< Joshua 19 >
1 Kèké kejì jáde fún ẹ̀yà Simeoni, ní agbo ilé, ní agbo ilé. Ìní wọn sì wà ní àárín ilẹ̀ Juda.
E saiu a segunda sorte por Simeão, pela tribo dos filhos de Simeão, segundo as suas famílias: e foi a sua herança no meio da herança dos filhos de Judá.
2 Lára ìpín wọn ní: Beerṣeba (tàbí Ṣeba), Molada,
E tiveram na sua herança: Beer-seba, e Seba, e Molada,
3 Hasari-Ṣuali, Bala, Esemu,
E Hassar-sual, e Bala, e Asem,
4 Eltoladi, Betuli, Horma,
E Eltholad, e Bethul, e Horma,
5 Siklagi, Beti-Markaboti, Hasari Susa,
E Siklag, e Beth-hammarcaboth, e Hassar-susa,
6 Beti-Lebaoti àti Ṣarueli, ìlú wọn jẹ́ mẹ́tàlá àti ìletò wọn.
E Beth-lebaoth, e Saruhen: treze cidades e as suas aldeias.
7 Aini, Rimoni, Eteri àti Aṣani, ìlú wọn jẹ́ mẹ́rin àti ìletò wọn,
Ain, e Rimmon, e Ether, e Asan: quatro cidades e as suas aldeias.
8 àti gbogbo àwọn agbègbè ìlú wọ̀nyí títí dé Baalati-Beeri (Rama ní gúúsù). Èyí ni ilẹ̀ ìní ẹ̀yà àwọn ọmọ Simeoni, agbo ilé, ní agbo ilé.
E todas as aldeias que havia em redor destas cidades, até Baalath-beer, que é Ramath do sul: esta é a herança da tribo dos filhos de Simeão, segundo as suas famílias.
9 A mú ogún ìní àwọn ọmọ Simeoni láti ìpín Juda, nítorí ìpín Juda pọ̀ ju èyí tí wọ́n nílò lọ. Báyìí ni àwọn ọmọ Simeoni gba ìní wọn ní àárín ilẹ̀ Juda.
A herança dos filhos de Simeão está entre o quinhão dos de Judá; porquanto a herança dos filhos de Judá era demasiadamente grande para eles: pelo que os filhos de Simeão tiveram a sua herança no meio deles.
10 Kèké kẹta jáde fún Sebuluni, ní agbo ilé ní agbo ilé ààlà ìní wọn sì lọ títí dé Saridi.
E saiu a terceira sorte pelos filhos de Zebulon, segundo as suas famílias: e foi o termo da sua herança até Sarid.
11 Ó sì lọ sí ìwọ̀-oòrùn ní Marala, ó sì dé Dabbeṣeti, ó sì lọ títí dé odo ní ẹ̀bá Jokneamu.
E sobe o seu termo pelo ocidente a Marala, e chega até Dabbeseth: chega também até ao ribeiro que está defronte de Jokneam.
12 Ó sì yípadà sí ìlà-oòrùn láti Saridi sí ìhà ìlà-oòrùn dé ilẹ̀ Kisiloti-Tabori, ó sì lọ sí Daberati, ó sì gòkè lọ sí Jafia.
E de Sarid volta para o oriente, para o nascente do sol, até ao termo de Chisloth-tabor, e sai a Dobrath, e vai subindo a Japhia.
13 Nígbà náà ní o lọ sí ìhà ìlà-oòrùn lọ sí Gati-Heferi àti Eti-Kaṣini, ó sì jáde ní Rimoni, ó sì yí sí ìhà Nea.
E dali passa pelo oriente para o nascente, a Gath-hepher, em Ethcasin; e sai a Rimmon-methoar, que é Nea.
14 Ní ibẹ̀, ààlà sì yíká ní ìhà àríwá lọ sí Hnatoni ó sì pín ní àfonífojì Ifita-Eli.
E torna este termo para o norte a Hannathon: e as suas saídas são o vale de Iphtah-el,
15 Lára wọn ni Katati, Nahalali, Ṣimroni, Idala àti Bẹtilẹhẹmu. Wọ́n sì jẹ́ ìlú méjìlá àti ìletò wọn.
E Cattath, e Nahalal, e Simron, e Idala, e Beth-lehem: doze cidades e as suas aldeias.
16 Ìlú wọ̀nyí àti ìletò wọn jẹ́ ìní Sebuluni, ní agbo ilé agbo ilé.
Esta é a herança dos filhos de Zebulon, segundo as suas famílias: estas cidades e as suas aldeias.
17 Kèké kẹrin jáde fún Isakari, agbo ilé ní agbo ilé.
A quarta sorte saiu por Issacar: pelos filhos de issacar, segundo as suas famílias.
