< John 19 >
1 Nítorí náà ni Pilatu mú Jesu, ó sì nà án.
Bilatus mali Yeesu.
2 Àwọn ọmọ-ogun sì hun adé ẹ̀gún, wọ́n sì fi dé e ní orí, wọ́n sì fi aṣọ ìgúnwà elése àlùkò wọ̀ ọ́.
nob gwam nebo ku yilang duwe la cin yo Yeesu neti dor cin mer ciyene beller liyar.
3 Wọ́n sì wí pé, “Kábíyèsí, ọba àwọn Júù!” Wọ́n sì fi ọwọ́ wọn gbá a ní ojú.
cin bo fiye co wiye ciki dumwe a kutange liya Yafudawa. la ci tee co.
4 Pilatu sì tún jáde, ó sì wí fún wọn pé, “Wò ó, mo mú u jáde tọ̀ yín wá, kí ẹ̀yin kí ó lè mọ̀ pé, èmi kò rí ẹ̀ṣẹ̀ kan lọ́wọ́ rẹ̀.”
Bilatus yila ceri kale yi ci to man bo kumen ki nii co be no kom nyomom mafiya cubo ki kange bwirangke”
5 Nítorí náà Jesu jáde wá, ti òun ti adé ẹ̀gún àti aṣọ elése àlùkò. Pilatu sì wí fún wọn pé, “Ẹ wò ọkùnrin náà!”
Yeesu cero ki yilangk duwek cwakek kange kure na liyaro ce Bilatus ki nii co wo.
6 Nítorí náà nígbà tí àwọn olórí àlùfáà, àti àwọn oníṣẹ́ rí i, wọ́n kígbe wí pé, “Kàn án mọ́ àgbélébùú, kàn án mọ́ àgbélébùú.” Pilatu wí fún wọn pé, “Ẹ mú un fún ara yín, kí ẹ sì kàn án mọ́ àgbélébùú: nítorí èmi kò rí ẹ̀ṣẹ̀ lọ́wọ́ rẹ̀.”
kange nobo dur webero wali kange tikertiyeu cin tam Yeesu, dila ci kwakiyyangti ciki a kulkenso, kulkenso la Bilatu ki kom tuco kom kulken mi mafiya chobo ki kerobwidi.”
7 Àwọn Júù dá a lóhùn wí pé, “Àwa ní òfin kan, àti gẹ́gẹ́ bí òfin, wa ó yẹ fún un láti kú, nítorí ó gbà pé Ọmọ Ọlọ́run ni òun ń ṣe.”
la Yafudawa ci yi coki yonweki bwirangka kange nurwarka con daten bwar wori cin nyoken dorcero na bi bwe kwama”
8 Nítorí náà nígbà tí Pilatu gbọ́ ọ̀rọ̀ yìí, ẹ̀rù túbọ̀ bà á.
Bilatu nuwa kero wo nyori la con cwa coko.
9 Ó sì tún wọ inú gbọ̀ngàn ìdájọ́ lọ, ó sì wí fún Jesu pé, “Níbo ni ìwọ ti wá?” Ṣùgbọ́n Jesu kò dá a lóhùn.
yila daten bwar kun gwam na, nyi Yeesu mocelufe?” layecu bciya cinen bo.
10 Nítorí náà, Pilatu wí fún un pé, “Èmi ni ìwọ kò fọhùn sí? Ìwọ kò mọ̀ pé, èmi ní agbára láti dá ọ sílẹ̀, èmi sì ní agbára láti kàn ọ́ mọ́ àgbélébùú?”
la Bikatu yico ki mani ma ciyayeti? mo nyombo miweki bigwan inyagum kan mwe, yila ma nyamgu kanti. kurkene
11 Jesu dá a lóhùn pé, “Ìwọ kì bá tí ní agbára kan lórí mi, bí kò ṣe pé a fi í fún ọ láti òkè wá, nítorí náà ẹni tí ó fi mí lé ọ lọ́wọ́ ni ó ní ẹ̀ṣẹ̀ pọ̀jù.”
