< Joshua 19 >

1 Kèké kejì jáde fún ẹ̀yà Simeoni, ní agbo ilé, ní agbo ilé. Ìní wọn sì wà ní àárín ilẹ̀ Juda.
Nitsatok’ amy Simone ty tsapake faha-roe ho a i fifokoa’ i Simoney ty amo hasavereña’eo; le añivo’ ty lova’ o ana’ Iehodao ty lova’ iareo.
2 Lára ìpín wọn ní: Beerṣeba (tàbí Ṣeba), Molada,
Aa le ty lova’ iareo: i Beer-seva, naho i Sebà, naho i Moladà;
3 Hasari-Ṣuali, Bala, Esemu,
naho i Hatsar-soale, naho i Balà naho i Atseme,
4 Eltoladi, Betuli, Horma,
naho i Eltolade, naho i Betole, naho i Kormà,
5 Siklagi, Beti-Markaboti, Hasari Susa,
naho i Tsiklage, naho i Bete-markabote, naho i Katsàre-sosà,
6 Beti-Lebaoti àti Ṣarueli, ìlú wọn jẹ́ mẹ́tàlá àti ìletò wọn.
naho i Bete-lebaote, vaho i Sarohene: rova folo-telo’ amby rekets’ o tanà’eo.
7 Aini, Rimoni, Eteri àti Aṣani, ìlú wọn jẹ́ mẹ́rin àti ìletò wọn,
I Aine, i Remone, naho i Etere vaho i Asane; rova efatse rekets’ o tanà’eo,
8 àti gbogbo àwọn agbègbè ìlú wọ̀nyí títí dé Baalati-Beeri (Rama ní gúúsù). Èyí ni ilẹ̀ ìní ẹ̀yà àwọn ọmọ Simeoni, agbo ilé, ní agbo ilé.
naho ze tanàñe mañohoke i rova rey pake Baal-atbeere, i Ramate’ i Atimoy. Ie ty lovam-pifokoan’ ana’ i Simoneo ty amo hasavereña’eo.
9 A mú ogún ìní àwọn ọmọ Simeoni láti ìpín Juda, nítorí ìpín Juda pọ̀ ju èyí tí wọ́n nílò lọ. Báyìí ni àwọn ọmọ Simeoni gba ìní wọn ní àárín ilẹ̀ Juda.
Nandivàñe amy anjara’ o ana’ Iehodao ty lova’ o ana’ i Simoneo; amy te niloho bey ama’e ty anjara’ Iehoda; aa le tañivo’ ty lova’ iareo ao ty lova’ o ana’ i Simoneo.
10 Kèké kẹta jáde fún Sebuluni, ní agbo ilé ní agbo ilé ààlà ìní wọn sì lọ títí dé Saridi.
Nitsatok’ amo ana’ i Zeboloneo ty tsapake faha-telo ty amo hasavereña’eo, le nahatakatse i Saride ty efe’ i lova’ iareoy.
11 Ó sì lọ sí ìwọ̀-oòrùn ní Marala, ó sì dé Dabbeṣeti, ó sì lọ títí dé odo ní ẹ̀bá Jokneamu.
Mionjoñe mb’amy riakey naho mb’e Maralà mb’eo i efetsey pake Dabasete vaho mitakatse i saka aolo’ Iok­neamey;
12 Ó sì yípadà sí ìlà-oòrùn láti Saridi sí ìhà ìlà-oòrùn dé ilẹ̀ Kisiloti-Tabori, ó sì lọ sí Daberati, ó sì gòkè lọ sí Jafia.
