< Joshua 1 >

1 Lẹ́yìn ikú u Mose ìránṣẹ́ Olúwa, Olúwa sọ fún Joṣua ọmọ Nuni, olùrànlọ́wọ́ ọ Mose,
Wǝ Pǝrwǝrdigarning ⱪuli bolƣan Musa wapat bolƣandin keyin xundaⱪ boldiki, Pǝrwǝrdigar Musaning hizmǝtkari, Nunning oƣli Yǝxuaƣa sɵz ⱪilip mundaⱪ dedi: —
2 “Mose ìránṣẹ́ mi ti kú. Nísinsin yìí, ìwọ àti gbogbo àwọn ènìyàn wọ̀nyí, ẹ múra láti kọjá odò Jordani lọ sí ilẹ̀ tí Èmi ó fi fún wọn fún àwọn ará Israẹli.
Mening ⱪulum Musa wapat boldi. Əmdi sǝn ⱪozƣilip, bu hǝlⱪning ⱨǝmmisini baxlap Iordan dǝryasidin ɵtüp, Mǝn ularƣa, yǝni Israillarƣa tǝⱪdim ⱪilidiƣan zeminƣa kirgin.
3 Èmi yóò fún un yín ní gbogbo ibi tí ẹ bá fi ẹsẹ̀ ẹ yín tẹ̀, gẹ́gẹ́ bí mo ti ṣe ìlérí fún Mose.
Mǝn Musaƣa eytⱪinimdǝk, putunglarning tapini ⱪǝyǝrgǝ tǝgkǝn bolsa, xu jayni silǝrgǝ bǝrdim;
4 Ilẹ̀ ẹ yín yóò fẹ̀ láti aginjù Lebanoni, àti láti odò ńlá, ti Eufurate—gbogbo orílẹ̀-èdè Hiti títí ó fi dé Òkun Ńlá ní ìwọ̀-oòrùn.
qegranglar qɵl-bayawandin tartip Liwanƣiqǝ, Ⱨittiylarning zeminini ɵz iqigǝ elip, Əfrat dǝryasidin kün petixtiki Ottura Dengizƣiqǝ bolidu.
5 Kì yóò sí ẹnikẹ́ni tí yóò le è dúró níwájú rẹ ní ọjọ́ ayé è rẹ gbogbo. Bí mo ti wà pẹ̀lú u Mose, bẹ́ẹ̀ ni Èmi yóò wà pẹ̀lú rẹ, Èmi kì yóò fi ọ́ sílẹ̀, bẹ́ẹ̀ ni Èmi kì yóò kọ̀ ọ́.
Sening barliⱪ ⱨayat künliringdǝ ⱨeqkim sanga ⱪarxi turalmaydu. Mǝn Ɵzüm Musa bilǝn billǝ bolƣandǝk sening bilǝn billǝ bolup, seni ⱨǝrgiz taxliwǝtmǝymǝn.
6 “Jẹ́ alágbára kí o sì mú àyà le, nítorí ìwọ ni yóò ṣe amọ̀nà àwọn ènìyàn wọ̀nyí, láti lè jogún ilẹ̀ tí mo ti búra fún àwọn baba ńlá a wọn láti fi fún wọn.
Sǝn jür’ǝtlik wǝ ⱪǝysǝr bolƣin; qünki sǝn bu hǝlⱪni Mǝn ata-bowiliriƣa berixkǝ ⱪǝsǝm bilǝn wǝdǝ ⱪilƣan zeminƣa mirashor ⱪilip igilitisǝn.
7 Jẹ́ alágbára, kí o sì mú àyà le gidigidi. Kí o sì ṣọ́ra láti pa gbogbo òfin tí Mose ìránṣẹ́ mi fún ọ mọ́, má ṣe yà kúrò nínú u rẹ̀ sí ọ̀tún tàbí sí òsì, kí ìwọ kí ó lè ṣe rere níbikíbi tí ìwọ bá ń lọ.
