< Joshua 7 >

1 Ṣùgbọ́n àwọn ará Israẹli ṣe àìṣòótọ́ nípa ohun ìyàsọ́tọ̀, Akani ọmọ Karmi, ọmọ Sabdi, ọmọ Sera, ẹ̀yà Juda, mú nínú wọn. Bẹ́ẹ̀ ni ìbínú Olúwa ru sí àwọn ará Israẹli.
Fe nandilatse amo raha navikeo o ana’ Israeleo; amy te nandrambe raha navike t’i Akane, ana’i Karmý, ana’ i Zabdý, ana’i Zerake, fifokoa’ Iehodà; vaho nisolebatse amo ana’ Israeleo ty haviñera’ Iehovà.
2 Joṣua rán àwọn ọkùnrin láti Jeriko lọ sí Ai, tí ó súnmọ́ Beti-Afeni ní ìlà-oòrùn Beteli, ó sì sọ fún wọn pé, “Ẹ gòkè lọ kí ẹ sì ṣe ayọ́lẹ̀wò.” Bẹ́ẹ̀ ni àwọn arákùnrin náà lọ, wọ́n sì yọ́ Ai wò.
Nañirake ondaty boake Ieriko mb’amy Ày marine i Bete-avene, atiñana’ i Betele mb’eo t’Iehosoa, le hoe ty nanoe’e: Akia, tampono i taney. Aa le nionjoñe mb’eo ondatio nanampoñe i Ày.
3 Nígbà tí wọ́n padà sí ọ̀dọ̀ Joṣua, wọ́n wí pé, “Kì í ṣe gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ni láti gòkè lọ bá Ai jà. Rán ẹgbẹ̀rún méjì tàbí ẹgbẹ̀rún mẹ́ta ọkùnrin láti gbà á, kí ó má ṣe dá gbogbo àwọn ènìyàn ní agara, nítorí ìba ọkùnrin díẹ̀ ní ó wà níbẹ̀.”
Ie nibalike mb’amy Iehosoa mb’eo le nitalily ty hoe: Ko ampionjoneñe mb’eo iaby ondatio; fe añiraho ondaty telo arivo ndra ro’ arivo hionjoñe mb’eo handafa i Ày; ko votsora’o hifanehake mb’eo i maro iabiy, amy t’ie tsy ampeampe.
4 Bẹ́ẹ̀ ní àwọn bí ẹgbẹ̀rún mẹ́ta ọkùnrin lọ; ṣùgbọ́n àwọn ọkùnrin Ai lé wọn sá.
Va’e lahilahy telo-arivo amy màroy ty nionjomb’eo; f’ie nitriban-day añatrefa’ ondati’ i Àio,
5 Àwọn ènìyàn Ai sì pa àwọn bí mẹ́rìndínlógójì nínú wọn. Wọ́n sì ń lépa àwọn ará Israẹli láti ibodè ìlú títí dé Ṣebarimu, wọ́n sì pa àwọn tí ń sọ̀kalẹ̀. Àyà àwọn ènìyàn náà sì já, ọkàn wọn sì pami.
naho nañohofa’ ondati’ i Àio loza t’indaty telopolo eneñ’ amby; le hinorida’e boak’amy lalam-beiy pake Sebarime añe, naho linafa’ iareo amy fizotso­añey mb’ eo vaho nalorè aman’ arofo ondatio, nitranake hoe rano.
6 Joṣua sì fa aṣọ rẹ̀ ya, ó sì dojúbolẹ̀ níwájú àpótí ẹ̀rí Olúwa títí di àṣálẹ́. Àwọn àgbà Israẹli sì ṣe bákan náà, wọ́n ku eruku sí orí wọn.
Rinia’ Iehosoa i saro’ey naho nibabok’ an-tane an-dahara’e añatrefa’ i vatam-pañina’ ­Iehovày ampara’ te haleñe, ie naho o androanavi’ ­Israeleo songa nampibobò deboke añam­bone’e.