miolake boake Saride re maniñanañe mb’ amy fanjiriha’ i àndroy mb’eo pak’ amy efe’ i Kislotabore vaho miakatse mb’e Daberate naho mañambone mb’e Iafià,
13 Nígbà náà ní o lọ sí ìhà ìlà-oòrùn lọ sí Gati-Heferi àti Eti-Kaṣini, ó sì jáde ní Rimoni, ó sì yí sí ìhà Nea.
boak’ao re manonjohy maniñana pake Gita-kefere naho i Eta-katsine mb’eo vaho miakatse mb’e Remone-metoare mb’e Neà añe;
14 Ní ibẹ̀, ààlà sì yíká ní ìhà àríwá lọ sí Hnatoni ó sì pín ní àfonífojì Ifita-Eli.
miary avara’e eo i efetsey pake Kanatone vaho mandoak’ am-bavatane’ Iiftakèle eo;
15 Lára wọn ni Katati, Nahalali, Ṣimroni, Idala àti Bẹtilẹhẹmu. Wọ́n sì jẹ́ ìlú méjìlá àti ìletò wọn.
mitraok’ ao ty Katàte naho i Nahalàle, naho i Simrone, naho Idalà vaho i Betlekheme: rova folo-ro’ amby naho o tanà’eo.
16 Ìlú wọ̀nyí àti ìletò wọn jẹ́ ìní Sebuluni, ní agbo ilé agbo ilé.
Izay ty lova’ o ana’ i Zeboloneo ty amo hasavereña’eo, i rova rey naho o tanà’eo.
17 Kèké kẹrin jáde fún Isakari, agbo ilé ní agbo ilé.
Nitsatok’ amy Isakhare ty tsapake fah’ efetsee, ho a o ana’ Isakhareo ty amo hasavereña’eo.
18 Lára ilẹ̀ wọn ni èyí: Jesreeli, Kesuloti, Ṣunemu,
Ty efe’ iareo le pake Iizreele, naho i Kesolote naho i Soneme,
19 Hafraimu, Ṣihoni, Anaharati,
naho i Kafaraime, naho i Sione, naho i Anakarate,
20 Rabiti, Kiṣioni, Ebesi,
naho i Rabite, naho i Kisione, naho i Ebetse,
21 Remeti, Eni-Gannimu, Eni-Hada àti Beti-Pasesi.
naho i Remete, naho i En-ganime, naho i En-kadà, vaho i Bete-pats’tsatese;
22 Ààlà náà sì dé Tabori, Ṣahasuma, àti Beti-Ṣemeṣi, ó sì pin ní Jordani. Wọ́n sì jẹ́ ìlú mẹ́rìndínlógún àti ìletò wọn.
mahatakatse i Tabore i efetsey naho i Sakatsome naho i Bete-semese; le mandoak’ am’ Iardeney i efe’ iareoy; rova folo-eneñ’ amby rekets’ o tanà’eo.
23 Ìlú wọ̀nyí àti ìletò wọn jẹ́ ìní ẹ̀yà Isakari, ní agbo ilé agbo ilé.
Ie ty lovam-pifokoa’ o ana’ Isakhareo ty amo hasavereña’eo; i rova rey rekets’ o tanà’eo.
24 Kèké karùn-ún jáde fún ẹ̀yà Aṣeri, ní agbo ilé agbo ilé.
Nitsatok’ amy fifokoa’ o ana’ i Asereoy i tsapake faha-limey ty amo hasavereña’eo.
25 Lára ilẹ̀ wọn ni èyí: Helikati, Hali, Beteni, Akṣafu,
Ty efe’ iareo le i Kelkate, naho i Kalý, naho i Betene, naho i Aksafe,
26 Allameleki, Amadi, àti Miṣali. Ní ìhà ìwọ̀-oòrùn ààlà náà dé Karmeli àti Ṣihori-Libinati.
naho i Alame­leke, naho i Amade, naho i Miseale, naho mitakatse i Karmele ahandrefa’e añe vaho mb’e Sikore-libnate mb’eo;
27 Nígbà náà ni o yí sí ìhà ìlà-oòrùn Beti-Dagoni, dé Sebuluni àti àfonífojì Ifita-Eli, ó sì lọ sí àríwá sí Beti-Emeki àti Neieli, ó sì kọjá lọ sí Kabulu ní apá òsì.
