< John 5 >

1 Lẹ́yìn nǹkan wọ̀nyí, àjọ àwọn Júù kan kò; Jesu sì gòkè lọ sí Jerusalẹmu.
bwiko nyeu duklume Yafudawa wi, la Yeecu yaken wurcalima. wi wurcalima nyilok bi fwa tatik bele caji wi, wo ki nyi Ibraniyawa ki co ki Baitacda, wi ki bitukko nung cumamgum cumange
2 Adágún omi kan sì wà ní Jerusalẹmu, létí bodè àgùntàn, tí a ń pè ní Betisaida ní èdè Heberu, tí ó ní ẹnu-ọ̀nà márùn-ún.
3 Ní ẹ̀gbẹ́ odò yìí ni ọ̀pọ̀ àwọn abirùn ènìyàn máa ń gbé dùbúlẹ̀ sí, àwọn afọ́jú, arọ àti aláàrùn ẹ̀gbà.
nubo kila-kila buro nuwa lumau, fukma, kilen, bwen co wo nani kange kani bwiyameri da rangum wi.
4
la be tomange kwama wucakeu, ki yam nyo ya bur mwembo kwama ce, la nawo yira kenten mur mwenge bureri fiya twaka bwen non twiraye co kala ticikeri.
5 Ọkùnrin kan wà níbẹ̀, ẹni tí ó tí wà ní àìlera fún ọdún méjìdínlógójì.
nii kange wi ni wo nuwa bo luma coro kwini ta'ar cilombo narub.
6 Bí Jesu ti rí i ní ìdùbúlẹ̀, tí ó sì mọ̀ pé ó pẹ́ tí ó ti wà bẹ́ẹ̀, ó wí fún un pé, “Ìwọ fẹ́ kí a mú ọ láradá bí?”
kambo Yeecu toco ca dom wiyeri, la con nyumom nii wo dam wi coti kila-kila, la con yii co, mo cuiti na yilam kwamara?
7 Abirùn náà dá a lóhùn wí pé, “Arákùnrin, èmi kò ní ẹni tí ìbá gbé mi sínú adágún, nígbà tí a bá ń rú omi náà, bí èmi bá ti ń bọ̀ wá, ẹlòmíràn a sọ̀kalẹ̀ sínú rẹ̀ síwájú mi.”
nii nuwa luma toki nii meramgka “ma man ki nii wuro a dokken yeti mor mwenge na ci mok mwembori. nan bou ri kange yira kenten minen.
8 Jesu wí fún un pé, “Dìde, gbé àkéte rẹ, kí o sì máa rìn.”
Yeecu yii co “kweni, to kwangni mweu mwa yakenti.
9 Lọ́gán, a sì mú ọkùnrin náà láradá, ó sì gbé àkéte rẹ̀, ó sì ń rìn. Ọjọ́ náà sì jẹ́ ọjọ́ ìsinmi.
dangjang nii con twam lan tu kwani ceu cu. la diye co diye kakuk fobka,
10 Nítorí náà àwọn Júù wí fún ọkùnrin náà tí a mú láradá pé, “Ọjọ́ ìsinmi ni òní; kò tọ́ fún ọ láti gbé àkéte rẹ.”
la Yafudawa yii nii wa twameu, kakuk fobkak, yorbo tu kwangni mweu,
11 Ó sì dá wọn lóhùn wí pé, “Ẹni tí ó mú mi láradá, ni ó wí fún mi pé, ‘Gbé àkéte rẹ, kí o sì máa rìn.’”
la con yii ci, nii wo twa yereu, yii ye tu kwama ni mwe mwa yakenti
12 Nígbà náà ni wọ́n bi í lérè wí pé, “Ọkùnrin wo ni ẹni tí ó wí fún ọ pé gbé àkéte rẹ, kí o sì máa rìn?”
cin me co, we nii co yi nen ki tu kwangni mweu mwa yakengtiye?
13 Ẹni tí a mú láradá náà kò sì mọ̀ ẹni tí ó jẹ́ nítorí Jesu ti kúrò níbẹ̀, àwọn ènìyàn púpọ̀ wà níbẹ̀.
la nii wo ci twa beu nyombo we Yeecu, la Yeecu cerum da'ar, wori nubo kila kabo fiye co.