Yeesu diye cine, mo manki be gwam dor mi naci, ne nefiren di kwamari, nyori wo neke ye moneneu co nii bwirangkeu,”
12 Nítorí èyí, Pilatu ń wá ọ̀nà láti dá a sílẹ̀, ṣùgbọ́n àwọn Júù kígbe, wí pé, “Bí ìwọ bá dá ọkùnrin yìí sílẹ̀, ìwọ kì í ṣe ọ̀rẹ́ Kesari: ẹnikẹ́ni tí ó bá ṣe ara rẹ̀ ní ọba, ó sọ̀rọ̀-òdì sí Kesari.”
dila co nuwa nyori, la Bilatu mani naci yemgum kancine, la Yafudawa kun dir ciyero ciki na mo nyongum nii wo nindi bo kebo farar kaicar no nii wo tuken dor cero na liyari, in kan kaicar ni.
13 Nítorí náà nígbà tí Pilatu gbọ́ ọ̀rọ̀ wọ̀nyí, ó mú Jesu jáde wá, ó sì jókòó lórí ìtẹ́ ìdájọ́ ní ibi tí a ń pè ní Òkúta-títẹ́, ṣùgbọ́n ní èdè Heberu, Gabata.
la Bilatu nurank kero belonabo la celu ki Yeesu kare nyara. nyike kabum kutirece fiye cico tike fiye bwirangke wo Yafudawa co tiki Gabbata”
14 Ó jẹ́ ìpalẹ̀mọ́ àjọ ìrékọjá, ó sì jẹ́ ìwọ̀n wákàtí ẹ̀kẹfà: Ó sì wí fún àwọn Júù pé, “Ẹ wo ọba yín!”
ki kakukowo ci yelank, lank dulubme yamkati, ki kwama kene nukune. la ki kakun, Bilatu yi Yafudawa “liya kume wo”
15 Nítorí náà wọ́n kígbe wí pé, “Mú un kúrò, mú un kúrò. Kàn án mọ́ àgbélébùú.” Pilatu wí fún wọn pé, “Èmi yóò ha kan ọba yín mọ́ àgbélébùú bí?” Àwọn olórí àlùfáà dáhùn wí pé, “Àwa kò ní ọba bí kò ṣe Kesari.”
la ci kwadiro yangenki co, yanken ki co. Bilatu nyi ci ki kulken liya kume ka? la nobo dur wabero ki cin manki liya kange no kebo kaicar dii.
16 Nítorí náà ni Pilatu fà á lé wọn lọ́wọ́ láti kàn án mọ́ àgbélébùú. Àwọn ológun gba Jesu lọ́wọ́ Pilatu.
la Bilatu nici Yeesu naci kulken co.
17 Nítorí náà, wọ́n mú Jesu, ó sì jáde lọ, ó ru àgbélébùú fúnra rẹ̀ sí ibi tí à ń pè ní ibi agbárí, ní èdè Heberu tí à ń pè ní Gọlgọta.
la cin yeken ki Yeesu cero ki beteren bwiti yakenti cuika fiwo Yafudawa coti ki golgota”
18 Níbi tí wọ́n gbé kàn án mọ́ àgbélébùú, àti àwọn méjì mìíràn pẹ̀lú rẹ̀, níhà ìhín àti níhà kejì, Jesu sì wà láàrín.
cin kulken Yeesu fiye co nobo kangum nyob, kulken ci Yeesu la tiber cinyer.
19 Pilatu sì kọ ìwé kan pẹ̀lú, ó sì fi lé e lórí àgbélébùú náà. Ohun tí a sì kọ ni, Jesu ti Nasareti Ọba àwọn Júù.
Bilatu mulangti yurombo dor bentilen bwetiye YEESU BANAZARE, LIYA YAFUDAWA.
20 Nítorí náà, ọ̀pọ̀ àwọn Júù ni ó ka ìwé àkọlé yìí, nítorí ibi tí a gbé kan Jesu mọ́ àgbélébùú súnmọ́ etí ìlú, a sì kọ ọ́ ní èdè Heberu àti Latin, àti ti Giriki.
Yafuda duco cin kiye yurom bowo wori fiye ci nyom Yeesu wiyeu bi dom kange cinalou.
21 Nítorí náà àwọn olórí àlùfáà àwọn Júù wí fún Pilatu pé, “Má ṣe kọ, ‘Ọba àwọn Júù,’ ṣùgbọ́n pé ọkùnrin yìí wí pé, èmi ni ọba àwọn Júù.”
la nobo dur waber Yafudawa, ci yi Bilatu ki mulangti muki liya Yafudawa. mulang moki yiki co liya Yafudawa.””
