< John 19 >
1 Nítorí náà ni Pilatu mú Jesu, ó sì nà án.
Amalalu, Bailade da Yesu lale, amola ea sia: beba: le dadi gagui dunu da Yesu fegasuga fananu.
2 Àwọn ọmọ-ogun sì hun adé ẹ̀gún, wọ́n sì fi dé e ní orí, wọ́n sì fi aṣọ ìgúnwà elése àlùkò wọ̀ ọ́.
Dadi gagui dunu ilia da aya: gaga: nomei nodomene, habuga hamone, Yesu Ea dialuma da: iya figisi. Ilia da yoi abula ida: iwane gala Ema idiniginisi.
3 Wọ́n sì wí pé, “Kábíyèsí, ọba àwọn Júù!” Wọ́n sì fi ọwọ́ wọn gbá a ní ojú.
Yesu leloba amogawi misini, ilia amane sia: i, “Yu Hina Bagade! Mae bogole, esaloma!” Amalalu, ilia da Ea odagi loboga fai.
4 Pilatu sì tún jáde, ó sì wí fún wọn pé, “Wò ó, mo mú u jáde tọ̀ yín wá, kí ẹ̀yin kí ó lè mọ̀ pé, èmi kò rí ẹ̀ṣẹ̀ kan lọ́wọ́ rẹ̀.”
Bailade da bu gadili asili, dunu huluane ilima amane sia: i, “Dilia! Amo dunu dili huluane ba: ma: ne, na da guiguda: oule misunu. E bogoma: ne wadela: i hou hamoi amo na da hamedafa ba: i, amo dilia ba: mu.”
5 Nítorí náà Jesu jáde wá, ti òun ti adé ẹ̀gún àti aṣọ elése àlùkò. Pilatu sì wí fún wọn pé, “Ẹ wò ọkùnrin náà!”
Amasea, Yesu da aya: gaga: nomei habuga Ea dialuma da: iya ligisi, yoi abula idiniginisi, gadili misi. Bailade da ilima amane sia: i, “Ba: ma: ! Dunu da amo!”
6 Nítorí náà nígbà tí àwọn olórí àlùfáà, àti àwọn oníṣẹ́ rí i, wọ́n kígbe wí pé, “Kàn án mọ́ àgbélébùú, kàn án mọ́ àgbélébùú.” Pilatu wí fún wọn pé, “Ẹ mú un fún ara yín, kí ẹ sì kàn án mọ́ àgbélébùú: nítorí èmi kò rí ẹ̀ṣẹ̀ lọ́wọ́ rẹ̀.”
Be gobele salasu ouligisu dunu amola Debolo Diasu sosodo aligisu dunu, ilia da Yesu ba: beba: le, amane halale sia: i, “Bulufalegeiga fuga: ma! Bulufalegeiga fuga: ma!” Bailade da ilima amane sia: i, “Defea! Dilisu lale, bulufalegeiga fuga: ma! E medomu bai na da hamedafa ba: sa.”
7 Àwọn Júù dá a lóhùn wí pé, “Àwa ní òfin kan, àti gẹ́gẹ́ bí òfin, wa ó yẹ fún un láti kú, nítorí ó gbà pé Ọmọ Ọlọ́run ni òun ń ṣe.”
Dunu huluane bu adole i, “E da Gode Egefe amo Ea sia: beba: le, ninia sema dedei defele E da bogomu da defea.”
8 Nítorí náà nígbà tí Pilatu gbọ́ ọ̀rọ̀ yìí, ẹ̀rù túbọ̀ bà á.
Amo sia: nababeba: le, Bailade da bu baligiliwane beda: i.
9 Ó sì tún wọ inú gbọ̀ngàn ìdájọ́ lọ, ó sì wí fún Jesu pé, “Níbo ni ìwọ ti wá?” Ṣùgbọ́n Jesu kò dá a lóhùn.
E da bu ea diasu ganodini golili sa: ili, Yesuma adole ba: i, “Di da habidili misila: ?” Be Yesu da bu hame adole i.
10 Nítorí náà, Pilatu wí fún un pé, “Èmi ni ìwọ kò fọhùn sí? Ìwọ kò mọ̀ pé, èmi ní agbára láti dá ọ sílẹ̀, èmi sì ní agbára láti kàn ọ́ mọ́ àgbélébùú?”