7 Joṣua sì wí pé, “Háà, Olúwa Olódùmarè, nítorí kín ni ìwọ ṣe mú àwọn ènìyàn yìí kọjá Jordani, láti fi wọ́n lé àwọn ará Amori lọ́wọ́, láti pa wọn run? Àwa ìbá mọ̀ kí a dúró ní òdìkejì Jordani?
Le hoe t’Ieho­soa: Hoke! ry Rañandria Iehovà, aa vaho akore ty nampi­tsaha’o Iardeney ondaty retoañe hanesea’o am-pità’ o nte-Amoreo, hampihomaha’o anay? Hamake t’ie nilesa naho nitobok’ alafe’ Iardeney añe!
8 Olúwa, kín ni èmi yóò sọ nísinsin yìí tí Israẹli sì ti sá níwájú ọ̀tá a rẹ̀?
O Rañandria, ino ty ho asako, kanao niambohoa’ Israele o rafelahi’eo!
9 Àwọn Kenaani àti àwọn ènìyàn ìlú tí ó kù náà yóò gbọ́ èyí, wọn yóò sì yí wa ká, wọn yóò sì ké orúkọ wa kúrò ní ayé. Kí ni ìwọ ó ha ṣe fún orúkọ ńlá à rẹ?”
Ie maha­janjiñe izay o nte-Kanàneo naho o hene mpimoneñe an-tane atoio, le hiarise­ho anay, vaho hapitso’ iareo an-tane atoy ty tahina’ay, le hatao’o akore i Tahina’o jabahinakey?
10 Olúwa sì sọ fún Joṣua pé, “Dìde! Kín ni ìwọ ń ṣe tí ó fi dojúbolẹ̀?
Le hoe t’Iehovà am’ Iehosoa: Miongaha, ino ty iba­boha’o an-dahara’o?
11 Israẹli ti ṣẹ̀, wọ́n sì ti ba májẹ̀mú mi jẹ́, èyí tí mo pàṣẹ fún wọn pé kí wọn pamọ́. Wọ́n ti mú nínú ohun ìyàsọ́tọ̀, wọ́n ti jí, wọ́n pa irọ́, wọ́n ti fi wọ́n sí ara ohun ìní wọn.
Toe nanao hakeo t’Israele; nilila­re’ iareo i fañinako nandiliako am’iareoy; nangalake amo raha navikeo; naho nampikametse naho nañetake vaho napoke amo harao’eo.
12 Ìdí nì èyí tí àwọn ará Israẹli kò fi lè dúró níwájú àwọn ọ̀tá wọn; wọ́n yí ẹ̀yìn wọn padà, wọ́n sì sálọ níwájú ọ̀tá a wọn nítorí pé àwọn gan an ti di ẹni ìparun. Èmi kì yóò wà pẹ̀lú u yín mọ́, bí kò ṣe pé ẹ̀yin pa ohun ìyàsọ́tọ̀ run kúrò ní àárín yín.
Aa le tsy nahafitroatse añatrefan-dra­felahi’e o ana’ Israeleo; niambohoa’ iareo o rafe­lahi’eo amy t’ie ninjare fokom-patse; tsy hindre ama’ areo iraho naho tsy mongore’ areo hey o nozoñeñe ama’ areoo.
13 “Lọ, ya àwọn ènìyàn náà sí mímọ́. Sọ fún wọn pé, ‘Ẹ ya ara yín sí mímọ́ fún ọ̀la, nítorí báyìí ni Olúwa, Ọlọ́run Israẹli wí, ohun ìyàsọ́tọ̀ kan ń bẹ ní àárín yín, Israẹli. Ẹ̀yin kì yóò lè dúró níwájú àwọn ọ̀tá a yín títí ẹ̀yin yóò fi mú kúrò.
Miongaha, ampiavaho ondatio, ano ty hoe: Miefera ho ami’ty maray; fa hoe ty tsara’ Iehovà Andrianañahare’ Israele: Aman’ onjitse ty añivo’o ao, ry Israele; tsy mahafijohañe añatrefa’ o rafelahi’oo irehe ampara’ te akareñe ama’ areo hey i natokañey.