Mening ⱪulum Musa sanga buyruƣan barliⱪ ⱪanunƣa ǝmǝl ⱪilixⱪa kɵngül bɵlüp, ⱪǝt’iy jür’ǝtlik wǝ tolimu ⱪǝysǝr bolƣin; sǝn ⱪǝyǝrgila barsang ixliring ƣǝlibilik boluxi üqün uningdin ya ong ya solƣa qǝtnǝp kǝtmǝ;
8 Má ṣe jẹ́ kí ìwé òfin yìí kúrò ní ẹnu rẹ, máa ṣe àṣàrò nínú u rẹ̀ ní ọ̀sán àti ní òru, kí ìwọ kí ó lè ṣọ́ra láti ṣe gbogbo nǹkan tí a kọ sí inú u rẹ̀. Nígbà náà ni yóò dára fún ọ, ìwọ yóò sì ní àṣeyọrí.
bu ⱪanun kitabini ɵz aƣzingdin neri ⱪilmay, uning iqidǝ pütülgǝnning ⱨǝmmisini tutup, uni keqǝ-kündüz zikir kilip oyla; xundaⱪ ⱪilsang yolliringda ƣǝlibilik bolup, ɵzüng ronaⱪ tapisǝn.
9 Èmi kò ha ti pàṣẹ fún ọ bí? Jẹ́ alágbára kí o sì mú àyà le. Má ṣe bẹ̀rù, má sì ṣe rẹ̀wẹ̀sì, nítorí pé Olúwa à rẹ yóò wà pẹ̀lú rẹ ní ibikíbi tí ìwọ bá ń lọ.”
Mana sanga: — Jür’ǝtlik wǝ ⱪǝysǝr bol, dǝp buyruƣanidimƣu? Xunga ⱨeq wǝⱨimigǝ qüxmǝ, yürǝksiz bolma; qünki ⱪǝyǝrgǝ barsang Pǝrwǝrdigar Hudaying sǝn bilǝn birgidur.
10 Báyìí ni Joṣua pàṣẹ fún olórí àwọn ènìyàn rẹ̀,
Xuning bilǝn Yǝxua hǝlⱪning baxliriƣa buyrup: —
11 “Ẹ la ibùdó já, kí ẹ sì sọ fún àwọn ènìyàn, ‘Ẹ pèsè oúnjẹ yín sílẹ̀. Ní ìwòyí ọ̀túnla, ẹ̀yin yóò la Jordani yìí kọjá, láti gba ilẹ̀ tí Olúwa Ọlọ́run yín fi fún un yín láti ní.’”
Silǝr qedirgaⱨtin ɵtüp hǝlⱪⱪǝ: — Ɵzünglar üqün ozuⱪ-tülük tǝyyar ⱪilinglar, qünki üq kün toxⱪanda silǝr Iordan dǝryasidin ɵtüp Pǝrwǝrdigar Hudayinglar silǝrgǝ beridiƣan zeminni igilǝx üqün kirisilǝr, — dǝnglar, dedi.
12 Ṣùgbọ́n Joṣua sọ fún àwọn ará a Reubeni, àwọn ará Gadi àti fún ìdajì ẹ̀yà Manase pé,
Yǝxua Rubǝnlǝr bilǝn Gadlar wǝ Manassǝⱨning yerim ⱪǝbilisigǝ sɵz ⱪilip: —
13 “Rántí àṣẹ tí Mose ìránṣẹ́ Olúwa pa fún yín: ‘Olúwa Ọlọ́run yín á fún yin ní ìsinmi, òun yóò sì fún un yín ní ilẹ̀ yìí.’
Hudaning ⱪuli bolƣan Musaning silǝrgǝ buyrup: — Pǝrwǝrdigar Hudayinglar silǝrgǝ aramliⱪ ata ⱪilip bu zeminni silǝrgǝ bǝrgǝn, dǝp eytⱪinini esinglarda tutunglar.
