< John 15 >

1 “Èmi ni àjàrà tòótọ́, Baba mi sì ni olùṣọ́gbà.
Mina ngilivini eliqotho, njalo uBaba ungumlimi.
2 Gbogbo ẹ̀ka nínú mi tí kò bá so èso, òun a mú kúrò, gbogbo ẹ̀ka tí ó bá sì so èso, òun a wẹ̀ ẹ́ mọ́, kí ó lè so èso sí i.
Lonke ugatsha olukimi olungatheliyo isithelo, uyalususa; lalo lonke oluthela isithelo, uyaluthena, ukuze lwengeze ukuthela.
3 Ẹ̀yin mọ́ nísinsin yìí nítorí ọ̀rọ̀ tí mo ti sọ fún yín.
Selihlambululekile lina ngelizwi engilikhulume kini.
4 Ẹ máa gbé inú mi, èmi ó sì máa gbé inú yín. Gẹ́gẹ́ bí ẹ̀ka kò ti lè so èso fún ara rẹ̀ bí kò ṣe pé ó ba ń gbé inú àjàrà, bẹ́ẹ̀ ni ẹ̀yin, bí kò ṣe pé ẹ bá ń gbé inú mi.
Hlalani kimi, lami kini. Njengalokhu ugatsha lungethele isithelo ngokwalo, uba lungahlali evinini, ngokunjalo lani lingeke, uba lingahlali kimi.
5 “Èmi ni àjàrà, ẹ̀yin ni ẹ̀ka. Ẹni tí ó ń gbé inú mi, àti èmi nínú rẹ̀, òun ni yóò so èso lọ́pọ̀lọ́pọ̀, nítorí ní yíya ara yín kúrò lọ́dọ̀ mi, ẹ kò lè ṣe ohun kan.
Mina ngilivini, lina lizingatsha. Lowo ohlala kimi, lami kuye, yena uyathela isithelo sande; ngoba ngaphandle kwami lingenze lutho.
6 Bí ẹnìkan kò bá gbé inú mi, a gbé e sọnù gẹ́gẹ́ bí ẹ̀ka, a sì gbẹ; wọn a sì kó wọn jọ, wọn a sì sọ wọ́n sínú iná, wọn a sì jóná.
Uba umuntu engahlali kimi, ulahlelwa phandle njengogatsha, abe esebuna, bazibuthe baziphose emlilweni, zitshiswe.
7 Bí ẹ̀yin bá ń gbé inú mi, tí ọ̀rọ̀ mi bá sì gbé inú yín, ẹ ó béèrè ohunkóhun tí ẹ bá fẹ́, a ó sì ṣe é fún yín.
Uba lihlala kimi, lamazwi ami ehlala kini, lizacela elikuthandayo, lizakwenzelwa.
8 Nínú èyí ní a yìn Baba mi lógo pé, kí ẹ̀yin kí ó máa so èso púpọ̀; ẹ̀yin ó sì jẹ́ ọmọ-ẹ̀yìn mi.
UBaba uyadunyiswa ngalokhu, ukuthi lithele isithelo sande; njalo lizakuba ngabafundi bami.
9 “Gẹ́gẹ́ bí Baba ti fẹ́ mi, bẹ́ẹ̀ ni èmi sì fẹ́ yín, ẹ dúró nínú ìfẹ́ rẹ̀.
Njengalokhu uBaba engithandile, lami ngilithandile; hlalani ethandweni lwami.
10 Bí ẹ̀yin bá pa òfin mi mọ́, ẹ ó dúró nínú ìfẹ́ mi; gẹ́gẹ́ bí èmi ti pa òfin Baba mi mọ́, tí mo sì dúró nínú ìfẹ́ rẹ̀.
Uba lilondoloza imilayo yami, lizahlala ethandweni lwami; njengalokhu mina ngilondoloze imilayo kaBaba, njalo ngihlala ethandweni lwakhe.
11 Nǹkan wọ̀nyí ni mo ti sọ fún yín, kí ayọ̀ mi kí ó lè wà nínú yín, àti kí ayọ̀ yín kí ó lè kún.
Lezizinto ngizikhulume kini, ukuze intokozo yami ihlale kini, njalo intokozo yenu igcwale.
12 Èyí ni òfin mi, pé kí ẹ̀yin kí ó fẹ́ràn ara yín, gẹ́gẹ́ bí mo ti fẹ́ràn yín.
Lo ngumlayo wami, ukuthi lithandane, njengalokhu ngilithandile.
13 Kò sí ẹnìkan tí ó ní ìfẹ́ tí ó tóbi ju èyí lọ, pé ẹnìkan fi ẹ̀mí rẹ̀ lélẹ̀ nítorí àwọn ọ̀rẹ́ rẹ̀.
Kakho olothando olukhulu kulalolu, lokuthi umuntu ababekele phansi abangane bakhe impilo yakhe.
14 Ọ̀rẹ́ mi ni ẹ̀yin ń ṣe, bí ẹ bá ṣe ohun tí èmi pàṣẹ fún yín.
Lina lingabangane bami, uba lisenza loba yini mina engililaya yona.