miolake mb’amy fanjiriha’ i àndroy re pake Bete-dagone le mahatakatse i Zebolone naho i vava­tane’ Iiftakèy le mañavaratse, mb’e Bete-meke, naho i Neiele vaho mandoake e Kabole am-pitàn-kavia eo,
28 Ó sì lọ sí Abdoni, Rehobu, Hammoni àti Kana títí dé Sidoni ńlá.
naho i Abrane, naho i Rekobe, naho i Kamone vaho i Kanà, pake Tsidone bey;
29 Ààlà náà sì tẹ̀ sí ìhà Rama, ó sì lọ sí ìlú olódi Tire, ó sì yà sí Hosa, ó sì jáde ní Òkun Ńlá ní ilẹ̀ Aksibu,
miolake mb’amy Kormà amy zao i efetsey naho mb’an-drova fatratse atao Tsore; miolake mb’ amy Kosà amy zao i efetsey vaho mandoak’ amy riakey; boake Hebel pak’ Akzibe,
30 Uma, Afeki àti Rehobu. Wọ́n sì jẹ́ ìlú méjìlélógún àti ìletò wọn.
naho i Omà, naho i Afeke, vaho i Rehobe: rova roa-polo-ro’ amby rekets’ o tanà’eo.
31 Àwọn ìlú wọ̀nyí àti ìletò wọn ní ìní ẹ̀yà Aṣeri, ní agbo ilé agbo ilé.
Ie ty lovam-pifokoan’ ana’ i Asere ty amo hasavereña’eo, i rova rey vaho o tanà’eo.
32 Ìpín kẹfà jáde fún Naftali, agbo ilé ní agbo ilé,
Nitsatok’ amo ana’ i Naftalio i tsapake faha-eneñey, ho a o ana’ i Naftalio ty amo hasavereña’eo.
33 ààlà wọn lọ láti Helefi àti igi ńlá ní Saananimu nímù; kọjá lọ sí Adami Nekebu àti Jabneeli dé Lakkumu, ó sì pín ní Jordani.
Ty efe-tane’ iareo le boake Kelefe amy sarongaza’ i Tsànanimey, naho i Adamý, i Nekebe, naho Iagnile, pake Lakome le mandoak’ am’ Iardeney
34 Ààlà náà gba ìhà ìwọ̀-oòrùn lọ sí Asnoti-Tabori ó sì jáde ní Hukoki. Ó sì dé Sebuluni, ní ìhà gúúsù Aṣeri ní ìhà ìwọ̀-oòrùn àti Juda ní Jordani ní ìhà ìlà-oòrùn.
miolake mañandrefa amy zao i efetsey mb’ Aznote-tabore naho miranga mb’e Kokoke le mahatakatse i Zebolone atimo’e naho mitakatse i Asere ahandrefañe añe vaho am’ Iehodà mb’am-panjiriha’ i àndroy mb’ am’ Iardeney mb’eo.
35 Àwọn ìlú olódi sì Siddimu, Seri, Hamati, Rakàti, Kinnereti,
O rova’ iareo fatratseo le i Tsidime, i Tsare, naho i Kamate, i Rakate, vaho i Kinerete,
36 Adama, Rama Hasori,
naho i Adamà naho i Ramà, naho i Katsore,
37 Kedeṣi, Edrei, Eni-Aṣọri,
naho i Kedese, naho i Edreý, naho i En-katsore,
38 Ironi, Migdali-Eli, Horemu, Beti-Anati àti Beti-Ṣemeṣi. Wọ́n sì jẹ́ ìlú mọ́kàndínlógún àti ìletò wọn.
naho Irone, naho i Migdal’El, naho i Koreme, naho i Betanate vaho i Bete-semese: rova folo-sive’ amby rekets’ o tanà’eo.
39 Àwọn ìlú wọ̀nyí àti ìletò wọn ní ìní ẹ̀yà Naftali, ní agbo ilé sí agbo ilé.
Ie ty lovam-pifokoan’ ana’ i Naftaliy ty amo hasavereña’eo; i rova rey rekets’ o tanà’eo.
