< Joshua 7 >
1 Ṣùgbọ́n àwọn ará Israẹli ṣe àìṣòótọ́ nípa ohun ìyàsọ́tọ̀, Akani ọmọ Karmi, ọmọ Sabdi, ọmọ Sera, ẹ̀yà Juda, mú nínú wọn. Bẹ́ẹ̀ ni ìbínú Olúwa ru sí àwọn ará Israẹli.
Tedae Israel ca rhoek te yaehtaboeih dongah boekoeknah la boe a koek uh. Judah koca khuikah Zerah kah a ca Zabdi ko Karmee capa Akhan loh yaehtaboeih la aka om te a loh. Te dongah BOEIPA kah a thintoek loh Israel ca rhoek taengah sai.
2 Joṣua rán àwọn ọkùnrin láti Jeriko lọ sí Ai, tí ó súnmọ́ Beti-Afeni ní ìlà-oòrùn Beteli, ó sì sọ fún wọn pé, “Ẹ gòkè lọ kí ẹ sì ṣe ayọ́lẹ̀wò.” Bẹ́ẹ̀ ni àwọn arákùnrin náà lọ, wọ́n sì yọ́ Ai wò.
Te vaengah Jerikho lamkah hlang rhoek te Bethel khothoeng Bethaven kaepkah aka om Ai la Joshua loh tueih tih, “Cet uh lamtah khohmuen ke hip uh lah,” a ti nah. Te dongah hlang rhoek te cet uh tih Ai te a hip uh.
3 Nígbà tí wọ́n padà sí ọ̀dọ̀ Joṣua, wọ́n wí pé, “Kì í ṣe gbogbo àwọn ènìyàn ni ó ni láti gòkè lọ bá Ai jà. Rán ẹgbẹ̀rún méjì tàbí ẹgbẹ̀rún mẹ́ta ọkùnrin láti gbà á, kí ó má ṣe dá gbogbo àwọn ènìyàn ní agara, nítorí ìba ọkùnrin díẹ̀ ní ó wà níbẹ̀.”
Joshua taengla a mael uh vaengah tah, “Pilnam pum he cet boel mai saeh. Hlang he tongpa thawng hnih thawng thum tluk cet uh saeh lamtah Ai te a tloek toem bitni. Amih hlangsii ham te pilnam pum taengah kohnue mai boeh,” a ti uh.
4 Bẹ́ẹ̀ ní àwọn bí ẹgbẹ̀rún mẹ́ta ọkùnrin lọ; ṣùgbọ́n àwọn ọkùnrin Ai lé wọn sá.
Te dongah pilnam khui lamkah hlang thawng thum tluk tah cet uh van dae Ai hlang rhoek mikhmuh ah rhaelrham uh.
5 Àwọn ènìyàn Ai sì pa àwọn bí mẹ́rìndínlógójì nínú wọn. Wọ́n sì ń lépa àwọn ará Israẹli láti ibodè ìlú títí dé Ṣebarimu, wọ́n sì pa àwọn tí ń sọ̀kalẹ̀. Àyà àwọn ènìyàn náà sì já, ọkàn wọn sì pami.
Amih khui lamkah hlang sawmthum parhuk tluk te Ai hlang rhoek loh a ngawn. Amih te vongka hmai lamloh Shebarim duela a hloem uh tih singling ah a tloek vaengah pilnam tah a thinko paci tih tui bangla om uh.
6 Joṣua sì fa aṣọ rẹ̀ ya, ó sì dojúbolẹ̀ níwájú àpótí ẹ̀rí Olúwa títí di àṣálẹ́. Àwọn àgbà Israẹli sì ṣe bákan náà, wọ́n ku eruku sí orí wọn.
Te dongah Joshua loh a himbai te a phen tih a BOEIPA kah thingkawng hmai ah kholaeh due a maelhmai neh diklai la bakop. Amah neh Israel a hamca rhoek long khaw a lu dongah laipi a poep uh.