22 Pilatu dáhùn pé, ohun tí mo ti kọ, mo ti kọ ọ́.
Bilatu ciya, ki dii kewo co.
23 Nígbà náà ni àwọn ọmọ-ogun, nígbà tí wọ́n kan Jesu mọ́ àgbélébùú tán, wọ́n mú aṣọ rẹ̀, wọ́n sì pín wọn sí ipa mẹ́rin, apá kan fún ọmọ-ogun kọ̀ọ̀kan, àti ẹ̀wù àwọ̀tẹ́lẹ̀ rẹ̀, ṣùgbọ́n ẹ̀wù àwọ̀tẹ́lẹ̀ náà kò ní ojúràn-án, wọ́n hun ún láti òkè títí jálẹ̀.
la nob bi gwanem cin kulken Yeesu ci worangum billeceu kifiti nyo nar, nob bigwanebo ki ciye, yilank ciyegu woranm tau dii yanken cu co bitine.
24 Nítorí náà wọ́n wí fún ara wọn pé, “Ẹ má jẹ́ kí a fà á ya, ṣùgbọ́n kí a ṣẹ́ gègé nítorí rẹ̀.” Ti ẹni tí yóò jẹ́: kí ìwé mímọ́ kí ó le ṣẹ, tí ó wí pé, “Wọ́n pín aṣọ mi láàrín ara wọn, wọ́n sì ṣẹ́ gègé fún aṣọ ìlekè mi.” Nǹkan wọ̀nyí ni àwọn ọmọ-ogun ṣe.
la ciyi bwiti tii cike bo worak bilengke ci nyib dige co toke birinka wori kom ki kom ne bilengke
25 Ìyá Jesu àti arábìnrin ìyá rẹ̀ Maria aya Kilopa, àti Maria Magdalene sì dúró níbi àgbélébùú,
nob bigwan nebo balangum dikge wo no Yeesu, kange yitim cobo kange maryamu weikilofa, kange maryamu magadaliya. natuwo tim bidom kange fiye ci nyom Yeesu wii ye.
26 nígbà tí Jesu rí ìyá rẹ̀ àti ọmọ-ẹ̀yìn náà dúró, ẹni tí Jesu fẹ́ràn, ó wí fún ìyá rẹ̀ pé, “Obìnrin, wo ọmọ rẹ!”
la Yeesu to neceri kange nii bwangka wo co cwitiye tem bidom, yiki to na we to be bweme.”
27 Lẹ́yìn náà ni ó sì wí fún ọmọ-ẹ̀yìn náà pé, “Wo ìyá rẹ!” Láti wákàtí náà lọ ni ọmọ-ẹ̀yìn náà sì ti mú un lọ sí ilé ara rẹ̀.
la to nii bwanka, to nemwen nob bwangka ce co tuco yangke co ko lo.
28 Lẹ́yìn èyí, bí Jesu ti mọ̀ pé, a ti parí ohun gbogbo tán, kí ìwé mímọ́ bà á lè ṣẹ, ó wí pé, “Òrùngbẹ ń gbẹ mí.”
na wo nyeu Yeesu nyumom digero mor kwamare ma dim. la nyi ciki co nuwa durometi
29 Ohun èlò kan tí ó kún fún ọtí kíkan wà níbẹ̀, wọ́n tẹ kànìnkànìn tí ó kún fún ọtí kíkan bọ inú rẹ̀, wọ́n sì fi lé orí igi hísópù, wọ́n sì nà án sí i lẹ́nu.
cwi kanciyen kollo timwe ki mwebo fur cin doti cukko mwero bwotiye kange cin neco nico.
30 Nígbà tí Jesu sì ti gba ọtí kíkan náà, ó wí pé, “Ó parí!” Ó sì tẹ orí rẹ̀ ba, ó jọ̀wọ́ ẹ̀mí rẹ̀.
la Yeesu cun mobowo furi nyori “laye ciki dim la cunke ki dor cero lademkan dume ce ni.
