tí a fi àwọn àpò tó ti gbó dì, àti àwọn awọ ọtí wáìnì tó ti gbó tí a tún rán.
ilia da Yosiuama ogogomusa: dawa: i galu. Ilia da ha: i manu lale, ilia dougi da: iya esa wadela: lesi dagoi amola waini gadofo gadelale nodomei ligisi.
5 Àwọn ọkùnrin náà sì wọ bàtà àti aṣọ tí ó ti gbó. Gbogbo oúnjẹ tí wọ́n pèsè fún ara wọn sì bu.
Ilia da abula wadela: i amola hea emo salasu wadela: iba: le nodomei gasisali.
6 Wọ́n sì tọ Joṣua lọ ní ibùdó ní Gilgali, wọ́n sì sọ fún òun àti àwọn ọkùnrin Israẹli pé, “Ìlú òkèrè ní àwọn ti wá, ẹ ṣe àdéhùn àlàáfíà pẹ̀lú wa.”
Amalalu, ilia da Isala: ili abula diasu gilisisu Giliga: le amoga gala amoga asili, Yosiua amola Isala: ili dunu ilima amane sia: i, “Ninia da soge sedagaga misi. Ninia da dilima gousa: su hamomu galebe.”
7 Àwọn ọkùnrin Israẹli sọ fún àwọn ará Hifi pé, “Ṣùgbọ́n bóyá tòsí wa ni ẹ ń gbé. Báwo ni a ó ṣe lè ṣe àdéhùn pẹ̀lú yín?”
Be Isala: ili dunu da amane sia: i, “Ninia da dilima gousa: su abuliga hamoma: bela: ? Amabela: ? Dilia da gadenene esalabala?”
8 “Ìránṣẹ́ rẹ ní àwa í ṣe.” Wọ́n sọ fún Joṣua. Ṣùgbọ́n Joṣua béèrè, “Ta ni yín àti pé níbo ni ẹ̀yin ti wá?”
Ilia da Yosiuama amane sia: i, “Ninia da dia hawa: hamosu dunu esala.” Yosiua da ilima amane adole ba: i, “Dilia da nowala: ? Dilia da habidili misibala: ?”
9 Wọ́n sì dáhùn pé, “Ní ilẹ̀ òkèèrè ní àwọn ìránṣẹ́ rẹ tí wá, nítorí orúkọ Olúwa Ọlọ́run rẹ. Nítorí tí àwa ti gbọ́ òkìkí rẹ àti ohun gbogbo tí ó ti ṣe ní Ejibiti,
Amalalu, ilia da amo sia: ema olelei, “Ninia da dilia Hina Gode Ea hou nababeba: le, soge sedade amoga misi dagoi. Ninia da Ea hou Idibidi soge ganodini hamoi,
10 àti ohun gbogbo tí ó ti ṣe sí ọba àwọn Amori méjèèje tí ń bẹ ní òkè Jordani, sí Sihoni ọba Heṣboni, àti Ogu ọba Baṣani, tí wọ́n jẹ ọba ní Aṣtarotu.
amola E da A: moulaide hina bagade aduna Yodane Hano eso mabadi la: idiga esalu (amo da Hesiabone hina bagade amo ea dio Saihone amola Ba: isia: ne hina bagade Asiadalode moilai bai bagadega esalu amo ea dio Oge) Hina Gode da elama hamoi, amo ninia nabi.
11 Àwọn àgbàgbà wa àti gbogbo àwọn tí ń gbé ìlú wa sọ fún wa pé, ‘Ẹ mú oúnjẹ lọ́wọ́ fún ìrìnàjò yín, ẹ lọ pàdé wọn, kí ẹ sì sọ fún wọn pé, “Àwa ni ìránṣẹ́ yín, ẹ dá àdéhùn pẹ̀lú wa.”’
Ninia ouligisu dunu amola fi dunu huluane ninia soge ganodini esala da nini ha: i manu momagele, dima gousa: musa: masa: ne sia: i. Ilia da nini da dima hawa: hamomusa: sia: ne, dilima gousa: su hamoma: ne sia: i.