18 Lára ilẹ̀ wọn ni èyí: Jesreeli, Kesuloti, Ṣunemu,
E foi o seu termo Jezreela, e Chesulloth, e Sunem,
19 Hafraimu, Ṣihoni, Anaharati,
E Hapharaim. e Sion, e Anacarath,
20 Rabiti, Kiṣioni, Ebesi,
E Rabbith, e Kision, e Ebes,
21 Remeti, Eni-Gannimu, Eni-Hada àti Beti-Pasesi.
E Remeth, e En-gannim, e En-Hadda, e Beth-patses.
22 Ààlà náà sì dé Tabori, Ṣahasuma, àti Beti-Ṣemeṣi, ó sì pin ní Jordani. Wọ́n sì jẹ́ ìlú mẹ́rìndínlógún àti ìletò wọn.
E chega este termo até Tabor, e Sahasima, e Beth-semes; e as saídas do seu termo estão para o Jordão: dezeseis cidades e as suas aldeias.
23 Ìlú wọ̀nyí àti ìletò wọn jẹ́ ìní ẹ̀yà Isakari, ní agbo ilé agbo ilé.
Esta é a herança da tribo dos filhos de issacar, segundo as suas famílias: estas cidades e as suas aldeias.
24 Kèké karùn-ún jáde fún ẹ̀yà Aṣeri, ní agbo ilé agbo ilé.
E saiu a quinta sorte pela tribo dos filhos de Aser, segundo as suas famílias.
25 Lára ilẹ̀ wọn ni èyí: Helikati, Hali, Beteni, Akṣafu,
E foi o seu termo Helkath, e Hali, e Beten, e Acsaph,
26 Allameleki, Amadi, àti Miṣali. Ní ìhà ìwọ̀-oòrùn ààlà náà dé Karmeli àti Ṣihori-Libinati.
E Alammelech, e Amad, e Misal: e chega a Carmel para o ocidente, e a Sihor-libnath;
27 Nígbà náà ni o yí sí ìhà ìlà-oòrùn Beti-Dagoni, dé Sebuluni àti àfonífojì Ifita-Eli, ó sì lọ sí àríwá sí Beti-Emeki àti Neieli, ó sì kọjá lọ sí Kabulu ní apá òsì.
E volta do nascente do sol a beth-dagOn, e chega a Zebulon e ao vale de Iphtah-el, ao norte de Beth-emek e de Neiel, e vem sair a Cabul pela esquerda,
28 Ó sì lọ sí Abdoni, Rehobu, Hammoni àti Kana títí dé Sidoni ńlá.
E Ebron, e Rehob, e Hammon, e Cana, até à grande Sidon.
29 Ààlà náà sì tẹ̀ sí ìhà Rama, ó sì lọ sí ìlú olódi Tire, ó sì yà sí Hosa, ó sì jáde ní Òkun Ńlá ní ilẹ̀ Aksibu,
E volta este termo a Rama, e até à forte cidade de Tiro: então torna este termo a Hosa, e as suas saídas estão para o mar, desde o quinhão da terra até Achzib;
30 Uma, Afeki àti Rehobu. Wọ́n sì jẹ́ ìlú méjìlélógún àti ìletò wọn.
E Uma, e Aphek, e Rechob: vinte e duas cidades e as suas aldeias.
31 Àwọn ìlú wọ̀nyí àti ìletò wọn ní ìní ẹ̀yà Aṣeri, ní agbo ilé agbo ilé.
Esta é a herança da tribo dos filhos de Aser, segundo as suas famílias: estas cidades e as suas aldeias.
32 Ìpín kẹfà jáde fún Naftali, agbo ilé ní agbo ilé,
E saiu a sexta sorte pelos filhos de Naphtali; para os filhos de Naphtali, segundo as suas famílias.
33 ààlà wọn lọ láti Helefi àti igi ńlá ní Saananimu nímù; kọjá lọ sí Adami Nekebu àti Jabneeli dé Lakkumu, ó sì pín ní Jordani.
E foi o seu termo desde Heleph e desde Allon em Saanannim, e Adami, Nekeb, e Jabneel, até Lakum: e estão as suas saídas no Jordão.
34 Ààlà náà gba ìhà ìwọ̀-oòrùn lọ sí Asnoti-Tabori ó sì jáde ní Hukoki. Ó sì dé Sebuluni, ní ìhà gúúsù Aṣeri ní ìhà ìwọ̀-oòrùn àti Juda ní Jordani ní ìhà ìlà-oòrùn.