7 Joṣua sì wí pé, “Háà, Olúwa Olódùmarè, nítorí kín ni ìwọ ṣe mú àwọn ènìyàn yìí kọjá Jordani, láti fi wọ́n lé àwọn ará Amori lọ́wọ́, láti pa wọn run? Àwa ìbá mọ̀ kí a dúró ní òdìkejì Jordani?
Te vaengah Joshua loh, “Aw ka Boeipa Yahovah, balae tih pilnam he Jordan na kat na kat sak phoeiah kaimih aka milh sak ham a Amori kut ah kaimih he nan voeih. Ka ueh uh mai vetih Jordan rhalvangan ah duem ka om uh mai mako?
8 Olúwa, kín ni èmi yóò sọ nísinsin yìí tí Israẹli sì ti sá níwájú ọ̀tá a rẹ̀?
Aw Boeipa Israel loh a thunkha rhoek kah mikhmuh ah a rhawn a maelh te balae ka ti eh.
9 Àwọn Kenaani àti àwọn ènìyàn ìlú tí ó kù náà yóò gbọ́ èyí, wọn yóò sì yí wa ká, wọn yóò sì ké orúkọ wa kúrò ní ayé. Kí ni ìwọ ó ha ṣe fún orúkọ ńlá à rẹ?”
Kanaan neh khohmuen kah khosa boeih loh ya koinih kaimih he m'vael uh vetih kaimih ming he diklai lamkah a hnawt uh ni ta. Te vaengah na boeilen ming te metlam na saii eh?,” a ti nah.
10 Olúwa sì sọ fún Joṣua pé, “Dìde! Kín ni ìwọ ń ṣe tí ó fi dojúbolẹ̀?
Te dongah Joshua te BOEIPA loh, “Namah mah thoo lah. Balae tih na hmai la na bakop?
11 Israẹli ti ṣẹ̀, wọ́n sì ti ba májẹ̀mú mi jẹ́, èyí tí mo pàṣẹ fún wọn pé kí wọn pamọ́. Wọ́n ti mú nínú ohun ìyàsọ́tọ̀, wọ́n ti jí, wọ́n pa irọ́, wọ́n ti fi wọ́n sí ara ohun ìní wọn.
Israel he tholh tih ka paipi khaw a poe. Amih te ka uen lalah yaehtaboeih te a loh uh bal tih a huen uh bal. Te lalah khaw basa uh tih amamih kah hnopai khuiah a khueh uh bal.
12 Ìdí nì èyí tí àwọn ará Israẹli kò fi lè dúró níwájú àwọn ọ̀tá wọn; wọ́n yí ẹ̀yìn wọn padà, wọ́n sì sálọ níwájú ọ̀tá a wọn nítorí pé àwọn gan an ti di ẹni ìparun. Èmi kì yóò wà pẹ̀lú u yín mọ́, bí kò ṣe pé ẹ̀yin pa ohun ìyàsọ́tọ̀ run kúrò ní àárín yín.
Israel ca rhoek he a thunkha rhoek mikhmuh ah pai thai mahpawh. Yaehtaboeih la a om uh dongah a thunkha kah mikhmuh ah khaw a rhawn ni hikhik a hooi uh eh. Na khui lamkah yaehtaboeih te na khoe uh pawt atah nangmih taengah om hamla ka coeng thai voel moenih.
13 “Lọ, ya àwọn ènìyàn náà sí mímọ́. Sọ fún wọn pé, ‘Ẹ ya ara yín sí mímọ́ fún ọ̀la, nítorí báyìí ni Olúwa, Ọlọ́run Israẹli wí, ohun ìyàsọ́tọ̀ kan ń bẹ ní àárín yín, Israẹli. Ẹ̀yin kì yóò lè dúró níwájú àwọn ọ̀tá a yín títí ẹ̀yin yóò fi mú kúrò.