Bailade da Ema amane sia: i, “Abuli nama hame sia: sa? Dia se iasu diasu logo doasima: ne o di bulufalegeiga fuga: ma: ne amo hamoma: ne na da gasa gala. Amo Di da hame dawa: bela: ?”
11 Jesu dá a lóhùn pé, “Ìwọ kì bá tí ní agbára kan lórí mi, bí kò ṣe pé a fi í fún ọ láti òkè wá, nítorí náà ẹni tí ó fi mí lé ọ lọ́wọ́ ni ó ní ẹ̀ṣẹ̀ pọ̀jù.”
Yesu E bu adole i, “Gode da amo ouligisu hou dima iabeba: le fawane, di da amo gasa gagusa. Amaiba: le, eno dunu amo da Na medomusa: dawa i, amo ea wadela: i hou da dia wadela: i hou baligi dagoi.”
12 Nítorí èyí, Pilatu ń wá ọ̀nà láti dá a sílẹ̀, ṣùgbọ́n àwọn Júù kígbe, wí pé, “Bí ìwọ bá dá ọkùnrin yìí sílẹ̀, ìwọ kì í ṣe ọ̀rẹ́ Kesari: ẹnikẹ́ni tí ó bá ṣe ara rẹ̀ ní ọba, ó sọ̀rọ̀-òdì sí Kesari.”
Amo sia: nababeba: le, Bailade da Yesu Ea se iasu diasu logo doasima: ne, logo hogoi helei. Be dunu huluane bu bagadewane halale sia: i, “E masa: ne di da sia: sea, di da Sisa ea na: iyado hame ganumu. Nowa da e da Hina Bagade sia: sa, e da Sisa ema ha lai.”
13 Nítorí náà nígbà tí Pilatu gbọ́ ọ̀rọ̀ wọ̀nyí, ó mú Jesu jáde wá, ó sì jókòó lórí ìtẹ́ ìdájọ́ ní ibi tí a ń pè ní Òkúta-títẹ́, ṣùgbọ́n ní èdè Heberu, Gabata.
Amo sia: nababeba: le, Bailade da Yesu gadili oule asili, ea fofada: su fisuga fi. Amo sogebi dio amo “Igi Fa: i.” (Hibulu sia: da Ga: bada.)
14 Ó jẹ́ ìpalẹ̀mọ́ àjọ ìrékọjá, ó sì jẹ́ ìwọ̀n wákàtí ẹ̀kẹfà: Ó sì wí fún àwọn Júù pé, “Ẹ wo ọba yín!”
Amoha da esomogoa, Baligisu Lolo Nasu esoga. Bailade da dunu huluane ilima amane sia: i, “Dilia Hina Bagade da goea.”
15 Nítorí náà wọ́n kígbe wí pé, “Mú un kúrò, mú un kúrò. Kàn án mọ́ àgbélébùú.” Pilatu wí fún wọn pé, “Èmi yóò ha kan ọba yín mọ́ àgbélébùú bí?” Àwọn olórí àlùfáà dáhùn wí pé, “Àwa kò ní ọba bí kò ṣe Kesari.”
Ilia bu halale sia: i, “E medoma! E medoma! Bulufalegeiga fuga: ma!” Bailade da ilima adole ba: i, “Na da dilia Hina Bagade bulufalegeiga fuga: mu da defeala: ?” Gobele salasu ouligisu dunu ilia da bu adole i, “Ninia hina bagade da afae fawane - Sisa!”
16 Nítorí náà ni Pilatu fà á lé wọn lọ́wọ́ láti kàn án mọ́ àgbélébùú. Àwọn ológun gba Jesu lọ́wọ́ Pilatu.
Amalalu, Bailade da Yesu bulufalegeiga fuga: musa: , ilima i dagoi.
17 Nítorí náà, wọ́n mú Jesu, ó sì jáde lọ, ó ru àgbélébùú fúnra rẹ̀ sí ibi tí à ń pè ní ibi agbárí, ní èdè Heberu tí à ń pè ní Gọlgọta.
Amaiba: le, ilia da Yesu lale oule asi. E da bulufalegei gisawane asili sogebi ea dio amo “Dialuma Gasa Sogebi,” amoga doaga: i. (Hibulu sia: amo sogebi ea dio da Gologoudia).