40 Ìbò kéje jáde fún ẹ̀yà Dani, ní agbo ilé ní agbo ilé.
Nitsatok’ am-pifokoan’ ana’ i Dane ty tsapake faha-fito ty amo hasavereña’eo.
41 Ilẹ̀ ìní wọn nìwọ̀nyí: Sora, Eṣtaoli, Iri-Ṣemesi,
Ty efe-tane’ iareo le i Tsorà, naho i Estaole, naho Ire-semese,
42 Ṣaalabini, Aijaloni, Itila,
naho i Saal-bine, naho i Aialone, naho Ietelà,
43 Eloni, Timna, Ekroni,
naho i Elone, naho i Timnatà, naho i Ekrone,
44 Elteke, Gibetoni, Baalati,
naho i Eltekè, naho i Gibetone, naho i Baalate,
45 Jehudu, Bene-Beraki, Gati-Rimoni,
naho Iehoda, naho i Bene-berake, naho i Gatrimone,
46 Me Jakoni àti Rakkoni, pẹ̀lú ilẹ̀ tí ó kọjú sí Joppa.
naho i Me-iarkone, vaho i Rakone, rekets’ i tane aolo’ Iafòy.
47 (Ṣùgbọ́n àwọn ará Dani ní ìṣòro láti gba ilẹ̀ ìní wọn, bẹ́ẹ̀ ni wọ́n gòkè lọ, wọ́n sì kọlu Leṣemu, wọ́n sì gbà á, wọ́n sì fi idà kọlù ú, wọ́n sì ń gbé ibẹ̀. Wọ́n sì ń gbé ní Leṣemu, wọ́n sì pe orúkọ rẹ̀ ní Dani orúkọ baba ńlá wọn).
Tsy niampe ty nitakara’ ty efe-tane’ i Dane; aa le nionjoñe haname i Leseme o ana’ i Daneo le tinava’ iereo naho linafa’ iareo an-dela-pibara naho nanoe’ iereo fanañañe vaho nimoneñe ao; natao iereo Dane ty Leseme ty amy Dane rae’ iareoy.
48 Àwọn ìlú wọ́n yí àti ìletò wọn ní ìní ẹ̀yà Dani, ní agbo ilé agbo ilé.
Ie ty lova’ o ana’ i Dane ty amo hasavereña’eoo, i rova’e rey naho o tanà’eo.
49 Nígbà tí wọ́n ti parí pínpín ilẹ̀ náà ní ìpín ti olúkúlùkù, àwọn ará Israẹli fún Joṣua ọmọ Nuni ní ìní ní àárín wọn,
Aa ie nihenefe’ iareo ty fizarañe i taney ho lova ty amo efe’eo, le tinolo’ o ana’ Israeleo lova añivo’ iareo ao t’Iehosoa ana’ i None;
50 bí Olúwa ti pàṣẹ, wọ́n fún un ni ìlú tí ó béèrè fún, Timnati Serah ní ìlú òkè Efraimu. Ó sì kọ́ ìlú náà, ó sì ń gbé ibẹ̀.
le natolo’ iareo aze i rova niha­lalie’ey ty amy tsara’ Iehovày; i Timna­tserà am-bohi’ i Efraime ey; le namboare’e i rovay vaho nimoneña’e.
51 Wọ̀nyí ni àwọn ilẹ̀ tí Eleasari àlùfáà, Joṣua ọmọ Nuni àti àwọn olórí ẹ̀yà agbo ilé Israẹli fi ìbò pín ní Ṣilo ní iwájú Olúwa ní ẹnu-ọ̀nà àgọ́ ìpàdé. Báyìí ni wọ́n parí pínpín ilẹ̀ náà.
Izay o lova zinara’ i Ela­zare mpisoroñe naho Iehosoa ana’ i Noneo naho o talem-pifokoa’ o ana’ Israeleoo, ho lova an-tsapake e Silò añatrefa’ Iehovà, an-dala’i kibohom-pamantañañey. Aa le nihenefe’ iareo i zara-taney.

< Joshua 19 >