14 Lẹ́yìn náà, Jesu rí i nínú tẹmpili ó sì wí fún un pé, “Wò ó, a mú ọ láradá: má ṣe dẹ́ṣẹ̀ mọ́, kí ohun tí ó burú ju èyí lọ má ba à bá ọ!”
la kaktenri Yeecu ya fiya co kuwabe, la yii co to mon yilam kwamer, mare bwirangke tak na kange dike bwiraneu fiya nen de.
15 Ọkùnrin náà lọ, ó sì sọ fún àwọn Júù pé, Jesu ni ẹni tí ó mú òun láradá.
nii co cu yan yii Yafudawau, Yeecu twa yere.
16 Nítorí èyí ni àwọn Júù ṣe inúnibíni sí Jesu, wọ́n sì ń wá ọ̀nà láti pa á, nítorí tí o ń ṣe nǹkan wọ̀nyí ní ọjọ́ ìsinmi.
lan co dike wo Yafudawa ne Yeecu dotange, won co ma nan dii keburo kakuk fobkak.
17 Ṣùgbọ́n Jesu dá wọn lóhùn pé, “Baba mi ń ṣiṣẹ́ títí di ìsinsin yìí, èmi náà sì ń ṣiṣẹ́.”
Yeecu yii ci teemi ma nangen ti bwen na wori, mo keneu ma manangenti.
18 Nítorí èyí ni àwọn Júù túbọ̀ ń wá ọ̀nà láti pa á, kì í ṣe nítorí pé ó ba ọjọ́ ìsinmi jẹ́ nìkan ni, ṣùgbọ́n ó wí pẹ̀lú pé, Baba òun ni Ọlọ́run jẹ́, ó ń mú ara rẹ̀ bá Ọlọ́run dọ́gba.
co dor Yafudawa do na twalum co ciki kebo ka kanuk fobka ca kimeu, yila con co ten kwama ki te ce, tu dor ceroti dong-dong na kwama
19 Nígbà náà ni Jesu dáhùn, ó sì wí fún wọn pé, “Lóòótọ́, lóòótọ́ ni mo wí fún yín, ọmọ kò lè ṣe ohunkóhun fún ara rẹ̀, bí kò ṣe ohun tí ó bá rí pé Baba ń ṣe, nítorí ohunkóhun tí baba bá ń ṣe, ìwọ̀nyí ni ọmọ náà sì ń ṣe pẹ̀lú.
Yeecu kar cinen, bicom ki bicom bwe mani a ma diker na dor ceroce kima kima kan co dike ca to tee ma tiyeu, wori dii ke na tee matiyeri, bwe kima co co ciko win.
20 Nítorí Baba fẹ́ràn ọmọ, ó sì ti fi ohun gbogbo tí ó ń ṣe hàn án, òun yóò sì fi iṣẹ́ tí ó tóbi jù wọ̀nyí lọ hàn án, kí ẹnu lè yà yín.
wori tee cui bweti, lan nun dikero gwam wo ca matiyeu, la an nung cinen dike burombo tenang tenangeu wo la buro la na ko nyumangi.
21 Nítorí pé, gẹ́gẹ́ bí Baba ti ń jí òkú dìde, tí ó sì ń sọ wọ́n di alààyè: bẹ́ẹ̀ ni ọmọ ń sọ àwọn tí ó fẹ́ di alààyè pẹ̀lú.
kambo teeu kungum nubo bweyarangume yila ne ci dumeu, nyo ken bweu ne dumeti nii wo ca cuiyeu.
22 Nítorí pé Baba kì í ṣe ìdájọ́ ẹnikẹ́ni, ṣùgbọ́n ó ti fi gbogbo ìdájọ́ lé ọmọ lọ́wọ́,
la tee ma bo nii nin buolang, la con neken buolangko kang bwek
23 kí gbogbo ènìyàn lè máa fi ọlá fún ọmọ gẹ́gẹ́ bí wọ́n ti ń fi ọlá fún Baba. Ẹnikẹ́ni tí kò bá fi ọlá fún ọmọ, kò fi ọlá fún Baba tí ó ran an.
la na nubo gwam na ne bwe dur, kanbo ci nem tee tiyeu. nii wo na nebo bwedurre di nebo teeu wo tuomceu.