14 “‘Ní òwúrọ̀, kí ẹ mú ará yín wá síwájú ní ẹ̀yà kọ̀ọ̀kan. Ẹ̀yà tí Olúwa bá mú yóò wá sí iwájú ní agbo ilé kọ̀ọ̀kan, agbo ilé tí Olúwa bá mú yóò wá sí iwájú ní ìdílé kọ̀ọ̀kan, ìdílé tí Olúwa bá sì mú yóò wá sí iwájú ní ẹni kọ̀ọ̀kan.
Aa ie marain­dray, miheova mb’eo am-pifokoañe; vaho ze fifokoa rambese’ Iehovà ro hañarine an-kasavereña’e; le ty hasavereñañe edrè’ Iehovà ro hañarine mb’eo ki-anjom­ba’e; le ty anjomba edrè’ Iehovà ro hitotoke ki’ ondaty.
15 Ẹnikẹ́ni tí a bá ká mọ́ pẹ̀lú ohun ìyàsọ́tọ̀ náà, a ó fi iná pa á run, pẹ̀lú gbogbo ohun tí ó ní. Ó ti ba májẹ̀mú Olúwa jẹ́, ó sì ti ṣe nǹkan ìtìjú ní Israẹli!’”
Ie amy zay, ho forototoeñe añ’afo ao ty nandrambe o raha navikeo rekets’ o fanaña’e iabio; amy te nililare’e ty fañina’ Iehovà, vaho nanao ha­tsivokarañe e Israele ao.
16 Ní kùtùkùtù òwúrọ̀ ọjọ́ kejì, Joṣua mú Israẹli wá síwájú ní ẹ̀yà kọ̀ọ̀kan, a sì mú ẹ̀yà Juda.
Aa le nañaleñàleñe amy maraiñey t’Iehosoa vaho nampitotohe’e t’Israele am-pifo­koa’e le nivoa ty fifokoa’ Iehoda.
17 Àwọn agbo ilé e Juda wá sí iwájú, ó sì mú agbo ilé Sera. Ó sì mú agbo ilé Sera wá síwájú ní ìdílé kọ̀ọ̀kan, a sì mú ìdílé Sabdi.
Nam­pi­totohe’e ty fifokoa’ Iehoda, le voa ty hasavereña’ i Zerake; nampi­totohe’e ty hasavereña’ i Zerake, lahilahy an-dahilahy le voa ty Zabdý.
18 Joṣua sì mú ìdílé Simri wá síwájú ní ọkùnrin kọ̀ọ̀kan, a sì mú Akani ọmọ Karmi, ọmọ Sabdi, ọmọ Sera ti ẹ̀yà Juda.
Nampi­totohe’e ki’ ondaty ki’ondaty i an­jomba’ey le voa t’i Akane, ana’ i Karmi, ana’ i Zabdy, ana’ i Ze­rake, fifokoa’ Iehoda.
19 Nígbà náà ní Joṣua sọ fún Akani pé, “Ọmọ mi fi ògo fún Olúwa, Ọlọ́run Israẹli, kí o sì fi ìyìn fún un. Sọ fún mi ohun tí ìwọ ti ṣe, má ṣe fi pamọ́ fún mi.”
Aa le hoe t’Iehosoa amy Akane, O anako, ehe toloro engeñe t’Iehovà Andrianañahare’ Israele, vaho andriaño; atalilio ahy henaneo i nanoe’oy; le ko aetake.
20 Akani sì dáhùn pé, “Òtítọ́ ni! Mo ti ṣẹ̀ sí Olúwa, Ọlọ́run Israẹli. Nǹkan tí mo ṣe nìyìí,
Le hoe ty natoi’ i Akane am’ Iehosoa: Toe nandilatse am’ Iehovà Andrianañahare’ Israele iraho vaho zao naho zao ty nanoeko.
