< Joshua 4 >

1 Nígbà tí gbogbo orílẹ̀-èdè náà kọjá nínú odò Jordani tan, Olúwa sọ fún Joṣua pé,
Hanki maka Israeli vahe'mo'za Jodani tima takahe vagaretazageno, Ra Anumzamo'a Josuana amanage huno asami'ne,
2 “Yan ọkùnrin méjìlá nínú àwọn ènìyàn, ẹnìkan nínú ẹ̀yà kọ̀ọ̀kan,
Israeli vahepintira 12fu'a vahe zamagi hinke'za eho. Hagi mago'mago naga nofipintira magoke etere hanagenka,
3 kí o sì pàṣẹ fún wọn pé, ‘Ẹ gbé òkúta méjìlá láti àárín odò Jordani ní ibi tí àwọn àlùfáà dúró sí, kí ẹ sì rù wọn kọjá, kí ẹ sì gbé wọn sí ibi tí ẹ̀yin yóò sùn ní alẹ́ yìí.’”
Jodani timofo amu'nompima pristi vahe'mo'zama zamagama re'za oti'nareti 12fu'a zamente zamente havea ome erita vuta, seli noma kita meni kenage'ma masesaza kumate omenteho hunka zamasamio.
4 Bẹ́ẹ̀ ni Joṣua pe àwọn ọkùnrin méjìlá tí ó ti yàn nínú àwọn ọmọ Israẹli, ẹnìkan nínú ẹ̀yà kọ̀ọ̀kan,
Higeno Josua'a Israeli naga nofipinti mago mago zamagi hutere huno 12fu'a vahe'ma huhampri'nea nagara kehige'za e'naze.
5 ó sì wí fún wọn pé, “Ẹ kọjá lọ ní iwájú àpótí ẹ̀rí Olúwa Ọlọ́run yín sí àárín odò Jordani. Kí olúkúlùkù yín gbé òkúta kọ̀ọ̀kan lé èjìká a rẹ̀, gẹ́gẹ́ bí iye ẹ̀yà àwọn ọmọ Israẹli,
Hagi Josua'a amanage huno zamasami'ne, Ete Jodani timpi uramita Ra Anumzana tamagri Anumzamofo huhagerafi huvempage vogisima eri'za oti'naza pristi vahe'mokizmi zamagiafinti 12fu'a naga'motma naga nofitamire huhampritere hutma mago'mago havea atita tamafunte erita eho.
6 kí ó sì jẹ́ àmì láàrín yín. Ní ọjọ́ iwájú, nígbà tí àwọn ọmọ yín bá béèrè lọ́wọ́ yín pé, ‘Kí ni òkúta wọ̀nyí dúró fún?’
Hanki henkama tamagripinti'ma fore'ma hanaza mofavremo'za ana haveramima nege'za, ama avame'zana nagafare me'ne? hu'za tamantahigesageta,
7 Nígbà náà ni ẹ̀yin yóò dá wọn lóhùn pé, nítorí a gé omi odò Jordani kúrò ní iwájú àpótí ẹ̀rí Olúwa. Nígbà tí a rékọjá a Jordani, a gé omi Jordani kúrò. Àwọn òkúta wọ̀nyí yóò sì jẹ́ ìrántí fún àwọn ọmọ Israẹli láéláé.”
tamagra amanage hutma zamasamiho, Ra Anumzamofo huhagerafi huvempage vogisima eri'za Jodani timpima azageno'ma tanege'zama hagege mopare'ma takahe'nazagu, Israeli vahe'mo'zama nege'za antahimi vava hanaza avame'za me'ne huta zmasamigahaze.
8 Báyìí ni àwọn ọmọ Israẹli sì ṣe bí Joṣua ti pàṣẹ fún wọn. Wọ́n gbé òkúta méjìlá láti àárín odò Jordani gẹ́gẹ́ bí iye ẹ̀yà àwọn ọmọ Israẹli, bí Olúwa ti sọ fún Joṣua; wọ́n sì rù wọ́n kọjá lọ sí ibùdó, ní ibi tí wọ́n ti gbé wọn kalẹ̀.