12 Gbígbóná ní a mú oúnjẹ wa wá, nígbà tí a dì í ní ilé ní ọjọ́ tí à ń bọ̀ wá sọ́dọ̀ yín. Ṣùgbọ́n ẹ wò ó bí ó ṣe gbẹ àti bí ó sì ṣe bu nísinsin yìí.
Ninia agi ga: gi ba: ma! Ninia da dilima gousa: musa: nini soge fisili, amo agi ga: gi da gugumi ba: i. Ba: ma! Wali amo da hafoga: i amola moloba: fi dagoi.
13 Àti ìgò wáìnì wọ̀nyí, tí àwa rọ kún tuntun ni, ṣùgbọ́n ẹ wò ó bí wọ́n ti sán. Aṣọ àti bàtà wa ni ó sì ti gbó nítorí ìrìnàjò ọ̀nà jíjìn.”
Ninia da waini amo waini gadofo ganodini sogasalaloba, waini gadofo da gaheabolo ba: i. Be wali ilia da gadelai. Ninia sedagaga misiba: le ninia abula amola emo salasu da hea hamoi dagoi.”
14 Àwọn ọkùnrin Israẹli sì yẹ oúnjẹ wọn wò, wọn kò sì wádìí ní ọwọ́ Olúwa.
Isala: ili dunu da ilima ha: i manu lai, be ilia hou dawa: ma: ne Hina Godema hame adole ba: i.
15 Nígbà náà ni Joṣua ṣe àdéhùn àlàáfíà pẹ̀lú wọn láti dá wọn sí, àti àwọn olórí ìjọ ènìyàn fi ọwọ́ sí àdéhùn náà nípa ṣíṣe ìbúra.
Yosiua da hahawane gousa: su ilima hamoi amola amo dunu hame medole legei. Isala: ili ouligisu dunu da dafawane amo gousa: su hame fisima: ne ilegele sia: i.
16 Ní ẹ̀yìn ọjọ́ mẹ́ta tí wọ́n ti ṣe àdéhùn pẹ̀lú àwọn ará Gibeoni, àwọn ọmọ Israẹli gbọ́ pé aládùúgbò wọn ni wọ́n, tí ń gbé ní tòsí wọn.
Be eso udiana asili, Isala: ili dunu da Gibionaide dunu da gadenene fi amo nabi dagoi.
17 Bẹ́ẹ̀ ní àwọn ọmọ Israẹli jáde, wọ́n sì dé ìlú wọn ní ọjọ́ kẹta: Gibeoni, Kefira, Beeroti àti Kiriati-Jearimu.
Amaiba: le, Isala: ili dunu da asili, eso udiana asili ilia esalebe moilale bai bagadega doaga: i. Amo moilale gagai bai bagade ilia dio da Gibione, Gifaila, Bialode amola Gilia: de Yialimi.
18 Ṣùgbọ́n àwọn ọmọ Israẹli kò si kọlù wọ́n, nítorí pé àwọn àgbàgbà ìjọ ènìyàn ti búra fún wọn ní orúkọ Olúwa Ọlọ́run Israẹli. Gbogbo ènìyàn sì kùn sí àwọn àgbàgbà náà,
Be Isala: ili ouligisu dunu da Hina Gode Ea Dioba: le amo dunu hame medomu ilegele sia: i dagoiba: le, ilia da amo dunu medole legemu hamedei ba: i. Isala: ili dunu huluane da ilia ouligisu dunuma sia: ga gegei.
19 ṣùgbọ́n gbogbo àwọn olórí dáhùn pé, “Àwa ti búra fún wọn ní orúkọ Olúwa Ọlọ́run Israẹli, a kò sì lè fọwọ́ kàn wọ́n nísinsin yìí.
Be Isala: ili ouligisu dunu da bu adole i, “Ninia da Isala: ili Hina Gode Ea Dioba: le amo dunuma sia: i dagoiba: le, ninia da ilima se imunu hamedei.
20 Èyí ní àwa yóò ṣe sí wọn, àwa yóò dá wọn sí, kí ìbínú kí ó má ba à wá sórí wa, nítorí ìbúra tí a búra fún wọn.”