18 Níbi tí wọ́n gbé kàn án mọ́ àgbélébùú, àti àwọn méjì mìíràn pẹ̀lú rẹ̀, níhà ìhín àti níhà kejì, Jesu sì wà láàrín.
Amoga ilia da Yesu bulufalegeiga fuga: i. Dunu aduna eno, afae da ea lobodafadili, eno da ea lobo fofadidili, ili bulufalegeiga fuga: i.
19 Pilatu sì kọ ìwé kan pẹ̀lú, ó sì fi lé e lórí àgbélébùú náà. Ohun tí a sì kọ ni, Jesu ti Nasareti Ọba àwọn Júù.
Bailade da meloa dedene, ea dadi gagui dunu ilia da bulufalegeiga gosagisi. E amane dedei “Yesu Na: salede dunu. Yu dunu ilia Hina Bagade!”
20 Nítorí náà, ọ̀pọ̀ àwọn Júù ni ó ka ìwé àkọlé yìí, nítorí ibi tí a gbé kan Jesu mọ́ àgbélébùú súnmọ́ etí ìlú, a sì kọ ọ́ ní èdè Heberu àti Latin, àti ti Giriki.
Yesu Ea bulufalegei sogebi da Yelusaleme gadeneiba: le, dunu bagohame da amo dedei idi. Dedei da Hibulu sia: , Louma sia: amola Galigi sia: , amoga dedene legei.
21 Nítorí náà àwọn olórí àlùfáà àwọn Júù wí fún Pilatu pé, “Má ṣe kọ, ‘Ọba àwọn Júù,’ ṣùgbọ́n pé ọkùnrin yìí wí pé, èmi ni ọba àwọn Júù.”
Gobele salasu ouligisu dunu ilia Bailadema amane sia: i, “Yu dunu ilia Hina Bagade mae dedema! Be ‘Amo dunu da ‘Na da Yu dunu ilia Hina Bagade E sia: i,’ amo fawane dedema!”
22 Pilatu dáhùn pé, ohun tí mo ti kọ, mo ti kọ ọ́.
Be Bailade da bu adole i, “Amo na dedei, na da dedei dagoi!”
23 Nígbà náà ni àwọn ọmọ-ogun, nígbà tí wọ́n kan Jesu mọ́ àgbélébùú tán, wọ́n mú aṣọ rẹ̀, wọ́n sì pín wọn sí ipa mẹ́rin, apá kan fún ọmọ-ogun kọ̀ọ̀kan, àti ẹ̀wù àwọ̀tẹ́lẹ̀ rẹ̀, ṣùgbọ́n ẹ̀wù àwọ̀tẹ́lẹ̀ náà kò ní ojúràn-án, wọ́n hun ún láti òkè títí jálẹ̀.
Ilia da Yesu bulufalegeiga dabagala: i dagoiba: le, dadi gagui dunu da Ea abula liligi huluane lale, biyaduyale agoane momogili, lai dagoi. Ea abuladafa, amo da disimusa: hame nodomei, afae fawane amuli.
24 Nítorí náà wọ́n wí fún ara wọn pé, “Ẹ má jẹ́ kí a fà á ya, ṣùgbọ́n kí a ṣẹ́ gègé nítorí rẹ̀.” Ti ẹni tí yóò jẹ́: kí ìwé mímọ́ kí ó le ṣẹ, tí ó wí pé, “Wọ́n pín aṣọ mi láàrín ara wọn, wọ́n sì ṣẹ́ gègé fún aṣọ ìlekè mi.” Nǹkan wọ̀nyí ni àwọn ọmọ-ogun ṣe.
Dadi gagui dunu ilia gilisili sia: dasu, “Amo gadelale sagomu da defea hame. Dunu afae da amo lama: ne, ninia amoga ululuale hedemu.” Gode Sia: da amane dedei dialu, “Na idiniginisi liligi huluane ilia afafale sagoi. Na abula lama: ne ilia da amoga ululuale hedei,” amo sia: da dafawane doaga: i dagoi ba: i.
