< Joshua 13 >

1 Nígbà tí Joṣua sì darúgbó tí ọjọ́ orí rẹ̀ sì pọ̀ jọjọ, Olúwa sọ fún un pé, “Ìwọ ti darúgbó púpọ̀, bẹ́ẹ̀ ni ilẹ̀ sì kù lọ́pọ̀lọ́pọ̀ fún yín láti gbà.
A ka koroheketia a Hohua, kua maha ona ra; na ka mea a Ihowa ki a ia, Kua koroheketia koe, kua maha ou ra, a he nui atu te whenua e toe ana, kahore ano i tangohia.
2 “Èyí ni ilẹ̀ tí ó kù: “gbogbo àwọn agbègbè àwọn Filistini, àti ti ara Geṣuri:
Ko te whenua tenei e toe ana: ko nga wahi o nga Pirihitini, ko nga Kehuri katoa;
3 láti odò Ṣihori ní ìlà-oòrùn Ejibiti sí agbègbè Ekroni ìhà àríwá, gbogbo rẹ̀ ni a kà kún Kenaani (agbègbè ìjòyè Filistini márùn-ún ní Gasa, Aṣdodu, Aṣkeloni, Gitti àti Ekroni; ti àwọn ará Affimu);
O Hihoro mai ano, i te ritenga atu o Ihipa a tae noa ki nga rohe o Ekerona whaka te raki, e kiia nei no nga Kanaani; e rima nga wahi ariki o nga Pirihitini; ko nga Kahati, ko nga Aharori, ko nga Ahakeroni, ko nga Kiti, ko nga Ekeroni; me nga Awim i,
4 láti gúúsù; gbogbo ilẹ̀ àwọn ará Kenaani, láti Arah ti àwọn ará Sidoni títí ó fi dé Afeki, agbègbè àwọn ará Amori,
Ki te tonga; ko te whenua katoa o nga Kanaani, me Meara i te taha o nga Hironi tae noa ki Apeke, ki nga rohe o nga Amori:
5 àti ilẹ̀ àwọn ará Gebali; àti gbogbo àwọn Lebanoni dé ìlà-oòrùn, láti Baali-Gadi ní ìsàlẹ̀ òkè Hermoni dé Lebo-Hamati.
Me te whenua o nga Kipiri, me Repanona katoa whaka te rawhiti atu o Paarakara i raro iho o Maunga Heremona tae noa ki te haerenga atu ki Hamata:
6 “Ní ti gbogbo àwọn olùgbé agbègbè òkè, láti Lebanoni sí Misrefoti-Maimu, àní, gbogbo àwọn ará Sidoni, èmi fúnra mi ní yóò lé wọn jáde ní iwájú àwọn ará Israẹli. Kí o ri dájú pé o pín ilẹ̀ yí fún Israẹli ní ilẹ̀ ìní, gẹ́gẹ́ bí mo ṣe fi àṣẹ fún ọ,
Ko nga tangata katoa o te whenua pukepuke, o Repanona tae noa ki Mihirepoto Maimi, me nga Hironi katoa; ka peia ratou e ahau i te aroaro o nga tama a Iharaira: mau ia e wehe a reira hei kainga tupu mo Iharaira, me pera me taku i whakahau ai ki a koe.
7 pín ilẹ̀ yìí ní ilẹ̀ ìní fún àwọn ẹ̀yà mẹ́sàn-án àti ìdajì ẹ̀yà Manase.”
Na reira wehewehea tenei whenua hei kainga tupu mo nga iwi e iwa, ratou ko tetahi taanga o te iwi o Manahi.
8 Àwọn ìdajì ẹ̀yà Manase tí ó kù, àti àwọn Reubeni àti àwọn Gadi ti gba ilẹ̀ ìní, tí Mose ti fún wọn ní ìhà ìlà-oòrùn Jordani bí Mose ìránṣẹ́ Olúwa ti fi fún wọn.
I whiwhi tahi ratou ko nga Reupeni, ko nga Kari ki to ratou wahi, i hoatu ra ki a ratou e Mohi ki tawahi o Horano whaka te rawhiti, ara ko ta Mohi, ko ta te pononga a Ihowa i hoatu ai ki a ratou;
9 Ó sì lọ títí láti Aroeri tí ń bẹ létí àfonífojì Arnoni, àti láti ìlú náà tí ń bẹ ní àárín àfonífojì náà, àti pẹ̀lú gbogbo pẹ̀tẹ́lẹ̀ Medeba títí dé Diboni.
