< Joshua 15 >
1 Ìpín fún ẹ̀yà Juda, ní agbo ilé agbo ilé, títí dé agbègbè Edomu, títí dé aginjù Sini ní òpin ìhà gúúsù.
Ty anjara’ i fifokoan’ ana’ Iehoda ty amo hasavereña’eo an-tsapake le pak’ an-tane’ i Edome naho ty fatrambei’ i Tsine mb’ amy Negeve mb’eo ho efe’e atimo.
2 Ààlà wọn ní ìhà gúúsù bẹ̀rẹ̀ láti etí òpin ìhà gúúsù Òkun Iyọ̀,
Ty efe-tane’ iareo atimo, le boak’ añ’ olo’ i Riake Siray hirik’ amy fitolian-dakañe mitolike mañatimoy;
3 ó sì gba gúúsù Akrabbimu lọ, títí dé Sini àti sí iwájú ìhà gúúsù Kadeṣi-Barnea. Nígbà náà ó sì tún kọjá Hesroni lọ sí Adari, ó sì tún yípo yíká lọ sí Karka.
le mb’e Negeve mb’eo pak’amy fitroara’ i Akrabime sikal’ amy Tsine naho mionjomb’ ami’ty ila atimo’ i Kadese-barnea an-kalo’ i Ketsrone naho mionjoñe mb’e Adare vaho mitolike mb’e Karkà mb’eo,
4 Ó tún kọjá lọ sí Asmoni, ó sì papọ̀ mọ́ Wadi ti Ejibiti, ó parí sí Òkun. Èyí ni ààlà wọn ní ìhà gúúsù.
ie boak’ ao le miary mb’e Atsmone vaho miakatse mb’ amy oñe’ i Mitsraimey, le mitakatse i riak’ ahandrefañey i efe’ey. Izay ty efe’o atimo.
5 Ààlà wọn ní ìhà ìlà-oòrùn ní Òkun Iyọ̀ títí dé ẹnu Jordani. Ààlà àríwá bẹ̀rẹ̀ láti etí òkun ní ẹnu Jordani,
I Riake Siray ty efe’e atiñanañe pak’ am’ Iardeney. Le ty efe’e avaratse boak’ am-pitolian-daka’ i riakey, am-binàñe’ Iardeney,
6 ààlà náà sì tún dé Beti-Hogla, ó sì lọ sí ìhà àríwá Beti-Araba. Ààlà náà sì tún dé ibi Òkúta Bohani ti ọmọ Reubeni.
le mitohy mb’e Betehoglà naho miary avara’ i Bete’ arabà; ie boak’ ao mionjomb’ am-bato’ i Bohane, ana’ i Reobene mb’eo i efetsey.
7 Ààlà náà gòkè lọ títí dé Debiri láti àfonífojì Akori, ó sì yípadà sí àríwá Gilgali, èyí tí ń bẹ ní iwájú òkè Adummimu, tí ń bẹ ní ìhà gúúsù odò náà. Ó sì tẹ̀síwájú sí apá omi En-Ṣemeṣi, ó sì jáde sí En-Rogeli.
Mibalike mb’e Debire boak’ am-bavatane’ i Akore i efetsey le mañavaratse, mitolike mb’e Gilgale, aolo’ ty fitroara’ i Adomime, atimo i sakay; miary amo rano’ i Ensemeseo i efetsey vaho miakatse amy rano migoangoa’ i Rogeley,
8 Ààlà náà sì tún gòkè lọ sí àfonífojì Beni-Hinnomu ní ìhà gẹ̀rẹ́gẹ̀rẹ́ gúúsù ti Jebusi (tí í ṣe Jerusalẹmu). Ó sì gòkè lọ sí orí òkè tí ó wà lórí àfonífojì Hinnomu tí ń bẹ ní ìpẹ̀kun àfonífojì Refaimu ní ìhà àríwá.
le mionjomb’ amy vavatanen’ ana’ i Hinome añ’ ila’ i nte-Iebosiý mañatimo; izay t’Ierosalaime, naho manganike mb’ an-dengom-bohitse aolo’ i vavatane’ i Hinomey mañandrefa ami’ty figadoña’ i vavatanen-dRafày, mañavaratse;
9 Ààlà náà sì lọ láti orí òkè lọ sí ìsun omi Nefitoa, ó sì jáde sí ìlú òkè Efroni, ó sì lọ sí apá ìsàlẹ̀ Baalahi (tí í ṣe, Kiriati-Jearimu).
miary ambone’ i vohitsey i efetsey pak’ amy rano migoangoa’ i Neftoà naho miakatse mb’ amo rova’ am-bohi’ i Efroneo mb’eo; le miary Efrone i efetsey pake Baalà; ie i Kiriat-iearime.