25 Ìyá Jesu àti arábìnrin ìyá rẹ̀ Maria aya Kilopa, àti Maria Magdalene sì dúró níbi àgbélébùú,
Yesu Ea ame, Ea ame eya Meli (Galiouba: se idua) amola Meli Ma: gadala, ilia da Yesu Ea bulufalegei bai amo gadenene lelu.
26 nígbà tí Jesu rí ìyá rẹ̀ àti ọmọ-ẹ̀yìn náà dúró, ẹni tí Jesu fẹ́ràn, ó wí fún ìyá rẹ̀ pé, “Obìnrin, wo ọmọ rẹ!”
Yesu da Ea ame amola Ea dogolegei na: iyado ado ba: su dunu, ela lelebe ba: loba, Ea amema amane sia: i, “Ame! Diagofe goea!”
27 Lẹ́yìn náà ni ó sì wí fún ọmọ-ẹ̀yìn náà pé, “Wo ìyá rẹ!” Láti wákàtí náà lọ ni ọmọ-ẹ̀yìn náà sì ti mú un lọ sí ilé ara rẹ̀.
Amalalu, Ea ado ba: su dunuma E amane sia: i, “Dia ame goea!” Amalalu, amoganini amo ado ba: su dunu da Yesu Ea ame, amo ea diasuga ouligisu.
28 Lẹ́yìn èyí, bí Jesu ti mọ̀ pé, a ti parí ohun gbogbo tán, kí ìwé mímọ́ bà á lè ṣẹ, ó wí pé, “Òrùngbẹ ń gbẹ mí.”
Ea hawa hamosu huluane da dagoi, amo Yesu E dawa: i galu. Gode Sia: Dedei dafawaneyale hamoma: ne, E amane sia: i, “Na hano hanai galebe!”
29 Ohun èlò kan tí ó kún fún ọtí kíkan wà níbẹ̀, wọ́n tẹ kànìnkànìn tí ó kún fún ọtí kíkan bọ inú rẹ̀, wọ́n sì fi lé orí igi hísópù, wọ́n sì nà án sí i lẹ́nu.
Ofodo amogawi dialu. Amo da waini hano amoga nabai galu. Amalalu, ilia da waini nasu amo ganodini abula gele, “hisobe” daguluga gosagili, Yesu moma: ne, Ea lafiga olelei.
30 Nígbà tí Jesu sì ti gba ọtí kíkan náà, ó wí pé, “Ó parí!” Ó sì tẹ orí rẹ̀ ba, ó jọ̀wọ́ ẹ̀mí rẹ̀.
Waini hano nanu, Yesu amane sia: i, “Defea! Amo da dagoi!” Amalalu, E da Ea dialuma fili sa: ili, bogoi dagoi.
31 Nítorí ó jẹ́ ọjọ́ ìpalẹ̀mọ́, kí òkú wọn má ba à wà lórí àgbélébùú ní ọjọ́ ìsinmi (nítorí ọjọ́ ńlá ni ọjọ́ ìsinmi náà), nítorí náà, àwọn Júù bẹ Pilatu pé kí a ṣẹ́ egungun itan wọn, kí a sì gbé wọn kúrò.
Amo eso da Falaida: i eso, aya da Sa: bade eso (Baligisu Lolo Nasu Sa: bade eso) galu. Amaiba: le bogoi da: i hodo da bulufalegeiga udigili dialumu, Yu ouligisu dunu ilia da higa: i galu. Sema ilia da sia: su. Amaiba: le, bulufalegeiga fuga: i dunu ilia emo gasa fili, bulufalegei amoga fadegale fasima: ne, amo ilia da Bailadema amane sia: i.
32 Nítorí náà, àwọn ọmọ-ogun wá, wọ́n sì ṣẹ́ egungun itan ti èkínní, àti ti èkejì, tí a kàn mọ́ àgbélébùú pẹ̀lú rẹ̀.
Amalalu, dadi gagui dunu da asili, musa: dunu ea emo gasa fili, asili eno dunu, ea emo gasa fi. Amo dunu ela da Yesu, gilisili bulufalegeiga fuga: i dagoi ba: i.
33 Ṣùgbọ́n nígbà tí wọ́n dé ọ̀dọ̀ Jesu, tí wọ́n sì rí i pé ó ti kú, wọn kò ṣẹ́ egungun itan rẹ̀,
Be Yesuma doaga: le, E da bogoi dagoi ba: loba, ilia da Ea emo gasa hame fi.