Ninia sia: i dagoiba: le, amo dunu hame medole legemu. Amai hame galea, Gode da ninima se imunu.
21 Wọ́n tẹ̀síwájú, “Ẹ dá wọn sí, ṣùgbọ́n ẹ jẹ́ kí wọn jẹ́ gégigégi àti apọnmi fún gbogbo ìlú.” Àwọn àgbàgbà náà sì mú ìlérí wọn ṣẹ fún wọn.
Ilia da esalumu da defea. Be ilia da ninia lalu habei amola hano nasu gaguli misunu.”
22 Nígbà náà ni Joṣua pe àwọn ọmọ Gibeoni jọ pé, “Èéṣe tí ẹ̀yin fi tàn wá wí pe, ‘Àwa gbé ní ibi tí ó jìnnà sí yín,’ nígbà tí ó jẹ́ pé tòsí wa ní ẹ̀yin ń gbé?
Yosiua da Isala: ili dunuma ilia da Gibionaide dunu ema oule misa: ne sia: i. E da ilima amane adole ba: i, “Dilia da abuliba: le ninima ogogobela: ? Dilia gadenene esalebeba: le, abuliba: le sedagaga esala sia: bela: ?
23 Nísinsin yìí, ẹ̀yin di ẹni ègún, ẹ̀yin kò sì ní kúrò ní gégigégi àti apọnmi fún ilé Ọlọ́run mi.”
Dilia da agoane hamoiba: le, Gode da dilima ougi, se imunu. Dilia fi da mae fisili, eso huluane udigili hawa: hamosu dunu esalumu. Dilia da na Gode Ea modale ligiagai diasuga lalu habele amola hano dili gaguli misunu.
24 Wọ́n sì dá Joṣua lóhùn pé, “Nítorí tí a sọ fún àwọn ìránṣẹ́ rẹ dájúṣáká bí Olúwa Ọlọ́run rẹ ti pàṣẹ fún Mose ìránṣẹ́ rẹ̀, láti fún yín ní gbogbo ilẹ̀ náà, kí ó sì pa gbogbo olùgbé ilẹ̀ náà run kúrò ní iwájú yín. Nítorí náà, àwa bẹ̀rù ẹ̀mí wa nítorí yín, èyí sì ni ìdí tí a fi ṣe bẹ́ẹ̀.
Ilia da bu adole i, “Ninia da sia: amo dilia Hina Gode da Ea hawa: hamosu dunu Mousese ema soge huluane lama amola amo ganodini fi dunu huluane medole legema sia: i dagoi, amo nababeba: le ninia da agoane hamoi. Ninia da dilima bagade beda: iba: le amola nini da bogosa: besa: le amo ogogosu hamoi.
25 Nísinsin yìí, àwa wà ní ọwọ́ yín. Ohunkóhun tí ẹ bá rò pé ó yẹ ó si tọ́ lójú yín ní kí ẹ fi wá ṣe.”
Be wali ninia da dia lobo ganodini gagui gala. Dia asigi dawa: su defele ninima hamoma.”
26 Bẹ́ẹ̀ ní Joṣua sì gbà wọ́n là kúrò ní ọwọ́ àwọn ọmọ Israẹli. Wọn kò sì pa wọ́n.
Amaiba: le Yosiua da agoane hamoi. E da Gibionaide dunu gaga: i amola Isala: ili dunuma amo mae medoma: ne sia: i.
27 Ní ọjọ́ náà ni ó sọ àwọn Gibeoni di aṣẹ́gi àti apọnmi fún àwọn ará ìlú àti fún pẹpẹ Olúwa ní ibi tí Olúwa yóò yàn. Báyìí ni wọ́n wà títí di òní yìí.
Be e da ili da udigili hawa: hamoma: ne sia: i. Ilia da Isala: ili dunuma amola Hina Gode Ea oloda amoga lalu habele, amola hano dili gaguli misi. Amola mae fisili hamonanu, ilia da wali eso amola Hina Godema nodomusa: sogebi E da ilegei, amoga ilia da amo udigili hawa: hamonana.

< Joshua 9 >