< Joshua 4 >

1 Nígbà tí gbogbo orílẹ̀-èdè náà kọjá nínú odò Jordani tan, Olúwa sọ fún Joṣua pé,
Volt pedig, midőn teljesen átkelt a Jordánon az egész nép, akkor szólt az Örökkévaló Józsuához, mondván:
2 “Yan ọkùnrin méjìlá nínú àwọn ènìyàn, ẹnìkan nínú ẹ̀yà kọ̀ọ̀kan,
Vegyetek magatoknak a nép közül tizenkét férfit, egy-egy férfit törzsenként;
3 kí o sì pàṣẹ fún wọn pé, ‘Ẹ gbé òkúta méjìlá láti àárín odò Jordani ní ibi tí àwọn àlùfáà dúró sí, kí ẹ sì rù wọn kọjá, kí ẹ sì gbé wọn sí ibi tí ẹ̀yin yóò sùn ní alẹ́ yìí.’”
és parancsoljátok meg nekik, mondván: vigyetek magatoknak innen, a Jordán közepéről, onnan, ahol szilárdan állnak a papok lábai, tizenkét követ, vigyétek azokat át magatokkal és tegyétek le a szálláson, ahol az éjjel meg fogtok hálni.
4 Bẹ́ẹ̀ ni Joṣua pe àwọn ọkùnrin méjìlá tí ó ti yàn nínú àwọn ọmọ Israẹli, ẹnìkan nínú ẹ̀yà kọ̀ọ̀kan,
És hívta Józsua a tizenkét férfiút; akiket kirendelt Izraél fiai közül, egy-egy férfit törzsenként;
5 ó sì wí fún wọn pé, “Ẹ kọjá lọ ní iwájú àpótí ẹ̀rí Olúwa Ọlọ́run yín sí àárín odò Jordani. Kí olúkúlùkù yín gbé òkúta kọ̀ọ̀kan lé èjìká a rẹ̀, gẹ́gẹ́ bí iye ẹ̀yà àwọn ọmọ Israẹli,
és mondta nekik Józsua: Vonuljatok az Örökkévaló, a ti Istentek ládája elé a Jordán közepére és emeljetek ki magatoknak, ki-ki egy követ a vállára, Izraél fiai törzseinek száma szerint.
6 kí ó sì jẹ́ àmì láàrín yín. Ní ọjọ́ iwájú, nígbà tí àwọn ọmọ yín bá béèrè lọ́wọ́ yín pé, ‘Kí ni òkúta wọ̀nyí dúró fún?’
Azért hogy ez jelül legyen köz-tetek, midőn majd holnap kérdezik gyermekeitek, mondván, mik nektek e kövek –
7 Nígbà náà ni ẹ̀yin yóò dá wọn lóhùn pé, nítorí a gé omi odò Jordani kúrò ní iwájú àpótí ẹ̀rí Olúwa. Nígbà tí a rékọjá a Jordani, a gé omi Jordani kúrò. Àwọn òkúta wọ̀nyí yóò sì jẹ́ ìrántí fún àwọn ọmọ Israẹli láéláé.”
akkor mondjátok nekik: mivel megszakadtak a Jordán vizei az Örökkévaló szövetségének ládája előtt, amikor átvonult a Jordánon, megszakadtak a Jordán vizei; legyenek tehát e kövek emlékül Izraél fiai számára örökre.
8 Báyìí ni àwọn ọmọ Israẹli sì ṣe bí Joṣua ti pàṣẹ fún wọn. Wọ́n gbé òkúta méjìlá láti àárín odò Jordani gẹ́gẹ́ bí iye ẹ̀yà àwọn ọmọ Israẹli, bí Olúwa ti sọ fún Joṣua; wọ́n sì rù wọ́n kọjá lọ sí ibùdó, ní ibi tí wọ́n ti gbé wọn kalẹ̀.
És cselekedtek akképpen Izraél fiai, amint megparancsolta Józsua: vittek tizenkét követ a Jordán közepéről, amint szólt az Örökkévaló Józsuához, Izraél fiai törzseinek száma szerint; átvitték magukkal a szállásra és letették ott.
9 Joṣua sì to òkúta méjìlá náà sí àárín odò Jordani fún ìrántí ní ọ̀kánkán ibi tí àwọn àlùfáà tí ó ru àpótí ẹ̀rí dúró sí. Wọ́n sì wà níbẹ̀ di òní yìí.
Tizenkét követ pedig fölállított Józsua a Jordán közepén, ott, ahol álltak a papoknak, a szövetség ládája vivőinek lábai; és ott maradtak mind e mai napig.
10 Àwọn àlùfáà tí ó ru àpótí náà dúró ní àárín Jordani títí gbogbo nǹkan tí Olúwa pàṣẹ fún Joṣua fi di ṣíṣe nípasẹ̀ àwọn ènìyàn, gẹ́gẹ́ bí Mose ti pàṣẹ fún Joṣua. Àwọn ènìyàn náà sì yára kọjá,
S a papok, a láda vivői, állva maradtak a Jordán közepén, míg bevégző-dött az egész dolog, amit parancsolt az Örökkévaló Józsuának, hogy mondja el a népnek, mindaszerint, amint parancsolta Mózes Józsuának; a nép pedig sietve átkelt.