24 “Lóòótọ́, lóòótọ́ ni mo wí fún yín, ẹnikẹ́ni tí ó bá gbọ́ ọ̀rọ̀ mi, tí ó bá sì gba ẹni tí ó rán mi gbọ́, ó ní ìyè tí kò nípẹ̀kun, òun kì yóò sì wá sí ìdájọ́; ṣùgbọ́n ó ti ré ikú kọjá bọ́ sí ìyè. (aiōnios g166)
bicom, bicom nii nuwa ker mire la ne bilenker nii wo tuom yereri wi ki dume diiri yeu, la mani a kangco ti la con cum buar con yabken dume. (aiōnios g166)
25 Lóòótọ́, lóòótọ́ ni mo wí fún yín, wákàtí náà ń bọ̀, ó sì dé tán nísinsin yìí, nígbà tí àwọn òkú yóò gbọ́ ohùn Ọmọ Ọlọ́run, àwọn tí ó bá gbọ́ yóò sì yè.
bicom, bicom ma yi kom kwama co wi bouti, wuro nubo bwiyameu a nuwa dir bi bwe kwamaro tiyeu, la nubo buro nuwa an da.
26 Nítorí pé gẹ́gẹ́ bí Baba ti ní ìyè nínú ara rẹ̀; gẹ́gẹ́ bẹ́ẹ̀ ni ó sì fi fún ọmọ láti ní ìyè nínú ara rẹ̀;
na wo tee wi ki dume coki bwici, la con ne bweu na yilam ki dume ki bwici.
27 Ó sì fún un ní àṣẹ láti máa ṣe ìdájọ́ pẹ̀lú, nítorí tí òun jẹ́ Ọmọ Ènìyàn.
la teeu ne ken bweu bikwan kerero na mwatum bolanko wori co bibwe nii fire.
28 “Kí èyí má ṣe yà yín lẹ́nu; nítorí pé wákàtí ń bọ̀, nínú èyí tí gbogbo àwọn tí ó wà ní ibojì yóò gbọ́ ohun rẹ̀.
ko nyuman de ki wo, kwama kange bouti wo nubo wo tuweti numeu an nuwa dircero.
29 Wọn ó sì jáde wá; àwọn tí ó ṣe rere, sí àjíǹde ìyè; àwọn tí ó sì ṣe búburú sí àjíǹde ìdájọ́.
la ci an cerangu, buro mana kenneu ki yan kwenka dumek, la buro mana bwireu kiyan kwenka buolangek.
30 Èmi kò le ṣe ohun kan fún ara mi, bí mo ti ń gbọ́ ni, mo ń dájọ́, òdodo sì ni ìdájọ́ mi; nítorí èmi kò wá ìfẹ́ ti èmi fúnra mi, bí kò ṣe ìfẹ́ ti ẹni tí ó rán mi.
mani ma makange diker ti ki bwimi, nawoma nuwau, ma mabuolangko nyo, buolanmiko dong-dong, wori dike ma matiyeu kebo mo, na nii wo tuoma yerece.
31 “Bí èmi bá ń jẹ́rìí ara mi, ẹ̀rí mi kì í ṣe òtítọ́.
na man warker dor mir di, warke miumani a yila bilenkeretti.
32 Ẹlòmíràn ni ẹni tí ń jẹ́rìí mi; èmi sì mọ̀ pé, òtítọ́ ni ẹ̀rí mi tí ó jẹ́.
kange wi wo awarker ti dor mire. la man nyimom warkeu ca ne ti dor mireu bilenker.
33 “Ẹ̀yin ti ránṣẹ́ lọ sọ́dọ̀ Johanu, òun sì ti jẹ́rìí sí òtítọ́.
kan tuom yuwa na nin, con ne warker bilenkerer.
34 Ṣùgbọ́n èmi kò gba ẹ̀rí lọ́dọ̀ ènìyàn, nǹkan wọ̀nyí ni èmi ń sọ, kí ẹ̀yin lè là.
la warke wo ma yoweu kebo nii fir nin, ma tok kere wo na fiya cerka.