34 ṣùgbọ́n ọ̀kan nínú àwọn ọmọ-ogun náà fi ọ̀kọ̀ gún un lẹ́gbẹ̀ẹ́, lójúkan náà, ẹ̀jẹ̀ àti omi sì tú jáde.
Be dadi gagui dunu afae da Yesu ea afo goge agei amoga sone, maga: me amola hano ahoanebe ba: i.
35 Ẹni tí ó rí sì jẹ́rìí, òtítọ́ sì ni ẹ̀rí rẹ̀, ó sì mọ̀ pé òtítọ́ ni òun sọ, kí ẹ̀yin ba à lè gbàgbọ́.
(Na, amo hou ba: su dunu, dilia huluane dafawaneyale dawa: ma: ne, amo hou olelesa. Na olelei da dafawane na dawa: )
36 Nǹkan wọ̀nyí ṣe, kí ìwé mímọ́ ba à lè ṣẹ, tí ó wí pé, “A kì yóò fọ́ egungun rẹ̀.”
Amo hou da Gode Sia: Dedei dafawaneyale dawa: ma: ne misi. Sia: dedei diala, amane, “Ilia da Ea gasa hamedafa fimu!”
37 Ìwé mímọ́ mìíràn pẹ̀lú sì wí pé, “Wọn ó máa wo ẹni tí a gún lọ́kọ̀.”
Gode Ea Sia: eno dedei diala, “Dunu amo da E soi dagoi, ilia E ba: lalumu.”
38 Lẹ́yìn nǹkan wọ̀nyí ní Josẹfu ará Arimatea, ẹni tí ó jẹ́ ọmọ-ẹ̀yìn Jesu, ní ìkọ̀kọ̀, nítorí ìbẹ̀rù àwọn Júù, o bẹ Pilatu kí òun lè gbé òkú Jesu kúrò, Pilatu sì fún un ní àṣẹ. Nígbà náà ni ó wá, ó sì gbé òkú Jesu lọ.
Amalalu, Yousefe, A:limadia dunu, e da Yesu Ea da: i hodo lamusa: , Bailadema adole ba: i. (Yousefe da Yesu ea fa: no bobogesu dunu esalu. Be e da Yu ouligisu dunu ilima beda: iba: le, wamowane fa: no bobogelalu.) Bailade da Yousefe e da Yesu Ea da: i hodo lamu da defea sia: i. Amaiba: le, Yousefe da Yesu Ea da: i hodo lale, gaguli asi.
39 Nikodemu pẹ̀lú sì wá, ẹni tí ó tọ Jesu wá lóru lákọ̀ọ́kọ́, ó sì mú àdàpọ̀ òjìá àti aloe wá, ó tó ìwọ̀n ọgọ́rùn-ún lita.
Nigoudimase (e da musa: gasia Yesuma masu dunu), e da30 gilougala: me agoane gabusiga: manoma legesu liligi aguni, Yousefe sigi asi.
40 Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n gbé òkú Jesu, wọ́n sì fi aṣọ ọ̀gbọ̀ dì í pẹ̀lú tùràrí, gẹ́gẹ́ bí ìṣe àwọn Júù ti rí ní ìsìnkú wọn.
Amo dunu aduna, Yesu Ea da: i hodo lale, abulaga sosone, Yu dunu ilia bogoi ouligisu hou defele, gabusiga: manoma legei.
41 Àgbàlá kan sì wà níbi tí a gbé kàn án mọ́ àgbélébùú; ibojì tuntun kan sì wà nínú àgbàlá náà, nínú èyí tí a kò tí ì tẹ́ ẹnìkan sí rí.
Yesu Ea bogoi sogebi amogai da ifabi galu. Amo ganodini gaheabolo bogoi gele gelabo dogoi dialu (amo ganodini bogoi hodo da hamedafa sali).
42 Ǹjẹ́ níbẹ̀ ni wọ́n sì tẹ́ Jesu sí, nítorí ìpalẹ̀mọ́ àwọn Júù; àti nítorí ibojì náà wà nítòsí.
Amo gele gelabo da gadeneiba: le, amola aya da Sa: bade eso amo ilia dawa: beba: le, ela da amo ganodini Yesu Ea da: i hodo sali.