< Jonah 3 >

1 Ọ̀rọ̀ Olúwa sì tọ Jona wá nígbà kejì wí pé:
Ningĩ ndũmĩrĩri ya Jehova ĩgĩkinyĩra Jona hĩndĩ ya keerĩ, akĩĩrwo atĩrĩ:
2 “Dìde lọ sí Ninefe, ìlú ńlá a nì, kí o sì kéde sí i, ìkéde tí mo sọ fún ọ.”
“Ũkĩra, ũthiĩ itũũra rĩrĩa inene rĩa Nineve, na ũrĩhunjĩrie ũhoro ũrĩa ngũkwĩra.”
3 Jona sì dìde ó lọ sí Ninefe gẹ́gẹ́ bí ọ̀rọ̀ Olúwa. Ninefe jẹ́ ìlú títóbi gidigidi, ó tó ìrìn ọjọ́ mẹ́ta.
Nake Jona agĩathĩkĩra ndũmĩrĩri ya Jehova, agĩthiĩ Nineve. Na rĩrĩ, Nineve rĩarĩ itũũra inene na rĩa bata mũno. Kũrĩthiũrũrũka rĩothe kũngĩaninire mĩthenya ĩtatũ.
4 Jona sì bẹ̀rẹ̀ sí wọ ìlú náà lọ ní ìrìn ọjọ́ kan, ó sì ń kéde, ó sì wí pé, “Níwọ́n ogójì ọjọ́ sí i, a ó bi Ninefe wó.”
Mũthenya wa mbere Jona akĩambĩrĩria gũtoonya itũũra rĩu. Akĩanĩrĩra, akiuga atĩrĩ, “Gwatigia mĩthenya mĩrongo ĩna Nineve kũharaganio.”
5 Àwọn ènìyàn Ninefe sì gba Ọlọ́run gbọ́. Wọ́n sì kéde àwẹ̀, gbogbo wọ́n sì wọ aṣọ ọ̀fọ̀, bẹ̀rẹ̀ láti orí ọmọdé títí dé orí àgbà wọn.
Nao andũ a Nineve magĩĩtĩkia Ngai. Makĩanĩrĩra kũgĩe na ihinda rĩa kwĩhinga kũrĩa irio, nao othe makĩĩhumba nguo cia makũnia, kuuma ũrĩa mũnene mũno o nginya ũrĩa mũnini mũno.
6 Ọ̀rọ̀ náà sì dé ọ̀dọ̀ ọba Ninefe, ó sì dìde kúrò lórí ìtẹ́ rẹ̀, ó sì bọ́ aṣọ ìgúnwà rẹ̀ kúrò lára rẹ̀, ó sì da aṣọ ọ̀fọ̀ bora, ó sì jókòó nínú eérú.
Hĩndĩ ĩrĩa mũthamaki wa kũu Nineve aakinyĩirwo nĩ ũhoro ũcio-rĩ, agĩũkĩra akiuma gĩtĩ-inĩ gĩake kĩa ũnene, akĩruta nguo ciake cia ũthamaki, akĩĩhumba nguo ya ikũnia, na agĩikara thĩ rũkũngũ-inĩ.
7 Nígbà náà ní ó kéde rẹ̀ ni Ninefe pé, “Kí a la Ninefe já nípa àṣẹ ọba, àti àwọn àgbàgbà rẹ̀ pé: “Má ṣe jẹ́ kí ènìyàn, tàbí ẹranko, ọ̀wọ́ ẹran tàbí agbo ẹran, tọ́ ohunkóhun wò, má jẹ́ kí wọn jẹ tàbí mu omi.
Ningĩ akĩanĩrĩrithia ũhoro ũyũ kũu Nineve: “Kuumana na uuge wa mũthamaki na andũ ake arĩa marĩ igweta: “Mũtikareke mũndũ o wothe, kana nyamũ cia rũũru rwa ngʼombe kana rwa mbũri, irũme kĩndũ; itikarekwo irĩe kana inyue.
8 Ṣùgbọ́n jẹ́ kí ènìyàn àti ẹranko da aṣọ ọ̀fọ̀ bo ara, kí wọn sì kígbe kíkan sí Ọlọ́run, sì jẹ́ kí wọn yípadà, olúkúlùkù kúrò ní ọ̀nà ibi rẹ̀ àti kúrò ní ìwà ìpa tí ó wà lọ́wọ́ wọn.
No rĩrĩ, andũ nĩmehumbe nguo cia makũnia o nacio nyamũ nĩihumbwo makũnia. O mũndũ nĩakaĩre Ngai narua. Andũ nĩmatige mĩthiĩre yao mĩũru na ngũĩ ciao.
9 Ta ni ó lè mọ̀ bí Ọlọ́run yóò yípadà kí ó sì ronúpìwàdà, kí ó sì yípadà kúrò ní ìbínú gbígbóná rẹ̀, kí àwa má ṣègbé?”
Nũũ ũngĩmenya kana Ngai aahota kwĩricũkwo, aigue tha atigane na marakara make mahiũ nĩgeetha tũtikaniinwo.”
10 Ọlọ́run sì rí ìṣe wọn pé wọ́n yípadà kúrò ní ọ̀nà ibi wọn, Ọlọ́run sì ronúpìwàdà ibi tí òun ti wí pé òun yóò ṣe sí wọn, òun kò sì ṣe e mọ́.
Hĩndĩ ĩrĩa Ngai onire ũrĩa meekire, na ũrĩa maagarũrũkĩte magatiga mĩthiĩre yao mĩũru-rĩ, akĩmaiguĩra tha akĩaga kũmaniina ta ũrĩa oigĩte nĩekũmaniina.

< Jonah 3 >