E volta este termo pelo ocidente a Azmoth-tabor, e dali passa a Huccok: e chega a Zebulon para o sul, e chega a Aser para o ocidente, e a Judá pelo Jordão, para o nascente do sol.
35 Àwọn ìlú olódi sì Siddimu, Seri, Hamati, Rakàti, Kinnereti,
E são as cidades fortes: Siddim, Ser, e Hammath, Raccath, e Chinnereth,
E Adama, e Rama, e Hasor,
37 Kedeṣi, Edrei, Eni-Aṣọri,
E Kedes, e Edrei, e En-hazor,
38 Ironi, Migdali-Eli, Horemu, Beti-Anati àti Beti-Ṣemeṣi. Wọ́n sì jẹ́ ìlú mọ́kàndínlógún àti ìletò wọn.
E Iron, e Migdal-el, Horem, e Beth-anath, e Beth-semes: dezenove cidades e as suas aldeias.
39 Àwọn ìlú wọ̀nyí àti ìletò wọn ní ìní ẹ̀yà Naftali, ní agbo ilé sí agbo ilé.
Esta é a herança da tribo dos filhos de Naphtali, segundo as suas famílias: estas cidades e as suas aldeias.
40 Ìbò kéje jáde fún ẹ̀yà Dani, ní agbo ilé ní agbo ilé.
A sétima sorte saiu pela tribo dos filhos de Dan, segundo as suas famílias.
41 Ilẹ̀ ìní wọn nìwọ̀nyí: Sora, Eṣtaoli, Iri-Ṣemesi,
E foi o termo da sua herança, Sora, e Estaol, e Ir-semes,
42 Ṣaalabini, Aijaloni, Itila,
E Saalabbin, e Ayalon, e Ithla,
E Elon, e Timnath, e Ekron,
44 Elteke, Gibetoni, Baalati,
E Elteke, e Gibthon, e Baalath,
45 Jehudu, Bene-Beraki, Gati-Rimoni,
E Jehud, e Bene-berak, e Gath-rimmon,
46 Me Jakoni àti Rakkoni, pẹ̀lú ilẹ̀ tí ó kọjú sí Joppa.
E Me-jarcom, e Raccon: com o termo defronte de Japho:
47 (Ṣùgbọ́n àwọn ará Dani ní ìṣòro láti gba ilẹ̀ ìní wọn, bẹ́ẹ̀ ni wọ́n gòkè lọ, wọ́n sì kọlu Leṣemu, wọ́n sì gbà á, wọ́n sì fi idà kọlù ú, wọ́n sì ń gbé ibẹ̀. Wọ́n sì ń gbé ní Leṣemu, wọ́n sì pe orúkọ rẹ̀ ní Dani orúkọ baba ńlá wọn).
Saiu porém pequeno o termo aos filhos de Dan: pelo que subiram os filhos de Dan, e pelejaram contra Lesem, e a tomaram, e a feriram ao fio da espada, e a possuiram e habitaram nela, e a Lesem chamaram Dan, conforme ao nome de Dan seu pai.
48 Àwọn ìlú wọ́n yí àti ìletò wọn ní ìní ẹ̀yà Dani, ní agbo ilé agbo ilé.
Esta é a herança da tribo dos filhos de Dan, segundo as suas famílias; estas cidades e as suas aldeias.
49 Nígbà tí wọ́n ti parí pínpín ilẹ̀ náà ní ìpín ti olúkúlùkù, àwọn ará Israẹli fún Joṣua ọmọ Nuni ní ìní ní àárín wọn,
Acabando pois de repartir a terra em herança segundo os seus termos, deram os filhos de Israel a Josué, filho de Nun, herança no meio deles.
50 bí Olúwa ti pàṣẹ, wọ́n fún un ni ìlú tí ó béèrè fún, Timnati Serah ní ìlú òkè Efraimu. Ó sì kọ́ ìlú náà, ó sì ń gbé ibẹ̀.
Segundo o dito do Senhor lhe deram a cidade que pediu, a Timnath-serah, na montanha de Ephraim: e reedificou aquela cidade, e habitou nela.
51 Wọ̀nyí ni àwọn ilẹ̀ tí Eleasari àlùfáà, Joṣua ọmọ Nuni àti àwọn olórí ẹ̀yà agbo ilé Israẹli fi ìbò pín ní Ṣilo ní iwájú Olúwa ní ẹnu-ọ̀nà àgọ́ ìpàdé. Báyìí ni wọ́n parí pínpín ilẹ̀ náà.
Estas são as heranças que Eleazar o sacerdote, e Josué filho de Nun, e os Cabeças dos pais das famílias por sorte em herança repartiram às tribos dos filhos de Israel em Silo, perante o Senhor, à porta da tenda da congregação. E assim acabaram de repartir a terra.