Thoo lamtah pilnam ke ciim laeh. Te vaengah, “Israel Pathen BOEIPA loh, 'Israel nang khui ah yaehtaboeih om tih na khui lamkah yaehtaboeih te na khoe uh hlanhil na thunkha rhoek kah mikhmuh ah pai ham tah na coeng uh moenih,’ a ti coeng dongah thangvuen kho ham namamih te ciim uh laeh,” ti nah.
14 “‘Ní òwúrọ̀, kí ẹ mú ará yín wá síwájú ní ẹ̀yà kọ̀ọ̀kan. Ẹ̀yà tí Olúwa bá mú yóò wá sí iwájú ní agbo ilé kọ̀ọ̀kan, agbo ilé tí Olúwa bá mú yóò wá sí iwájú ní ìdílé kọ̀ọ̀kan, ìdílé tí Olúwa bá sì mú yóò wá sí iwájú ní ẹni kọ̀ọ̀kan.
Te dongah mincang ah namamih koca rhoek loh ha capit uh laeh. BOEIPA loh a buem koca long tah amah huiko neh ha pawk uh saeh. BOEIPA loh a buem huiko long tah a imkhuikho neh ha pawk uh saeh. BOEIPA loh a buem imkhuikho long khaw a hlang rhoek neh ha pawk saeh.
15 Ẹnikẹ́ni tí a bá ká mọ́ pẹ̀lú ohun ìyàsọ́tọ̀ náà, a ó fi iná pa á run, pẹ̀lú gbogbo ohun tí ó ní. Ó ti ba májẹ̀mú Olúwa jẹ́, ó sì ti ṣe nǹkan ìtìjú ní Israẹli!’”
Yaehtaboeih aka buem tah ana om saeh, BOEIPA kah paipi a poe tih Israel khui ah boethae halang ni a. saii. Te dongah amah neh amah taengkah boeih te hmai neh hoeh saeh,” a ti nah.
16 Ní kùtùkùtù òwúrọ̀ ọjọ́ kejì, Joṣua mú Israẹli wá síwájú ní ẹ̀yà kọ̀ọ̀kan, a sì mú ẹ̀yà Juda.
Mincang a thoh vaengah Joshua taengla Israel koca rhoek loh ha capit uh tih Judah koca te a tuuk.
17 Àwọn agbo ilé e Juda wá sí iwájú, ó sì mú agbo ilé Sera. Ó sì mú agbo ilé Sera wá síwájú ní ìdílé kọ̀ọ̀kan, a sì mú ìdílé Sabdi.
Judah kah a hui a ko ha pawk vaengah Zarkhii kah a huiko te a tuuk. Zarkhii huiko khuikah hlang la a pawk dongah Zabdi te a tuuk.
18 Joṣua sì mú ìdílé Simri wá síwájú ní ọkùnrin kọ̀ọ̀kan, a sì mú Akani ọmọ Karmi, ọmọ Sabdi, ọmọ Sera ti ẹ̀yà Juda.
Anih imkhui kah hlang la a pawk dongah Judah koca Zerah ko Zabdi kah a ca Karmee capa Akhan te a tuuk.
19 Nígbà náà ní Joṣua sọ fún Akani pé, “Ọmọ mi fi ògo fún Olúwa, Ọlọ́run Israẹli, kí o sì fi ìyìn fún un. Sọ fún mi ohun tí ìwọ ti ṣe, má ṣe fi pamọ́ fún mi.”
Te dongah Akhan te Joshua loh, “Ka ca, Israel Pathen BOEIPA taengah thangpomnah pae laeh lamtah uemonah khaw amah taengah pae laeh. Na saii te kai taengah phoe lamtah phah voel boeh,” a ti nah.
20 Akani sì dáhùn pé, “Òtítọ́ ni! Mo ti ṣẹ̀ sí Olúwa, Ọlọ́run Israẹli. Nǹkan tí mo ṣe nìyìí,
Te vaengah Akhan loh Joshua te a doo tih, “Ue kai he Israel Pathen BOEIPA taengah ka tholh coeng tih he tlam he khaw ka saii coeng.