Hanki Ra Anumzamo'ma Josua'ma asami'nea kante ante'za, Jodani timofo amu'nompinti Israeli naga'nofite huhampri'za mago'mago have atitere hu'za ana maka 12fu'a havea eri'za, vu'za kuma'ma ome ante'za masazare anante ome ante'naze.
9 Joṣua sì to òkúta méjìlá náà sí àárín odò Jordani fún ìrántí ní ọ̀kánkán ibi tí àwọn àlùfáà tí ó ru àpótí ẹ̀rí dúró sí. Wọ́n sì wà níbẹ̀ di òní yìí.
Hanki Josua'a agranena 12fu'a have erino Jodani timofo amu'nompima Ra Anumzamofo huhagerafi huvempage vogisima pristi vahe'mo'zama eri'ne'zama oti'nazare magopi ante atru higeno meno eno ama knarera ehanati'ne.
10 Àwọn àlùfáà tí ó ru àpótí náà dúró ní àárín Jordani títí gbogbo nǹkan tí Olúwa pàṣẹ fún Joṣua fi di ṣíṣe nípasẹ̀ àwọn ènìyàn, gẹ́gẹ́ bí Mose ti pàṣẹ fún Joṣua. Àwọn ènìyàn náà sì yára kọjá,
Hagi Ra Anumzamofo huhagerafi huvempage vogisima eri'naza pristi vahe'mo'za Jodani timofo amu'nompi oti'nazageno, ana maka zama Ra Anumzamo'ene Mosese'enema Josuama asamike, huo huke hunte'na'a zana, ana maka huvagare'naze. Hige'za Israeli naga'mo'za ame'ama hu'za Jodani tina takahe'za kantu kaziga vu'naze.
11 bí gbogbo wọn sì ti rékọjá tán, ni àpótí ẹ̀rí Olúwa àti àwọn àlùfáà wá sí òdìkejì. Bí àwọn ènìyàn sì ti ń wò wọ́n.
Hanki maka Israeli vahe'mo'za Jodani tima takahe'za kama kazigama eme oti vagarazage'za, timpintira Ra Anumzamofo huhagerafi huvempage vogisia pristi naga'mo'za eri'za ome zamagatere'za zamavuga evu oti'naze.
12 Àwọn ọkùnrin Reubeni, Gadi àti ìdajì ẹ̀yà Manase náà sì rékọjá ní ìhámọ́ra ogun níwájú àwọn ọmọ Israẹli, gẹ́gẹ́ bí Mose ti pàṣẹ fún wọn.
Hagi Rubeni naga'ma Gati naga'ma Manase naga'ma amu'nompinti refko hu'naza naga'mo'zane ha'ma huga vahe'amozage Israeli naga'mokizmi zamavuga ha'zana tro tra hu'za, Mosese'ma zamasami'nea kante ante'za ugote'za vu'naze.
13 Àwọn bí ọ̀kẹ́ méjì tó ti múra fún ogun rékọjá lọ ní iwájú Olúwa sí pẹ̀tẹ́lẹ̀ Jeriko láti jagun.
Anampina 40 tauseni'a naza ha'ma huga vahera Ra Anumzamofo avurera vu'za, Jeriko tavaonte mago agupo me'nefi vu'naze.
14 Ní ọjọ́ náà ni Olúwa gbé Joṣua ga ní ojú gbogbo àwọn ọmọ Israẹli, wọ́n sì bẹ̀rù u rẹ̀ ní gbogbo ọjọ́ ayé e wọn, gẹ́gẹ́ bí wọ́n ti bẹ̀rù Mose.
Ana knazupa Ra Anumzamo'a Israeli vahe zamavufi Josuana azeri ante'ama hige'za, Mosesenkema antahimi'nazaza hu'za Josu'ana ke'a antahimi'naze.
15 Olúwa sì sọ fún Joṣua pé,
Anante Ra Anumzamo'a Josuana amanage huno asami'ne,
16 “Pàṣẹ fún àwọn àlùfáà tí o ń ru àpótí ẹ̀rí, kí wọn kí ó jáde kúrò nínú odò Jordani.”