35 Òun ni fìtílà tí ó ń jó, tí ó sì ń tànmọ́lẹ̀, ẹ̀yin sì fẹ́ fún sá à kan láti máa yọ̀ nínú ìmọ́lẹ̀ rẹ̀.
yuwana kira wo titi re filang tiyeu, la kom cuiti na ko ma bilangtum mor filange ce nin biduwar.
36 “Ṣùgbọ́n èmi ní ẹ̀rí tí ó pọ̀jù ti Johanu lọ. Nítorí iṣẹ́ tí Baba ti fi fún mi láti ṣe parí, iṣẹ́ náà pàápàá tí èmi ń ṣe náà ń jẹ́rìí mi pé, Baba ni ó rán mi.
dual, warke ma cike tenangi la yuwana ceu, ki nangendo wo tee ne ye nan dimeu, nangen do buro matiyeu, warker ti dor mir, nung teeu tuom ye
37 Àti Baba tìkára rẹ̀ tí ó rán mi ti jẹ́rìí mi. Ẹ̀yin kò gbọ́ ohùn rẹ̀ nígbà kan rí, bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò rí ìrísí rẹ̀.
tee wo tuom yereu ki bwici warker dor mir. ka nuwambo dir cer wi ko tom bo cerkanka ceu wi.
38 Ẹ kò sì ní ọ̀rọ̀ rẹ̀ láti máa gbé inú yín, nítorí ẹni tí ó rán, òun ni ẹ̀yin kò gbàgbọ́.
kercero mani yim mor nee kume, wori ka nebo bilenker ki nii wo ca tuomu weu.
39 Ẹ̀yin ń wá ìwé mímọ́ nítorí ẹ̀yin rò pé nínú wọn ni ẹ̀yin ní ìyè tí kò nípẹ̀kun. Wọ̀nyí sì ni àwọn tí ó ń jẹ́rìí mi. (aiōnios g166)
kom kiyerang bifumeroti kom kwatiri more ciye kan fiya dume dii ri yeu, wentati cici warkerti dor miro. (aiōnios g166)
40 Ẹ̀yin kò sì fẹ́ láti wá sọ́dọ̀ mi, kí ẹ̀yin ba à lè ní ìyè.
la kom cui bo ko bou minen nako fiya dume.
41 “Èmi kò gba ògo lọ́dọ̀ ènìyàn.
mani ma yo cak-lanka fiye nubo wiye.
42 Ṣùgbọ́n èmi mọ̀ pé, ẹ̀yin fúnra yín kò ní ìfẹ́ Ọlọ́run nínú yín.
la man nyumom ka man ki cuika kwamak neer kumer.
43 Èmi wá ní orúkọ Baba mi, ẹ̀yin kò sì gbà mí; bí ẹlòmíràn bá wá ní orúkọ ara rẹ̀, òun ni ẹ̀yin yóò gbà.
ma bou mor dene teemi la ka yoyebou, no na kange an bou ki den cer di kan yo co.
44 Ẹ̀yin ó ti ṣe lè gbàgbọ́, ẹ̀yin tí ń gba ògo lọ́dọ̀ ara yín tí kò wá ògo tí ó ti ọ̀dọ̀ Ọlọ́run nìkan wá?
la ka nebilenker nyi kom wo ciya caklangka bwi ti kumeu, lamanikado caklankako wo bou kwama nin win ki kwaceu
45 “Ẹ má ṣe rò pé, èmi ó fi yín sùn lọ́dọ̀ Baba, ẹni tí ń fi yín sùn wà, àní Mose, ẹni tí ẹ̀yin gbẹ́kẹ̀lé.
kom kware neer fiye teemi wiyeu niiwo muca woka yoneer cineneu.
46 Nítorí pé ẹ̀yin ìbá gba Mose gbọ́, ẹ̀yin ìbá gbà mí gbọ́, nítorí ó kọ ìwé nípa tèmi.
na kom ciyaki mucari, kan ciya kimo, wori con mulangi dor mir.
47 Ṣùgbọ́n bí ẹ̀yin kò bá gba ìwé rẹ̀ gbọ́, ẹ̀yin ó ti ṣe gbà ọ̀rọ̀ mi gbọ́?”
na kom ciya bo ki mulangka cerkori, la kom mani na ko ciya ki kermiro.

< John 5 >