< Joshua 4 >

1 Nígbà tí gbogbo orílẹ̀-èdè náà kọjá nínú odò Jordani tan, Olúwa sọ fún Joṣua pé,
Pütkül hǝlⱪ Iordan dǝryasidin tamamǝn ɵtüp bolƣanda, Pǝrwǝrdigar Yǝxuaƣa sɵz ⱪilip: —
2 “Yan ọkùnrin méjìlá nínú àwọn ènìyàn, ẹnìkan nínú ẹ̀yà kọ̀ọ̀kan,
Hǝlⱪning arisidin on ikki adǝmni talliƣin, ⱨǝr ⱪǝbilidin birdin adǝm bolsun,
3 kí o sì pàṣẹ fún wọn pé, ‘Ẹ gbé òkúta méjìlá láti àárín odò Jordani ní ibi tí àwọn àlùfáà dúró sí, kí ẹ sì rù wọn kọjá, kí ẹ sì gbé wọn sí ibi tí ẹ̀yin yóò sùn ní alẹ́ yìí.’”
ularƣa: — Silǝr Iordan dǝryasining otturisidin, kaⱨinlarning putliri mǝzmut turƣan jaydin on ikki taxni elip, ularni kɵtürüp kelip ɵzünglar bügün keqǝ bargaⱨ tikidiƣan yǝrgǝ ⱪoyunglar, degin, dedi.
4 Bẹ́ẹ̀ ni Joṣua pe àwọn ọkùnrin méjìlá tí ó ti yàn nínú àwọn ọmọ Israẹli, ẹnìkan nínú ẹ̀yà kọ̀ọ̀kan,
Xuning bilǝn Yǝxua ⱨǝr ⱪǝbilidin birdin adǝmni, yǝni Israillar arisidin talliƣan on ikki kixini qaⱪirdi;
5 ó sì wí fún wọn pé, “Ẹ kọjá lọ ní iwájú àpótí ẹ̀rí Olúwa Ọlọ́run yín sí àárín odò Jordani. Kí olúkúlùkù yín gbé òkúta kọ̀ọ̀kan lé èjìká a rẹ̀, gẹ́gẹ́ bí iye ẹ̀yà àwọn ọmọ Israẹli,
andin Yǝxua ularƣa: — Silǝr Iordan dǝryasining otturisiƣa qüxüp Pǝrwǝrdigar Hudayinglarning ǝⱨdǝ sanduⱪining aldiƣa berip, Israilning on ikki ⱪǝbilisining saniƣa mas ⱨalda birdin taxni elip mürǝnglǝrgǝ ⱪoyunglar.
6 kí ó sì jẹ́ àmì láàrín yín. Ní ọjọ́ iwájú, nígbà tí àwọn ọmọ yín bá béèrè lọ́wọ́ yín pé, ‘Kí ni òkúta wọ̀nyí dúró fún?’
Qünki bu aranglarda bir ǝslǝtmǝ-bǝlgǝ bolidu; kǝlgüsidǝ baliliringlar: — Bu taxlarning silǝrgǝ nemǝ ǝⱨmiyiti bar? — dǝp sorap ⱪalsa, silǝr ularƣa: —
7 Nígbà náà ni ẹ̀yin yóò dá wọn lóhùn pé, nítorí a gé omi odò Jordani kúrò ní iwájú àpótí ẹ̀rí Olúwa. Nígbà tí a rékọjá a Jordani, a gé omi Jordani kúrò. Àwọn òkúta wọ̀nyí yóò sì jẹ́ ìrántí fún àwọn ọmọ Israẹli láéláé.”
Iordan dǝryasining suliri Pǝrwǝrdigarning ǝⱨdǝ sanduⱪining aldida üzüp ⱪoyuldi; [ǝⱨdǝ sanduⱪi] Iordan dǝryasidin ɵtküzülgǝndǝ Iordan dǝryasining suliri üzüp ⱪoyuldi; xunga bu taxlar Israillarƣa mǝnggülük bir ǝslǝtmǝ-bǝlgǝ bolidu, — dǝp jawap berisilǝr.
8 Báyìí ni àwọn ọmọ Israẹli sì ṣe bí Joṣua ti pàṣẹ fún wọn. Wọ́n gbé òkúta méjìlá láti àárín odò Jordani gẹ́gẹ́ bí iye ẹ̀yà àwọn ọmọ Israẹli, bí Olúwa ti sọ fún Joṣua; wọ́n sì rù wọ́n kọjá lọ sí ibùdó, ní ibi tí wọ́n ti gbé wọn kalẹ̀.