Zamasamige'za huhagerafi huvempage vogisima e'neri'za pristi vahe'mo'za Jodani timpintira atre'za ankenarega emareriho.
17 Bẹ́ẹ̀ ni Joṣua pàṣẹ fún àwọn àlùfáà pé, “Ẹ jáde kúrò nínú odò Jordani.”
Higeno Josua'a pristi nagara huzamanteno, Jodani timpintira atreta ankenarega atiramita eho.
18 Àwọn àlùfáà náà jáde láti inú odò pẹ̀lú àpótí ẹ̀rí Olúwa ni orí wọn. Bí wọ́n ti fi ẹsẹ̀ ẹ wọn tẹ orí ilẹ̀ gbígbẹ ni omi Jordani náà padà sí ààyè e rẹ̀, o sì kún wọ bèbè bí i ti àtẹ̀yìnwá.
Anagema hige'za Ra Anumzamofo huhagerafi huvempage vogisima eri'za oti'naza pristi vahe'mo'za, Jodani timofo amu'nompintira atre'za ankenarega e'za, timpinti'ma zamagiama erisga hu'za mopare'ma razageno'a, Jodani timo'a ete hageno ko'ma hu'neaza huno evu'ne.
19 Ní ọjọ́ kẹwàá oṣù kìn-ín-ní àwọn ènìyàn náà lọ láti Jordani, wọ́n sì dúró ní Gilgali ní ìlà-oòrùn Jeriko.
Hagi Israeli vahe'mo'za ese ikamofona 10ni knazupa Jodani tina takamahe'za kantu kazigama vute'za, Jeriko kuma'mofona zage hanati kaziga Gilgalie nehazare ome kumara ante'naze.
20 Joṣua sì to àwọn òkúta méjìlá tí wọ́n mú jáde ní Jordani jọ ní Gilgali.
Hanki 12fu'a havema Jodani timpinti'ma ati'zama eri'za e'naza haveramina, Gilgalie nehazare ana haveramina Josua'a magopi eri ante atru hu'ne.
21 Ó sì sọ fún àwọn ará Israẹli, “Ní ọjọ́ iwájú nígbà tí àwọn ọmọ yín bá béèrè ní ọwọ́ baba wọn pé, ‘Kín ni òkúta wọ̀nyí dúró fún?’
Ana nehuno Israeli vahe'mokizmia amanage huno zamasami'ne, henkama fore'ma hanaza mofavremo'zama zamafahe'ima zamantahige'zma, ama haveramina nagafare mane'ne? hu'zama zamantahigesage'za,
22 Nígbà náà ni ẹ ó jẹ́ kí àwọn ọmọ yín mọ̀ pé, ‘Israẹli rékọjá odò Jordani ní orí ilẹ̀ gbígbẹ.’
amanage hu'za zamasamiho, Israeli vahe'mo'za Jodani timo'ma hihima huno marerigeno mopamo hagegema hu'nege'za takahe'za e'naza zanku negeta antahimi avame'za me'ne hu'za zmasamigahaze.
23 Nítorí Olúwa Ọlọ́run yín mú Jordani gbẹ ní iwájú u yín títí ẹ̀yin fi kọjá. Olúwa Ọlọ́run yín ti ṣe sí Jordani gẹ́gẹ́ bí ó ti ṣe sí Òkun Pupa, nígbà tí ó mú un gbẹ ní iwájú wa títí àwa fi kọjá.
Na'ankure Ra Anumzana tamagri Anumzamo Koranke Hagerima hu'neaza huno Jodani tina eri hagege higeta, hagege mopare takaheta evagare'none.
24 Ó ṣe èyí kí gbogbo ayé lè mọ̀ pé ọwọ́ Olúwa ní agbára, àti kí ẹ̀yin kí ó lè máa bẹ̀rù Olúwa Ọlọ́run yín ní ìgbà gbogbo.”
E'ina hu'negu ama mopafi maka vahe'mo'zama ke'za antahi'zama hanazana, Ra Anumzamofo azamo'a hanavenentake hu'ne nehanageta, tamagra Ra Anumzana tamagri Anumzamofonke maka zupa korora huntevava hiho.

< Joshua 4 >