11 bí gbogbo wọn sì ti rékọjá tán, ni àpótí ẹ̀rí Olúwa àti àwọn àlùfáà wá sí òdìkejì. Bí àwọn ènìyàn sì ti ń wò wọ́n.
És volt, midőn teljesen átkelt az egész nép, akkor vonult az Örökkévaló ládája, meg a papok a nép elé.
12 Àwọn ọkùnrin Reubeni, Gadi àti ìdajì ẹ̀yà Manase náà sì rékọjá ní ìhámọ́ra ogun níwájú àwọn ọmọ Israẹli, gẹ́gẹ́ bí Mose ti pàṣẹ fún wọn.
És vonultak Reúbén fiai, Gád fiai és Menasse féltörzse fegyveresen Izraél fiai előtt, amint mondta nekik Mózes;
13 Àwọn bí ọ̀kẹ́ méjì tó ti múra fún ogun rékọjá lọ ní iwájú Olúwa sí pẹ̀tẹ́lẹ̀ Jeriko láti jagun.
mintegy negyvenezeren, hadra fölfegyverkezve, vonultak az Örökkévaló előtt háborúra Jeríchó síkságai felé.
14 Ní ọjọ́ náà ni Olúwa gbé Joṣua ga ní ojú gbogbo àwọn ọmọ Israẹli, wọ́n sì bẹ̀rù u rẹ̀ ní gbogbo ọjọ́ ayé e wọn, gẹ́gẹ́ bí wọ́n ti bẹ̀rù Mose.
Ama napon naggyá tette az Örökkévaló Józsuát egész Izraél szemei előtt; félték őt, amint félték Mózest élete minden napjaiban.
15 Olúwa sì sọ fún Joṣua pé,
És szólt az Örökkévaló Józsuához, mondván:
16 “Pàṣẹ fún àwọn àlùfáà tí o ń ru àpótí ẹ̀rí, kí wọn kí ó jáde kúrò nínú odò Jordani.”
Parancsold meg a papoknak, a bizonyság ládája vivőinek, hogy menjenek föl a Jordánból.
17 Bẹ́ẹ̀ ni Joṣua pàṣẹ fún àwọn àlùfáà pé, “Ẹ jáde kúrò nínú odò Jordani.”
S meg-parancsolta Józsua a papoknak, mondván: Jöjjetek föl a Jordánból.
18 Àwọn àlùfáà náà jáde láti inú odò pẹ̀lú àpótí ẹ̀rí Olúwa ni orí wọn. Bí wọ́n ti fi ẹsẹ̀ ẹ wọn tẹ orí ilẹ̀ gbígbẹ ni omi Jordani náà padà sí ààyè e rẹ̀, o sì kún wọ bèbè bí i ti àtẹ̀yìnwá.
Volt pedig, amikor fölmentek a papok, az Örökkévaló szövetsége ládájának vivői, a Jordánból, alig kerültek a papok lába talpai a szárazra, akkor visszatértek a Jordán vizei helyükre és folytak mint tegnap tegnapelőtt mind a partjain túl.
19 Ní ọjọ́ kẹwàá oṣù kìn-ín-ní àwọn ènìyàn náà lọ láti Jordani, wọ́n sì dúró ní Gilgali ní ìlà-oòrùn Jeriko.
A nép pedig fölment a Jordánból az első hónap tizedikén, és táboroztak Gilgálban, Jeríchó keleti szélén.
20 Joṣua sì to àwọn òkúta méjìlá tí wọ́n mú jáde ní Jordani jọ ní Gilgali.
Ama tizenkét követ pedig, melyeket vettek a Jordánból, fölállította Józsua Gilgálban.
21 Ó sì sọ fún àwọn ará Israẹli, “Ní ọjọ́ iwájú nígbà tí àwọn ọmọ yín bá béèrè ní ọwọ́ baba wọn pé, ‘Kín ni òkúta wọ̀nyí dúró fún?’
És szólt Izraél fiaihoz, mondván: Hogyha majd holnap kérdezik gyermekeitek atyáikat, mondván, mik e kövek –
22 Nígbà náà ni ẹ ó jẹ́ kí àwọn ọmọ yín mọ̀ pé, ‘Israẹli rékọjá odò Jordani ní orí ilẹ̀ gbígbẹ.’
akkor tudassátok gyermekeitekkel, mondván: szárazon kelt át Izraél e Jordánon,
23 Nítorí Olúwa Ọlọ́run yín mú Jordani gbẹ ní iwájú u yín títí ẹ̀yin fi kọjá. Olúwa Ọlọ́run yín ti ṣe sí Jordani gẹ́gẹ́ bí ó ti ṣe sí Òkun Pupa, nígbà tí ó mú un gbẹ ní iwájú wa títí àwa fi kọjá.
mivel kiszárasztotta előttetek az Örökkévaló, a ti Istentek a Jordán vizeit, míg át nem keltetek, a mint tett a Örökkévaló, a ti Istentek a nádas tengerrel, melyet kiszárasztott előttünk, míg át nem keltünk.
24 Ó ṣe èyí kí gbogbo ayé lè mọ̀ pé ọwọ́ Olúwa ní agbára, àti kí ẹ̀yin kí ó lè máa bẹ̀rù Olúwa Ọlọ́run yín ní ìgbà gbogbo.”
Azért, hogy megismerjék mind a föld népei az Örökkévaló kezét, hogy erős az; azért hogy féljétek az Örökkévalót, a ti Istenteket, minden időben

< Joshua 4 >