Xuning bilǝn Israillar Yǝxua ularƣa buyruƣandǝk ⱪildi. Pǝrwǝrdigarning Yǝxuaƣa ⱪilƣan ǝmri boyiqǝ Israilning ⱪǝbililirining saniƣa muwapiⱪ Iordan dǝryasining otturisidin on ikki taxni elip, ⱪonidiƣan jayƣa kɵtürüp berip, xu yǝrdǝ ⱪoyup ⱪoydi.
9 Joṣua sì to òkúta méjìlá náà sí àárín odò Jordani fún ìrántí ní ọ̀kánkán ibi tí àwọn àlùfáà tí ó ru àpótí ẹ̀rí dúró sí. Wọ́n sì wà níbẹ̀ di òní yìí.
Buningdin baxⱪa Yǝxua Iordan dǝryasining otturisida ǝⱨdǝ sanduⱪini kɵtürgǝn kaⱨinlarning putliri mustǝⱨkǝm turƣan jayda on ikki taxni tiklǝp ⱪoydi. Bu taxlar bolsa bügüngiqǝ xu yǝrdǝ turidu.
10 Àwọn àlùfáà tí ó ru àpótí náà dúró ní àárín Jordani títí gbogbo nǹkan tí Olúwa pàṣẹ fún Joṣua fi di ṣíṣe nípasẹ̀ àwọn ènìyàn, gẹ́gẹ́ bí Mose ti pàṣẹ fún Joṣua. Àwọn ènìyàn náà sì yára kọjá,
Pǝrwǝrdigar Yǝxuaƣa hǝlⱪⱪǝ eytixⱪa tapiliƣan barliⱪ ixlar orunlanƣuqilik, yǝni Musa ǝslidǝ Yǝxuaƣa buyruƣanlirining ⱨǝmmisi bǝja kǝltürülgüqǝ, ǝⱨdǝ sanduⱪini kɵtürgǝn kaⱨinlar Iordan dǝryasining otturisida tohtap turdi. Hǝlⱪ xu yǝrdin tezdin ɵtüwatatti.
11 bí gbogbo wọn sì ti rékọjá tán, ni àpótí ẹ̀rí Olúwa àti àwọn àlùfáà wá sí òdìkejì. Bí àwọn ènìyàn sì ti ń wò wọ́n.
Xundaⱪ boldiki, barliⱪ hǝlⱪ tamamǝn ɵtüp bolƣanda, Pǝrwǝrdigarning [ǝⱨdǝ] sanduⱪi bilǝn kaⱨinlar hǝlⱪning aldidin ɵtti.
12 Àwọn ọkùnrin Reubeni, Gadi àti ìdajì ẹ̀yà Manase náà sì rékọjá ní ìhámọ́ra ogun níwájú àwọn ọmọ Israẹli, gẹ́gẹ́ bí Mose ti pàṣẹ fún wọn.
Rubǝnlǝr bilǝn Gadlar wǝ Manassǝⱨning yerim ⱪǝbilisidikilǝrmu Musaning ularƣa buyruƣinidǝk sǝptǝ tüzüp Israillarning aldida dǝryadin ɵtti.
13 Àwọn bí ọ̀kẹ́ méjì tó ti múra fún ogun rékọjá lọ ní iwájú Olúwa sí pẹ̀tẹ́lẹ̀ Jeriko láti jagun.
jǝmiy bolup ⱪiriⱪ mingqǝ ⱪorallanƣan kixi Pǝrwǝrdigarning aldidin ɵtüp, Yeriho tüzlǝngliklirigǝ kelip, jǝng ⱪilixⱪa tǝyyar turdi.
14 Ní ọjọ́ náà ni Olúwa gbé Joṣua ga ní ojú gbogbo àwọn ọmọ Israẹli, wọ́n sì bẹ̀rù u rẹ̀ ní gbogbo ọjọ́ ayé e wọn, gẹ́gẹ́ bí wọ́n ti bẹ̀rù Mose.
U küni Pǝrwǝrdigar Yǝxuani pütkül Israilning nǝziridǝ qong ⱪildi; ular uning pütün ɵmridǝ Musadin ⱪorⱪⱪandǝk uningdinmu ⱪorⱪti.
15 Olúwa sì sọ fún Joṣua pé,
Pǝrwǝrdigar Yǝxuaƣa sɵz ⱪilip: —
16 “Pàṣẹ fún àwọn àlùfáà tí o ń ru àpótí ẹ̀rí, kí wọn kí ó jáde kúrò nínú odò Jordani.”