31 Nítorí ó jẹ́ ọjọ́ ìpalẹ̀mọ́, kí òkú wọn má ba à wà lórí àgbélébùú ní ọjọ́ ìsinmi (nítorí ọjọ́ ńlá ni ọjọ́ ìsinmi náà), nítorí náà, àwọn Júù bẹ Pilatu pé kí a ṣẹ́ egungun itan wọn, kí a sì gbé wọn kúrò.
la Yafudawa, wori kakun yerank kari ci domti bwiciye dor bantilank bwe tiye na yaken kaku foka (wori kakun furkako nyori fiyeci weye) cin kinan Bilatu na ciyeco na cugum ci
32 Nítorí náà, àwọn ọmọ-ogun wá, wọ́n sì ṣẹ́ egungun itan ti èkínní, àti ti èkejì, tí a kàn mọ́ àgbélébùú pẹ̀lú rẹ̀.
la nob bigwannebo bo. kiyalum na nubo burumbo nii kaba nii yobe bulo ci yuci wori kange Yeesu.
33 Ṣùgbọ́n nígbà tí wọ́n dé ọ̀dọ̀ Jesu, tí wọ́n sì rí i pé ó ti kú, wọn kò ṣẹ́ egungun itan rẹ̀,
cin bou cifiya Yeesu bweyam ci keyanbo na ciyeko.
34 ṣùgbọ́n ọ̀kan nínú àwọn ọmọ-ogun náà fi ọ̀kọ̀ gún un lẹ́gbẹ̀ẹ́, lójúkan náà, ẹ̀jẹ̀ àti omi sì tú jáde.
dila wii nob bi gwanne boning gwico kiya dange buyare kange mwebo ti ceri.
35 Ẹni tí ó rí sì jẹ́rìí, òtítọ́ sì ni ẹ̀rí rẹ̀, ó sì mọ̀ pé òtítọ́ ni òun sọ, kí ẹ̀yin ba à lè gbàgbọ́.
buro towo ciya yilam nii warka. warka ceco birinke.
36 Nǹkan wọ̀nyí ṣe, kí ìwé mímọ́ ba à lè ṣẹ, tí ó wí pé, “A kì yóò fọ́ egungun rẹ̀.”
ci tokwo naci dim bifumer kwamaro kunko kange mani wo ciya kiyan tiye.”
37 Ìwé mímọ́ mìíràn pẹ̀lú sì wí pé, “Wọn ó máa wo ẹni tí a gún lọ́kọ̀.”
kange bifumero toki, bon nii wo cikwareu.
38 Lẹ́yìn nǹkan wọ̀nyí ní Josẹfu ará Arimatea, ẹni tí ó jẹ́ ọmọ-ẹ̀yìn Jesu, ní ìkọ̀kọ̀, nítorí ìbẹ̀rù àwọn Júù, o bẹ Pilatu kí òun lè gbé òkú Jesu kúrò, Pilatu sì fún un ní àṣẹ. Nígbà náà ni ó wá, ó sì gbé òkú Jesu lọ.
bwiko dige borumbo, Yusufu nii Armatiya, con wi win mor nob tomange Yeesu, dila temi tai Yafudawa, yaken Bilatu a naco bwi Yeesu. Bilatu neco, Yusufu bõti bwiyo.
39 Nikodemu pẹ̀lú sì wá, ẹni tí ó tọ Jesu wá lóru lákọ̀ọ́kọ́, ó sì mú àdàpọ̀ òjìá àti aloe wá, ó tó ìwọ̀n ọgọ́rùn-ún lita.
ni ko dimu ken bõ wuro ki kabo bõ Yeesu nin ki dila bõnuwan ficange womur doceu kange alul wo lam tutum cwanka kweni kwabe.
40 Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n gbé òkú Jesu, wọ́n sì fi aṣọ ọ̀gbọ̀ dì í pẹ̀lú tùràrí, gẹ́gẹ́ bí ìṣe àwọn Júù ti rí ní ìsìnkú wọn.
dila ci tuti bwi Yeesu ciyoken co yilanforka kange nuko ficen ficenye. naci yimkan bõ na nur banka Yafudawa ceu.
41 Àgbàlá kan sì wà níbi tí a gbé kàn án mọ́ àgbélébùú; ibojì tuntun kan sì wà nínú àgbàlá náà, nínú èyí tí a kò tí ì tẹ́ ẹnìkan sí rí.
fiye ciya ci yumce we kange tekewi, muro tekeu tuwe kangewi woci forumbo nii weye.
42 Ǹjẹ́ níbẹ̀ ni wọ́n sì tẹ́ Jesu sí, nítorí ìpalẹ̀mọ́ àwọn Júù; àti nítorí ibojì náà wà nítòsí.
du waleu kaku yolanka Yafudawa tuwe bi la ci dogken Yeesu borece.