14 Àwọn ìyàwó yín, àwọn ọmọ yín àti àwọn ẹran ọ̀sìn yín lè dúró ní ilẹ̀ tí Mose fún un yin ní ìlà-oòrùn Jordani; ṣùgbọ́n gbogbo àwọn jagunjagun un yín, pẹ̀lú ìhámọ́ra ogun gbọdọ̀ kọjá síwájú àwọn arákùnrin yín. Ẹ̀yin yóò sì rán àwọn arákùnrin yín lọ́wọ́
Hotun bala-qaⱪanglar wǝ qarpayliringlar Musa ɵzi silǝrgǝ tǝⱪsim ⱪilƣan, Iordan dǝryasining bu tǝripidiki zeminda ⱪalsun, lekin aranglarda ⱪanqilik batur palwan bolsanglar, silǝr ɵz ⱪerindaxliringlarning aldida sǝptǝ turup ularƣa yardǝm berip jǝng ⱪilinglar; taki Pǝrwǝrdigar Hudayinglar ⱪerindaxliringlarƣa silǝrgǝ ata ⱪilƣiniƣa ohxax aram ata ⱪilip, ⱪerindaxliringlarƣa u ularƣa miras ⱪilip beridiƣan zeminni igilǝtgüqǝ xundaⱪ ⱪilinglar. Andin silǝr tǝwǝlikinglar bolƣan zeminni, yǝni Hudaning ⱪuli bolƣan Musa silǝrgǝ tǝⱪsim ⱪilƣan, Iordan dǝryasining kün qiⱪix tǝripidiki bu zeminni igilǝx üqün ⱪaytip beringlar, — dedi.
15 títí Olúwa yóò fi fún wọn ní ìsinmi, gẹ́gẹ́ bí ó ti ṣe fún un yín, àti títí tí àwọn pẹ̀lú yóò fi gba ilẹ̀ náà tí Olúwa Ọlọ́run yín fi fún wọn. Lẹ́yìn náà, ẹ̀yin lè padà sí ilẹ̀ ìní in yín, tí Mose ìránṣẹ́ Olúwa fi fún un yin ní agbègbè ìlà-oòrùn ti Jordani.”
16 Nígbà náà ni wọ́n dá Joṣua lóhùn pé, “Ohunkóhun tí ìwọ pàṣẹ fún wa ni àwa yóò ṣe, ibikíbi tí ìwọ bá rán wa ni àwa yóò lọ.
Ular Yǝxuaƣa jawab berip: — Sǝn bizgǝ ǝmr ⱪilƣanning ⱨǝmmisigǝ ǝmǝl ⱪilimiz, sǝn bizni ⱪǝyǝrgǝ ǝwǝtsǝng, xu yǝrgǝ barimiz.
17 Gẹ́gẹ́ bí àwa ti gbọ́rọ̀ sí Mose nínú ohun gbogbo, bẹ́ẹ̀ ni àwa yóò máa gbọ́ tìrẹ. Kí Olúwa Ọlọ́run rẹ wà pẹ̀lú rẹ, gẹ́gẹ́ bí ó ṣe wà pẹ̀lú u Mose.
Biz ⱨǝmmǝ ixta Musaning sɵzigǝ ⱪulaⱪ salƣinimizdǝk sanga ⱪulaⱪ salimiz; birdinbir tilikimiz, Pǝrwǝrdigar Hudaying Musa bilǝn billǝ bolƣandǝk sening bilǝnmu billǝ bolƣay!
18 Ẹnikẹ́ni tí ó bá tàpá sí ọ̀rọ̀ rẹ, tí kò sì ṣe ìgbọ́ràn sí ọ̀rọ̀ rẹ nínú ohun gbogbo tí ìwọ yóò pàṣẹ fún wọn, pípa ni a ó pa á. Kí ìwọ sá à ṣe gírí, kí ó sì mú àyà le!”
Kimki sening ǝmringgǝ itaǝtsizlik ⱪilip, sǝn bizgǝ buyruƣan ⱨǝrⱪandaⱪ sɵzliringgǝ ⱪulaⱪ salmisa, ɵltürülidu! Sǝn pǝⱪǝtla jür’ǝtlik wǝ ⱪǝysǝr bolƣin, — dedi.

< Joshua 1 >