10 Ààlà tí ó yípo láti Baalahi lọ sí ìhà ìwọ̀-oòrùn sí òkè Seiri, ó sì lọ sí gẹ̀rẹ́gẹ̀rẹ́ àríwá òkè Jearimu (tí í ṣe, Kesaloni), ó sì sọ̀kalẹ̀ lọ sí Beti-Ṣemeṣi, ó sì kọjá lọ sí Timna.
Ie amy zay miolake boake Baalà mañandrefa pak’ am-bohi-Seire naho miary mb’ añila’ avara’ i vohi’ Iearimey mb’eo—i Kesalone zay, le mizotso mb’e Bete-Semese mb’eo vaho miary mb’e Timnà mb’eo.
11 Ààlà náà sì lọ sí gẹ̀rẹ́gẹ̀rẹ́ àríwá òkè Ekroni, ó sì yípadà lọ sí Ṣikkeroni, ó sì yípadà lọ sí òkè Baalahi, ó sì dé Jabneeli, ààlà náà sì parí sí Òkun.
Le miary añ’ ila’ i Ekrone mañavaratse i efetsey; le miary mb’e Sikrone mb’eo ty efe’e naho mb’ amy Baalà naho miakatse mb’e Iabnile; vaho miakatse mb’ an-driak’ añe i efe’ey.
12 Ààlà ìwọ̀-oòrùn sì jẹ́ agbègbè Òkun Ńlá. Ìwọ̀nyí ni ààlà àyíká ènìyàn Juda ní agbo ilé wọn.
Ty efe’e ahandrefa, le i olon-driake jabajabay. Ie ty efe-tane’ o ana’ Iehodao mb’eo mb’eo ty amo hasavereña’eo.
13 Gẹ́gẹ́ bí àṣẹ tí Olúwa pa fún Joṣua, ó fi ìpín fún Kalebu ọmọ Jefunne, ìpín ní Juda—Kiriati-Arba, tí í ṣe Hebroni. (Arba sì ní baba ńlá Anaki.)
Natolo’e amy Kalebe’ ana’ Iefonè ty ila’ o anjara’ o ana’ Iehodaoo, ty amy nandilia’ Iehovà Iehosoay, rekets’ i Kiriate-Arbà, toe rae’ i Anàke t’i Arbà; ty rova atao Kebrone.
14 Kalebu sì lé àwọn ọmọ Anaki mẹ́ta jáde láti Hebroni; Ṣeṣai, Ahimani, àti Talmai, ìran Anaki.
Natao i Kalebe soike i ana-dahi’ telo’ i Anàke rey: i Sesay naho i Ahimane naho i Talmay, i ana’ i Anàke rey.
15 Ó sì wọ́de ogun láti ibẹ̀ lọ bá àwọn ènìyàn tí ń gbé ní Debiri (tí à ń pè ní Kiriati-Seferi nígbà kan rí).
Ie boak’ ao le nionjomb’ amo mpimone’ i Debireo mb’eo; natao Kiriate-sefere ty añara’ i Debire taolo.
16 Kalebu sì wí pé, “Èmi yóò fi ọmọbìnrin mi Aksa fún ọkùnrin tí ó bá kọlu Kiriati-Seferi, tí ó sì gbà á ní ìgbéyàwó.”
Le hoe t’i Kalebe, Hatoloko amy ze manjevoñe i Kiriate-sefere vaho mahatavañe aze t’i Aksàe anak’ ampelako ho vali’e.
17 Otnieli ọmọ Kenasi, arákùnrin Kalebu, sì gbà á, báyìí ni Kalebu sì fi ọmọbìnrin rẹ̀ Aksa fún un ní ìyàwó.
Aa le tinava’ i Otniele ana’i Kenaze rahalahi’ i Kalebe vaho natolo’e aze t’i Aksae anak’ ampela’e ho tañanjomba’e.
18 Ní ọjọ́ kan, nígbà tí Aksa lọ sí ọ̀dọ̀ Otnieli, ó rọ̀ ọ́ kí ó béèrè ilẹ̀ oko lọ́wọ́ baba rẹ̀. Nígbà náà ni Aksa sọ̀kalẹ̀ ní orí kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ rẹ̀, Kalebu sì béèrè pé, “Kí ni kí èmi ṣe fún ọ?”