21 nígbà tí mo rí ẹ̀wù Babeli kan tí ó dára nínú ìkógun, àti igba ṣékélì fàdákà àti odindi wúrà olóṣùnwọ́n àádọ́ta ṣékélì, mo ṣe ojúkòkòrò wọn mo sì mú wọn. Mo fi wọ́n pamọ́ ní abẹ́ àgọ́ mi àti fàdákà ní abẹ́ rẹ̀.”
Kutbuem te ka sawt tih ka hmuh vaengah Shinar himbai then yungat, cak a khiing shekel yahnih, sui a khiing shekel sawmnga pakhat te ka nai tih ka loh. Tedae ka dap khui kah diklai khui ah ka up tih a cak te laedil ah om ke,” a ti nah.
22 Bẹ́ẹ̀ ni Joṣua ran àwọn òjíṣẹ́, wọ́n sì sáré wọ inú àgọ́ náà, ó sì wà níbẹ̀, a sì fi pamọ́ nínú àgọ́ ọ rẹ̀, àti fàdákà ní abẹ́ ẹ rẹ̀.
Te dongah Joshua loh puencawn rhoek te a tueih tih dap la a yong uh vaengah tah dap khuiah a thuh tih a laedil ah cak ana om tangloeng.
23 Wọ́n sì mú àwọn nǹkan náà jáde láti inú àgọ́ rẹ̀, wọ́n mú wọn wá fún Joṣua àti gbogbo àwọn ọmọ Israẹli, wọ́n sì fi wọ́n lélẹ̀ níwájú Olúwa.
Te dongah amih te dap khui lamkah a loh uh tih Joshua neh Israel ca rhoek taengla boeih a khuen uh. Te phoeiah BOEIPA hmai ah a rha uh.
24 Nígbà náà ni Joṣua pẹ̀lú gbogbo Israẹli, mú Akani ọmọ Sera, fàdákà, ẹ̀wù àti wúrà tí a dà, àwọn ọmọ rẹ̀ ọkùnrin àti obìnrin, màlúù rẹ̀, kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ àti àgùntàn àgọ́ rẹ̀ àti gbogbo ohun tí ó ni, wọ́n sì kó wọn lọ sí ibi àfonífojì Akori.
Te phoeiah Zerah capa Akhan neh cak khaw, himbai khaw sui tling khaw, a capa neh a canu khaw, a vaito khaw, a laak khaw, a boiva khaw, a dap neh anih taengkah aka om boeih te Joshua loh a loh pah tih anih te Israel pum loh Akor kol la a khuen uh.
25 Joṣua sì wí pé, “Èéṣe tí ìwọ mú wàhálà yìí wá sí orí wa? Olúwa yóò mú ìpọ́njú wá sí orí ìwọ náà lónìí.” Nígbà náà ni gbogbo Israẹli sọ ọ́ ní òkúta pa, lẹ́yìn ìgbà tí wọ́n sọ àwọn tókù ní òkúta pa tán, wọ́n sì jó wọn níná.
Te phoeiah Joshua loh, “Balae tih kaimih nan lawn, tihnin ah BOEIPA loh nang n'lawn saeh,” a ti nah. Anih te Israel pum loh lungto neh a dae uh tih hmai neh a hoeh uh. Te phoeiah ah khaw lungto neh a dae thil uh bal.
26 Wọ́n sì kó òkìtì òkúta ńlá lé Akani lórí títí di òní yìí. Nígbà náà ní Olúwa sì yí ìbínú gbígbóná rẹ̀ padà. Nítorí náà ni a ṣe ń pe orúkọ ibẹ̀ ní àfonífojì Akori láti ìgbà náà.
Te dongah anih sokah a kuk lungkuk te tihnin duela muep om pueng. Tedae BOEIPA thintoek thinsa a sah coeng dongah tekah a hmuen ming khaw tihnin due Akor kol la a khue.