21 nígbà tí mo rí ẹ̀wù Babeli kan tí ó dára nínú ìkógun, àti igba ṣékélì fàdákà àti odindi wúrà olóṣùnwọ́n àádọ́ta ṣékélì, mo ṣe ojúkòkòrò wọn mo sì mú wọn. Mo fi wọ́n pamọ́ ní abẹ́ àgọ́ mi àti fàdákà ní abẹ́ rẹ̀.”
Naho nitreako amo fikopahañeo ty sarimbo soa boake Sinare naho ty volafoty sekele roanjato, naho ty tseram-bolamena milan­ja sekele limampolo, le nihañeko, naho rinambeko; vaho ingo, mikafitse an-tane añivon-kibohoko ao, ambane ao i volafotiy.
22 Bẹ́ẹ̀ ni Joṣua ran àwọn òjíṣẹ́, wọ́n sì sáré wọ inú àgọ́ náà, ó sì wà níbẹ̀, a sì fi pamọ́ nínú àgọ́ ọ rẹ̀, àti fàdákà ní abẹ́ ẹ rẹ̀.
Aa le nampañitrike irake t’Ie­hosoa, naho nilay mb’ amy kibohotsey iereo, le ingo t’ie nikafitse an-kiboho’e ao, vaho ambane’e ao i volafotiy.
23 Wọ́n sì mú àwọn nǹkan náà jáde láti inú àgọ́ rẹ̀, wọ́n mú wọn wá fún Joṣua àti gbogbo àwọn ọmọ Israẹli, wọ́n sì fi wọ́n lélẹ̀ níwájú Olúwa.
Rinambe’ iereo boak’ an-kibohotse ao izay le nendese’e mb’ amy Iehosoa, naho mb’amo hene ana’ Israeleo mb’eo vaho napo’ iereo añatrefa’ Iehovà.
24 Nígbà náà ni Joṣua pẹ̀lú gbogbo Israẹli, mú Akani ọmọ Sera, fàdákà, ẹ̀wù àti wúrà tí a dà, àwọn ọmọ rẹ̀ ọkùnrin àti obìnrin, màlúù rẹ̀, kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ àti àgùntàn àgọ́ rẹ̀ àti gbogbo ohun tí ó ni, wọ́n sì kó wọn lọ sí ibi àfonífojì Akori.
Rinambe’ Iehosoa naho Israele iaby t’i Akane ana’ i Ze­rake naho i volafotiy, i sarimboy naho i tseram-bolamenay naho o ana-dahi’eo, o anak’ ampela’eo naho o añombe’eo naho o borìke’eo naho o añondri’eo naho i kiboho’ey naho ze ama’e iaby; le nampionjone’ iereo mb’ am-ba­vatane’ Akore mb’eo.
25 Joṣua sì wí pé, “Èéṣe tí ìwọ mú wàhálà yìí wá sí orí wa? Olúwa yóò mú ìpọ́njú wá sí orí ìwọ náà lónìí.” Nígbà náà ni gbogbo Israẹli sọ ọ́ ní òkúta pa, lẹ́yìn ìgbà tí wọ́n sọ àwọn tókù ní òkúta pa tán, wọ́n sì jó wọn níná.
Le hoe t’Iehosoa: Ino ty nanolora’o sotry anay? Iehovà ty hanolo-sotry ama’o te anito. Aa le nametsaha’ Israele vato, naho namorototo iareo an’ afo vaho nametsa-bato ama’e.
26 Wọ́n sì kó òkìtì òkúta ńlá lé Akani lórí títí di òní yìí. Nígbà náà ní Olúwa sì yí ìbínú gbígbóná rẹ̀ padà. Nítorí náà ni a ṣe ń pe orúkọ ibẹ̀ ní àfonífojì Akori láti ìgbà náà.
Nampitoabora’ iareo votrim-bato jabajaba ty ambone’ iereo, ze mbe eo henaneo, le nitolik’ amy havi­ñera’ey t’Iehovà. Aa le natao Vavatane’ i Akore ty añara’ i toetsey, pake henane.

< Joshua 7 >