Ie amy zao, naho nasese ama’e i ampelay, le nosihe’e ty hihalaly tetek’ aman-drae’e; aa ie nizotso amy borìke’ey, le hoe ty asa’ i Kalebe ama’e: Ino o paia’oo?
19 Ó sì dáhùn pé, “Mo ń fẹ́ kí o ṣe ojúrere kan fún mi, nígbà ti o ti fún mi ní ilẹ̀ ní gúúsù, fún mi ní ìsun omi náà pẹ̀lú.” Kalebu sì fún un ní ìsun òkè àti ìsun ìsàlẹ̀.
Hoe re: Tatao iraho, kanao tinolo’o tane atimo ao, ehe itoloro rano manganahana. Aa le natolo’e aze i Rano Manganahana Amboney naho i Rano Manganahana Ambaney.
20 Èyí ni ilẹ̀ ìní ẹ̀yà àwọn ọmọ Juda gẹ́gẹ́ bi ìdílé wọn.
Zao ty lova ty fifokoa’ Iehoda ty amo hasavereña’eo.
21 Ìlú ìpẹ̀kun gúúsù ti ẹ̀yà Juda ní gúúsù ní ààlà Edomu nìwọ̀nyí: Kabṣeeli, Ederi, Jaguri,
O rovam-pifokoa’ o ana’ Iehodao mañatimo mb’ añ’efe-tane’ Edome mb’eoo le i Kab-tseel naho i Eder naho Iagore
naho i Kinà naho i Dimonà naho i Adadà
23 Kedeṣi, Hasori, Itina,
naho i Kedese naho i Katsore naho Iitnàne;
24 Sifi, Telemu, Bealoti,
i Zife naho i Teleme naho i Bealote
25 Hasori Hadatta, Kerioti Hesroni (tí í ṣe Hasori),
naho i Katsore-kadatà naho i Keriote naho i Ketsrone ze toe Katsore,
i Amame naho i Semà naho i Moladà,
27 Hasari Gada, Heṣmoni, Beti-Peleti,
naho i Katsar-gadà naho i Kesmone naho i Betepalete
28 Hasari-Ṣuali, Beerṣeba, Bisiotia,
naho i Katsar-soale naho i Beersevà naho i Beziotià,
i Baalà naho Iime naho i Etseme
30 Eltoladi, Kesili, Horma,
naho i Eltolade naho i Kesile naho i Kormà
31 Siklagi, Madmana, Sansanna,
naho i Tsiklage naho i Madmanà naho i Sansanà
32 Leboati, Ṣilhimu, Aini àti Rimoni, àpapọ̀ ìlú mọ́kàndínlọ́gbọ̀n àti àwọn ìletò wọn.
naho i Lebaote naho i Silehime naho i Aine vaho i Rimone; rova roapolo-sive’ amby rekets’ o tanà’eo.
33 Ní ìhà ìwọ̀-oòrùn ẹsẹ̀ òkè: Eṣtaoli, Sora, Aṣna,
Aa naho an-tane pisake, i Estaole naho i Tsoreà naho i Asnà,
34 Sanoa, Eni-Gannimu, Tapua, Enamu,
naho i Tsanoà naho i Enganime, i Tapoà naho i Ename,
35 Jarmatu, Adullamu, Soko, Aseka,
Iarmote naho i Adolame, i Sokò naho i Azekà,
36 Ṣaaraimu, Adittaimu àti Gedera (tàbí Gederotaimu). Ìlú mẹ́rìnlá àti àwọn ìletò wọn.
naho i Saraime naho i Aitaime naho i Gederà vaho i Gederotaime: rova folo-efats’ amby rekets’ o tanà’eo.
37 Senani, Hadaṣa, Migdali Gadi,
I Tsenane naho i Kadasà naho i Migdal-gade
38 Dileani, Mispa, Jokteeli,
naho i Dileane naho i Mitspe naho Ioktile,
39 Lakiṣi, Boskati, Egloni,
i Lakise naho i Bots-kate naho i Eglone
40 Kabboni, Lamasi, Kitlisi,
naho i Kabone naho i Lamame naho i Kitlise
41 Gederoti, Beti-Dagoni, Naama àti Makkeda, ìlú mẹ́rìndínlógún àti ìletò wọn.
naho i Gederote, i Bete-dagone, naho i Naamà vaho i Màkedà; rova folo-eneñ’ amby rekets’ o tanà’eo.
