< Joshua 4 >

1 Nígbà tí gbogbo orílẹ̀-èdè náà kọjá nínú odò Jordani tan, Olúwa sọ fún Joṣua pé,
Isala: ili fi dunu huluane da Yodane Hano degei dagoloba, Hina Gode da Yosiuama amane sia: i,
2 “Yan ọkùnrin méjìlá nínú àwọn ènìyàn, ẹnìkan nínú ẹ̀yà kọ̀ọ̀kan,
“Dunu fagoyale, Isala: ili fi fagoyale amoga afae afae amo ilegema.
3 kí o sì pàṣẹ fún wọn pé, ‘Ẹ gbé òkúta méjìlá láti àárín odò Jordani ní ibi tí àwọn àlùfáà dúró sí, kí ẹ sì rù wọn kọjá, kí ẹ sì gbé wọn sí ibi tí ẹ̀yin yóò sùn ní alẹ́ yìí.’”
Ilia da igi fagoyale Yodane Hano dogoa gobele salasu dunu ilia lelu sogebi gala, amo lale dilia wali gasia esalebego amoga legema: ne sia: ma.”
4 Bẹ́ẹ̀ ni Joṣua pe àwọn ọkùnrin méjìlá tí ó ti yàn nínú àwọn ọmọ Israẹli, ẹnìkan nínú ẹ̀yà kọ̀ọ̀kan,
Amalalu, Yosiua da dunu fagoyale gala e da ilegei, ilima misa: ne sia: i.
5 ó sì wí fún wọn pé, “Ẹ kọjá lọ ní iwájú àpótí ẹ̀rí Olúwa Ọlọ́run yín sí àárín odò Jordani. Kí olúkúlùkù yín gbé òkúta kọ̀ọ̀kan lé èjìká a rẹ̀, gẹ́gẹ́ bí iye ẹ̀yà àwọn ọmọ Israẹli,
E da ilima amane sia: i, “Dilia Hina Gode Ea Gousa: su Sema Gagili amo bisili, Yodane Hano amo ganodini masa. Dilia afae afae igi gisa masa. Amo da Isala: ili fi fagoyale gala afae afae igi afae gala.
6 kí ó sì jẹ́ àmì láàrín yín. Ní ọjọ́ iwájú, nígbà tí àwọn ọmọ yín bá béèrè lọ́wọ́ yín pé, ‘Kí ni òkúta wọ̀nyí dúró fún?’
Amo igi ba: sea, Isala: ili dunu da Hina Gode Ea hamoi amo bu dawa: mu. Hobea, dilia mano da amo igi gilisi ea bai amo dilima adole ba: sea,
7 Nígbà náà ni ẹ̀yin yóò dá wọn lóhùn pé, nítorí a gé omi odò Jordani kúrò ní iwájú àpótí ẹ̀rí Olúwa. Nígbà tí a rékọjá a Jordani, a gé omi Jordani kúrò. Àwọn òkúta wọ̀nyí yóò sì jẹ́ ìrántí fún àwọn ọmọ Israẹli láéláé.”
dilia da amo bai olelemu, amo Isala: ili fi amola Hina Gode Ea Gousa: su Sema Gagili da hano degemusa: dawa: loba, hano ea ahoabe da yolesi dagoi. Isala: ili dunu da amo igi ba: sea, ilia da guiguda: hou amo dawa: lalumu.”
8 Báyìí ni àwọn ọmọ Israẹli sì ṣe bí Joṣua ti pàṣẹ fún wọn. Wọ́n gbé òkúta méjìlá láti àárín odò Jordani gẹ́gẹ́ bí iye ẹ̀yà àwọn ọmọ Israẹli, bí Olúwa ti sọ fún Joṣua; wọ́n sì rù wọ́n kọjá lọ sí ibùdó, ní ibi tí wọ́n ti gbé wọn kalẹ̀.
Dunu ilegei da Yosiua ea sia: nabi. Hina Gode da Yosiuama sia: i amo defele, ilia da igi fagoyale gala (Isala: ili fi afae afae igi afae gala) amo Yodane Hano dogoa lale, ilia golamu sogebi amoga gisa asili ligisi.
9 Joṣua sì to òkúta méjìlá náà sí àárín odò Jordani fún ìrántí ní ọ̀kánkán ibi tí àwọn àlùfáà tí ó ru àpótí ẹ̀rí dúró sí. Wọ́n sì wà níbẹ̀ di òní yìí.
Amola Yosiua da igi fagoyale gala eno amo gobele salasu ilia Gode Ea Gousa: su Sema Gagili gaguli lelu sogebi Yodane Hano dogoa amoga legesu. (Amo igi da wali amogawi diala.)
10 Àwọn àlùfáà tí ó ru àpótí náà dúró ní àárín Jordani títí gbogbo nǹkan tí Olúwa pàṣẹ fún Joṣua fi di ṣíṣe nípasẹ̀ àwọn ènìyàn, gẹ́gẹ́ bí Mose ti pàṣẹ fún Joṣua. Àwọn ènìyàn náà sì yára kọjá,
Gobele salasu dunu da Yodane Hano dogoa liligi huluane Hina Gode da Yosiua Isala: ili dunuma hamoma: ne sia: i, amo hamoi dagoi. Ilia da Yodane Hano dogoa ba: musa: lelu. Mousese da amo hou hamoma: ne sia: i. Dunu huluane da hedolo degei dagoi.