Ⱨɵküm-guwaⱨliⱪ sanduⱪini kɵtürgǝn kaⱨinlarƣa: — Iordan dǝryasidin qiⱪinglar, dǝp buyruƣin, dedi.
17 Bẹ́ẹ̀ ni Joṣua pàṣẹ fún àwọn àlùfáà pé, “Ẹ jáde kúrò nínú odò Jordani.”
Xunga Yǝxua kaⱨinlarƣa: — Iordan dǝryasidin qiⱪinglar, dǝp buyrudi.
18 Àwọn àlùfáà náà jáde láti inú odò pẹ̀lú àpótí ẹ̀rí Olúwa ni orí wọn. Bí wọ́n ti fi ẹsẹ̀ ẹ wọn tẹ orí ilẹ̀ gbígbẹ ni omi Jordani náà padà sí ààyè e rẹ̀, o sì kún wọ bèbè bí i ti àtẹ̀yìnwá.
Xundaⱪ boldiki, Pǝrwǝrdigarning ǝⱨdǝ sanduⱪini kɵtürgǝn kaⱨinlar Iordan dǝryasining otturisidin qiⱪip, putlirining tapini ⱪuruⱪluⱪni dǝssixi bilǝnla, Iordan dǝryasining süyi yǝnǝ ɵz jayiƣa ⱪaytip kelip, awwalⱪidǝk ikki ⱪirƣiⱪiƣiqǝ texip eⱪixⱪa baxlidi.
19 Ní ọjọ́ kẹwàá oṣù kìn-ín-ní àwọn ènìyàn náà lọ láti Jordani, wọ́n sì dúró ní Gilgali ní ìlà-oòrùn Jeriko.
Hǝlⱪ bolsa birinqi ayning oninqi küni Iordan dǝryasidin ɵtüp, Yerihoning xǝrⱪining ǝng qǝt tǝripidiki Gilgalƣa kelip qedirgaⱨ tikti.
20 Joṣua sì to àwọn òkúta méjìlá tí wọ́n mú jáde ní Jordani jọ ní Gilgali.
Ular Iordan dǝryasidin alƣaq kǝlgǝn on ikki taxni bolsa, Yǝxua ularni Gilgalda tiklǝp ⱪoydi;
21 Ó sì sọ fún àwọn ará Israẹli, “Ní ọjọ́ iwájú nígbà tí àwọn ọmọ yín bá béèrè ní ọwọ́ baba wọn pé, ‘Kín ni òkúta wọ̀nyí dúró fún?’
andin Israillarƣa: — Keyin baliliringlar ɵz atiliridin: — Bu taxlarning ǝⱨmiyiti nemǝ, dǝp sorisa,
22 Nígbà náà ni ẹ ó jẹ́ kí àwọn ọmọ yín mọ̀ pé, ‘Israẹli rékọjá odò Jordani ní orí ilẹ̀ gbígbẹ.’
silǝr baliliringlarƣa mundaⱪ uⱪturup ⱪoyunglar: — «Israil ilgiri ⱪuruⱪ yǝrni dǝssǝp Iordan dǝryasidin ɵtkǝnidi;
23 Nítorí Olúwa Ọlọ́run yín mú Jordani gbẹ ní iwájú u yín títí ẹ̀yin fi kọjá. Olúwa Ọlọ́run yín ti ṣe sí Jordani gẹ́gẹ́ bí ó ti ṣe sí Òkun Pupa, nígbà tí ó mú un gbẹ ní iwájú wa títí àwa fi kọjá.
qünki Pǝrwǝrdigar Hudayinglar biz Ⱪizil Dengizdin ɵtküqǝ aldimizda uning sulirini ⱪurutup bǝrgǝndǝk, Pǝrwǝrdigar Hudayinglar silǝr ɵtküqǝ aldinglarda Iordan dǝryasining süyini ⱪurutup bǝrdi;
24 Ó ṣe èyí kí gbogbo ayé lè mọ̀ pé ọwọ́ Olúwa ní agbára, àti kí ẹ̀yin kí ó lè máa bẹ̀rù Olúwa Ọlọ́run yín ní ìgbà gbogbo.”
yǝr yüzidiki barliⱪ ǝllǝr Pǝrwǝrdigarning ⱪolining ⱪanqilik küqlüklükini bilsun, xundaⱪla silǝrning Pǝrwǝrdigar Hudayinglardin ⱨǝmixǝ ⱪorⱪuxunglar üqün U xundaⱪ ⱪildi» — dedi.

< Joshua 4 >