I Libnà, naho i Etere naho i Asane
naho Iptà, naho i Asnà naho i Netsibe,
44 Keila, Aksibu àti Meraṣa: ìlú mẹ́sàn-án àti àwọn ìletò wọn.
naho i Keilà naho i Akzeebe vaho i Maresà: rova sive rekets’ o tanà’eo.
45 Ekroni, pẹ̀lú ibùgbé àti àwọn ìletò rẹ̀ tó yí i ká,
I Ekrone, rekets’ o rova’eo naho o tanà’eo.
46 ìwọ̀-oòrùn Ekroni, gbogbo èyí tí ń bẹ nítòsí Aṣdodu, pẹ̀lú àwọn ìletò wọn,
Le boak’ Ekrone pak’ an-driakey mañohoke i Asdode naho o tanà’e iabio.
47 Aṣdodu, agbègbè ìlú rẹ̀ àti ìletò; àti Gasa, ìlú rẹ̀ àti ìletò, títí ó fi dé odò Ejibiti àti agbègbè Òkun Ńlá.
I Asdode rekets’ o rova’eo naho o tanà’eo naho i Aza rekets’ o rova’eo naho o tanà’eo pak’ an-tsaka’ i Mitsraime añe, i riake jabajabay ro efe-tane’e.
48 Ní ilẹ̀ òkè náà: Ṣamiri, Jattiri, Soko,
Le amo vohitseo: i Samire, Iatire naho i Sokò, naho
49 Dannah, Kiriati-Sannnah (tí í ṣe Debiri),
i Danà, naho i Kiriate-sanà (i Debire izay),
50 Anabu, Eṣitemo, Animu,
i Anabe naho i Estemò naho i Enime,
51 Goṣeni, Holoni àti Giloni, ìlú mọ́kànlá àti ìletò wọn.
naho i Gosene naho i Kolone vaho i Gilò; rova folo-raik’ amby rekets’ o tanà’eo.
I Arabe naho i Doma naho i Eseane,
53 Janimu, Beti-Tapua, Afeka,
naho Ianome naho i Bete-tapoà naho i Afekà,
54 Hamuta, Kiriati-Arba (tí í ṣe, Hebroni) àti Ṣiori: ìlú mẹ́sàn-án àti àwọn ìletò rẹ̀
naho i Kamotà naho i Kiriate-arbà (i Kebrone izay) vaho i Tsiore: rova sive naho o tanà’eo;
55 Maoni, Karmeli, Sifi, Jutta,
i Maone, i Karmele naho i Zife naho Iotà
56 Jesreeli, Jokdeamu, Sanoa,
naho Iezreele naho Iokdeame naho i Zanoàke,
57 Kaini, Gibeah àti Timna: ìlú mẹ́wàá àti àwọn ìletò wọn.
i Kaine, i Gibà vaho i Timnà: rova folo rekets’ o tanà’eo.
58 Halhuli, Beti-Suri, Gedori,
I Kalkole, i Bete-tsore naho i Gedore
59 Maarati, Beti-Anoti àti Eltekoni: ìlú mẹ́fà àti àwọn ìletò wọn.
naho i Maarate naho i Betanote vaho i Eltekone: rova eneñe rekets’ o tanà’eo.
60 Kiriati-Baali (tí í ṣe, Kiriati-Jearimu) àti Rabba ìlú méjì àti ìletò wọn.
I Kiriabat-baale, toe Kiriate-Iearime naho i Rabà: rova roe rekets’ o tanà’eo;
61 Ní aginjù: Beti-Araba, Middini, Sekaka,
aa naho am-patrambey añe: i Bete-arabà, i Midine, naho i Sekakà,
62 Nibṣani, Ìlú Iyọ̀ àti En-Gedi: ìlú mẹ́fà àti ìletò wọn.
i Nisbane, naho i rovan-tSiray, vaho i Engedý: rova eneñe rekets’ o tanà’eo.
63 Juda kò lè lé àwọn ọmọ Jebusi jáde, tí wọ́n ń gbé ní Jerusalẹmu. Àwọn ará Jebusi sì ń gbé pẹ̀lú àwọn ènìyàn Juda títí dí òní.
Aa naho o nte-Iebosý mpimoneñe e Ierosalaime ao, tsy naharoake iareo o nte’ Iehodao, fa mbe tambatse e Ierosalaime ao miharo amo ana’ Iehodao pak’ androany o nte-Iebosio.