11 bí gbogbo wọn sì ti rékọjá tán, ni àpótí ẹ̀rí Olúwa àti àwọn àlùfáà wá sí òdìkejì. Bí àwọn ènìyàn sì ti ń wò wọ́n.
Ilia da huluane na: iyado bega: doaga: loba, gobele salasu dunu da dunu eno bisili, Hina Gode Ea Gousa: su Sema Gagili amo gaguli asi.
12 Àwọn ọkùnrin Reubeni, Gadi àti ìdajì ẹ̀yà Manase náà sì rékọjá ní ìhámọ́ra ogun níwájú àwọn ọmọ Israẹli, gẹ́gẹ́ bí Mose ti pàṣẹ fún wọn.
Mousese ea sia: i defele, Liubene fi, Ga: de fi amola Mana: se fi la: idi ilia da gegesu liligi gaguli, dunu eno bisili degei.
13 Àwọn bí ọ̀kẹ́ méjì tó ti múra fún ogun rékọjá lọ ní iwájú Olúwa sí pẹ̀tẹ́lẹ̀ Jeriko láti jagun.
Hina Gode ba: ma: ne dunu 40,000 ilia gegesu liligi gaguli, Yodane Hano degele, umi soge Yeligou moilai bai bagade gadenene amoga doaga: i.
14 Ní ọjọ́ náà ni Olúwa gbé Joṣua ga ní ojú gbogbo àwọn ọmọ Israẹli, wọ́n sì bẹ̀rù u rẹ̀ ní gbogbo ọjọ́ ayé e wọn, gẹ́gẹ́ bí wọ́n ti bẹ̀rù Mose.
Hina Gode da amo eso hou hamobeba: le, Isala: ili dunu da Yosiua da gasa bagade mimogo dunu dawa: i. E da esalea, ilia da Mousesema dawa: i defele, Yosiuama nodosu.
15 Olúwa sì sọ fún Joṣua pé,
Amalalu, Hina Gode da Yosiuama amane sia: i,
16 “Pàṣẹ fún àwọn àlùfáà tí o ń ru àpótí ẹ̀rí, kí wọn kí ó jáde kúrò nínú odò Jordani.”
“Gobele salasu dunu amo da Gode Ea Gousa: su Sema Gagili gaguli ahoa, ilima ilia da Yodane Hano fisili osoboga heda: ma: ne sia: ma.”
17 Bẹ́ẹ̀ ni Joṣua pàṣẹ fún àwọn àlùfáà pé, “Ẹ jáde kúrò nínú odò Jordani.”
Yosiua da agoane sia: i.
18 Àwọn àlùfáà náà jáde láti inú odò pẹ̀lú àpótí ẹ̀rí Olúwa ni orí wọn. Bí wọ́n ti fi ẹsẹ̀ ẹ wọn tẹ orí ilẹ̀ gbígbẹ ni omi Jordani náà padà sí ààyè e rẹ̀, o sì kún wọ bèbè bí i ti àtẹ̀yìnwá.
Gobele salasu dunu da hano bega: doaga: le heda: loba, hano da bu ahoasu amola bu bagade nedei.
19 Ní ọjọ́ kẹwàá oṣù kìn-ín-ní àwọn ènìyàn náà lọ láti Jordani, wọ́n sì dúró ní Gilgali ní ìlà-oòrùn Jeriko.
Eso nabuga amola oubi age amoga, Isala: ili dunu da Yodane Hano degele, Giliga: le soge (Yeligou moilai bai bagade amo ea eso mabadi la: idi gala) amoga ilia abula diasu gaguli gagai.
20 Joṣua sì to àwọn òkúta méjìlá tí wọ́n mú jáde ní Jordani jọ ní Gilgali.
Amogawi Yosiua da igi fagoyale gala e Yodane Hanoga lai, amo legei.
21 Ó sì sọ fún àwọn ará Israẹli, “Ní ọjọ́ iwájú nígbà tí àwọn ọmọ yín bá béèrè ní ọwọ́ baba wọn pé, ‘Kín ni òkúta wọ̀nyí dúró fún?’
E da Isala: ili dunuma amane sia: i, “Hobea dilia mano da amo igi ilia bai dilima adole ba: sea,
22 Nígbà náà ni ẹ ó jẹ́ kí àwọn ọmọ yín mọ̀ pé, ‘Israẹli rékọjá odò Jordani ní orí ilẹ̀ gbígbẹ.’
dilia da esoha amoga Isala: ili dunu da Yodane Hano amo osobo hafoga: i amoga degei ilima olelema.
23 Nítorí Olúwa Ọlọ́run yín mú Jordani gbẹ ní iwájú u yín títí ẹ̀yin fi kọjá. Olúwa Ọlọ́run yín ti ṣe sí Jordani gẹ́gẹ́ bí ó ti ṣe sí Òkun Pupa, nígbà tí ó mú un gbẹ ní iwájú wa títí àwa fi kọjá.
Dilia Hina Gode da Maga: me Hano Wayabo amo hafoga: i, amo defele Yodane Hano dili degema: ne hafoga: i, amo ilima olelema.
24 Ó ṣe èyí kí gbogbo ayé lè mọ̀ pé ọwọ́ Olúwa ní agbára, àti kí ẹ̀yin kí ó lè máa bẹ̀rù Olúwa Ọlọ́run yín ní ìgbà gbogbo.”
Amo hou ba: beba: le, osobo bagade fifi asi gala huluane da Hina Gode Ea gasa bagade hou dawa: mu, amola dilia da mae fisili eso huluane dilia Hina Godema nodonanumu.”

< Joshua 4 >