O Aroere atu i te taha o te awaawa o Aranona, me te pa i waenganui o te awaawa, me te mania katoa o Merepa tae noa ki Ripono;
10 Gbogbo ìlú Sihoni ọba àwọn Amori, tí ó ṣe àkóso ní Heṣboni, títí dé ààlà àwọn ará Ammoni.
Me nga pa katoa o Hihona kingi o nga Amori, i kingi ra ki Hehepona, tae noa ki te rohe ki nga tama a Amona;
11 Àti Gileadi, ní agbègbè àwọn ènìyàn Geṣuri àti Maakati, gbogbo òkè Hermoni àti gbogbo Baṣani títí dé Saleka,
Me Kireara, me te rohe ki nga Kehuri, ki nga Maakati, me Maunga Heremona katoa, me Pahana katoa, tae noa ki Hareka;
12 ìyẹn, gbogbo ilẹ̀ ọba Ogu ní Baṣani, tí ó jẹ ọba ní Aṣtarotu àti Edrei, ẹni tí ó kù nínú àwọn Refaimu ìyókù. Mose ti ṣẹ́gun wọn, ó sì ti gba ilẹ̀ wọn.
Te kingitanga katoa o Oka i Pahana; i kingi hoki ia ki Ahataroto, ki Eterei, he toenga ia no nga oranga o nga Repaima; i patua hoki enei e Mohi, a peia atu ana.
13 Ṣùgbọ́n àwọn ará Israẹli kò lé àwọn ará Geṣuri àti Maakati jáde, bẹ́ẹ̀ ni wọ́n ń gbé ní àárín àwọn ará Israẹli títí di òní yìí.
Ko nga Kehuri ia me nga Maakati kihai i peia e nga tama a Iharaira: engari i noho nga Kehuri ratou ko nga Maakati i waenganui o Iharaira a taea noatia tenei ra.
14 Ṣùgbọ́n àwọn ẹ̀yà Lefi ni kò fi ogún kankan fún, níwọ̀n ìgbà tí ó ti jẹ́ pé ọrẹ àfinásun sí Olúwa Ọlọ́run Israẹli ni ogún tiwọn, gẹ́gẹ́ bí o ti ṣèlérí fún wọn.
Ko te iwi anake o Riwai, kihai i hoatu e ia he kainga tupu; ko nga whakahere ahi a Ihowa, a te Atua o Iharaira, te wahi tupu mo ratou, ko tana hoki i korero ai ki a ia.
15 Èyí ni Mose fi fún ẹ̀yà Reubeni ni agbo ilé sí agbo ilé,
A rite tonu ki o ratou hapu ta Mohi i hoatu ai ki te iwi o nga tama a Reupena.
16 láti agbègbè Aroeri ní etí Arnoni Jọ́ọ́jì àti láti ìlú tí ń bẹ láàrín Jọ́ọ́jì, àti gbogbo pẹ̀tẹ́lẹ̀ ní ìkọjá Medeba
A ko te rohe ki a ratou kei Aroere, kei te taha o te awaawa o Aranona, kei te pa hoki i waenganui o te awaawa me te mania katoa i Merepa;
17 sí Heṣboni àti gbogbo ìlú rẹ̀ ní pẹ̀tẹ́lẹ̀, pẹ̀lú Diboni, Bamoti Baali, Beti-Baali-Mioni,
Ko Hehepona me o reira pa katoa i te mania; ko Ripono, me Pamotopaara, me Petepaara Meono,
18 Jahisa, Kedemoti, Mefaati,
Ko Iahata hoki, me Keremoto, me Mepaata,
19 Kiriataimu, Sibma, Sereti Ṣahari lórí òkè ní àfonífojì.
Me Kiriataima, me Hipima, me Terete Hahara i te maunga o taua raorao,
20 Beti-Peori, gẹ̀rẹ́gẹ̀rẹ́ Pisga, àti Beti-Jeṣimoti
Me Petepeoro, me Aharoto Pihika, me Peteiehimoto,
21 gbogbo ìlú tí ó wà ní pẹ̀tẹ́lẹ̀ àti gbogbo agbègbè Sihoni ọba Amori, tí ó ṣe àkóso Heṣboni. Mose sì ti ṣẹ́gun rẹ̀ àti àwọn ọmọ ìjòyè Midiani, Efi, Rekemu, Suri, Huri àti Reba, àwọn ọmọ ọba pawọ́pọ̀ pẹ̀lú Sihoni tí ó gbé ilẹ̀ náà.
Me nga pa katoa o te mania, me te kingitanga katoa o Hihona, o te kingi o nga Amori, i kingi nei ki Hehepona, i patua ngatahitia nei e Mohi me nga ariki o Miriana, me Ewi, ratou ko Rekeme, ko Turu, ko Huru, ko Repa; na Hihona ena ariki, a i noho ki taua whenua.
22 Ní àfikún àwọn tí a pa ní ogun, àwọn ọmọ Israẹli fi idà pa Balaamu ọmọ Beori alásọtẹ́lẹ̀.
I patua ano hoki e nga tama a Iharaira ki te hoari a Paraama tama a Peoro, te tohunga maori, i roto i era atu o to ratou parekura.
23 Ààlà àwọn ọmọ Reubeni ni etí odò Jordani. Àwọn ìlú wọ̀nyí àti abúlé rẹ̀ ni ilẹ̀ ìní àwọn ọmọ Reubeni ní agbo ilé ní agbo ilé.
A ko te rohe ki nga tama a Reupena ko Horano, me tona rohe ano. Ko te wahi tuturu tenei i nga tama a Reupena, i o ratou hapu, nga pa me nga kainga o aua pa.
24 Èyí ni ohun tí Mose ti fi fún ẹ̀yà Gadi, ní agbo ilé ní agbo ilé.
A i hoatu ano e Mohi he wahi ki te iwi o Kara, ki nga tama a Kara, he mea whakarite ki o ratou hapu.
25 Agbègbè ìlú Jaseri, gbogbo ìlú Gileadi àti ìdajì orílẹ̀-èdè àwọn ọmọ ará Ammoni títí dé Aroeri, ní ẹ̀bá Rabba;
A ko te rohe ki a ratou ko Iatere, me nga pa katoa o Kireara, me te hawhe o te whenua o nga tama a Amona, a tae noa ki Aroere ki te ritenga atu o Rapa:
26 àti láti Heṣboni lọ sí Ramati-Mispa àti Betonimu, àti láti Mahanaimu sí agbègbè ìlú Debiri,
I Hehepona hoki a tae noa ki Ramata Mihipe, ki Petonimi; i Mahanaima a tae noa ki te rohe o Repiri:
27 àti ní àfonífojì Beti-Haramu, Beti-Nimra, Sukkoti àti Safoni pẹ̀lú ìyókù agbègbè ilẹ̀ Sihoni ọba Heṣboni (ní ìhà ìlà-oòrùn Jordani, agbègbè rẹ̀ títí dé òpin Òkun Kinnereti).
A i te raorao, ko Petearama, ko Petenimira, ko Hukota, ko Tawhono, a ko te toenga atu o te kingitanga o Hihona, o te kingi o Hehepona, ko Horano me tona rohe tae noa ki te pito o te moana o Kinereta, i tawahi o Horano, whaka te rawhiti.
28 Àwọn ìlú wọ̀nyí àti abúlé rẹ̀ jẹ́ ogún àwọn ọmọ Gadi, ní agbo ilé ní agbo ilé.
Ko te wahi tupu tenei i nga tama a Kara, i o ratou hapu, ko nga pa me nga kainga o aua pa.
29 Èyí ni ohun tí Mose ti fi fún ìdajì ẹ̀yà Manase, èyí ni pé, fún ìdajì ìdílé irú-ọmọ Manase, ní agbo ilé ní agbo ilé.
A i hoatu e Mohi he wahi tuturu ki tetahi taanga o te iwi o Manahi: a ka riro i tetahi taanga o te iwi o nga tama a Manahi, he mea whakarite ki o ratou hapu.
30 Ilẹ̀ náà fẹ̀ dé Mahanaimu àti gbogbo Baṣani, gbogbo agbègbè ilẹ̀ Ogu ọba Baṣani, èyí tí í ṣe ibùgbé Jairi ní Baṣani, ọgọ́ta ìlú,
A no Mahanaima atu te rohe ki a ratou, ko Pahana katoa, me te kingitanga katoa o Oka, o te kingi o Pahana, me nga pa katoa o Haira, era i Pahana ra, e ono tekau nga pa:
31 ìdajì Gileadi, àti Aṣtarotu àti Edrei (àwọn ìlú ọba Ogu ní Baṣani). Èyí ni fún irú àwọn ọmọ Makiri ọmọ Manase fún ààbọ̀ àwọn ọmọ Makiri, ní agbo ilé ní agbo ilé.
Ko tetahi hawhe o Kireara, me Ahataroto, me Eterei, ko nga pa o te kingitanga o Oka i Pahana, i riro era i nga tama a Makiri, a te tama a Manahi, ara i tetahi taanga o nga tama a Makiri, he mea whakarite ki o ratou hapu.
32 Èyí ni ogún tí Mose fi fún wọn nígbà tí ó wà ní pẹ̀tẹ́lẹ̀ Moabu ní ìhà kejì Jordani ní ìlà-oòrùn Jeriko.
Ko enei nga wahi i hoatu ai e Mohi hei kainga tupu i nga mania o Moapa i tawahi o Horano whaka te rawhiti, i te wahi e anga ana ki Heriko.
33 Ṣùgbọ́n fún ẹ̀yà Lefi, Mose kò fi ogún fún un; Olúwa, Ọlọ́run Israẹli, ní ogún wọn, gẹ́gẹ́ bí ó ti ṣe ìlérí fún wọn.
Otiia kihai i hoatu e Mohi he wahi tupu ki te iwi o Riwai: ko Ihowa, ko te Atua o Iharaira, ko ia hei wahi tupu mo ratou; ko tana hoki tena i korero ai.

< Joshua 13 >