15 Èmi kò pè yín ní ọmọ ọ̀dọ̀ mọ́; nítorí ọmọ ọ̀dọ̀ kò mọ ohun tí olúwa rẹ̀ ń ṣe, ṣùgbọ́n èmi pè yín ní ọ̀rẹ́ nítorí ohun gbogbo tí mo ti gbọ́ láti ọ̀dọ̀ Baba mi wá, mo ti fihàn fún yín.
Kangisalibizi ngokuthi lizinceku, ngoba inceku kayikwazi ukuthi inkosi yayo yenzani; kodwa sengilibize ngokuthi lingabangane, ngoba konke engikuzwileyo kuBaba ngilazise khona.
16 Kì í ṣe ẹ̀yin ni ó yàn mí, ṣùgbọ́n èmi ni ó yàn yín, mo sì fi yín sípò, kí ẹ̀yin kí ó lè lọ, kí ẹ sì so èso, àti kí èso yín lè dúró; kí ohunkóhun tí ẹ bá béèrè lọ́wọ́ Baba ní orúkọ mi, kí ó lè fi í fún yín.
Kalingikhethanga lina, kodwa mina ngilikhethile, njalo ngilimisile, ukuze lina lihambe lithele isithelo, lesithelo senu sihlale; ukuze loba yini eliyicela kuBaba ngebizo lami, alinike.
17 Nǹkan wọ̀nyí ni mo pàṣẹ fún yín pé, kí ẹ̀yin kí ó fẹ́ràn ara yín.
Ngililaya lezizinto, ukuze lithandane.
18 “Bí ayé bá kórìíra yín, ẹ mọ̀ pé, ó ti kórìíra mi ṣáájú yín.
Uba umhlaba ulizonda, yazini ukuthi wangizonda mina ngaphambi kwenu.
19 Ìbá ṣe pé ẹ̀yin ń ṣe ti ayé, ayé ìbá fẹ́ yin bi àwọn tirẹ̀; gẹ́gẹ́ bi o ṣe ri tí ẹ̀yin kì ń ṣe ti ayé, ṣùgbọ́n èmi ti yàn yín kúrò nínú ayé, nítorí èyí ni ayé ṣe kórìíra yín.
Uba belingabomhlaba, umhlaba ubuzathanda abawo; kodwa ngoba lingeyisibo abomhlaba, kodwa ngalikhetha mina emhlabeni, ngakho umhlaba uyalizonda.
20 Ẹ rántí ọ̀rọ̀ tí mo ti sọ fún yín pé, ‘Ọmọ ọ̀dọ̀ kò tóbi ju olúwa rẹ̀ lọ.’ Bí wọ́n bá ti ṣe inúnibíni sí mi, wọ́n ó ṣe inúnibíni sí yín pẹ̀lú: bí wọ́n bá ti pa ọ̀rọ̀ mi mọ́, wọ́n ó sì pa tiyín mọ́ pẹ̀lú.
Khumbulani ilizwi mina engalitsho kini: Inceku kayinkulu kulenkosi yayo. Uba bengizingele mina, bazalizingela lani; uba belondoloza ilizwi lami, bazalondoloza lelenu.
21 Ṣùgbọ́n gbogbo nǹkan wọ̀nyí ni wọ́n yóò ṣe sí yín, nítorí orúkọ mi, nítorí tí wọn kò mọ ẹni tí ó rán mi.
Kodwa bazakwenza konke lokhu ngenxa yebizo lami, ngoba bengamazi ongithumileyo.
22 Ìbá ṣe pé èmi kò ti wá kí n sì ti bá wọn sọ̀rọ̀, wọn kì bá tí ní ẹ̀ṣẹ̀, ṣùgbọ́n nísinsin yìí wọ́n di aláìríwí fún ẹ̀ṣẹ̀ wọn.
Uba bengingafikanga ngakhuluma labo, ngabe kabalasono; kodwa khathesi kabalazaba ngesono sabo.
23 Ẹni tí ó bá kórìíra mi, ó kórìíra Baba mi pẹ̀lú.
Ongizondayo, uzonda loBaba.
24 Ìbá ṣe pé èmi kò ti ṣe iṣẹ́ wọ̀n-ọn-nì láàrín wọn tí ẹlòmíràn kò ṣe rí, wọn kì bá tí ní ẹ̀ṣẹ̀, ṣùgbọ́n nísinsin yìí wọ́n sì rí, wọ́n sì kórìíra èmi àti Baba mi.
Uba bengingenzanga phakathi kwabo imisebenzi kungekho omunye owayenzayo, ngabe kabalasono; kodwa khathesi sebeyibonile sebezonde sonke mina loBaba.
25 Ṣùgbọ́n èyí rí bẹ́ẹ̀ kí ọ̀rọ̀ tí a kọ nínú òfin wọn kí ó lè ṣẹ pé, ‘Wọ́n kórìíra mi ní àìnídìí.’
Kodwa ukuze ligcwaliseke ilizwi elilotshiweyo emlayweni wabo elokuthi: Bangizonda kungelasizatho.
26 “Ṣùgbọ́n nígbà tí Olùtùnú náà bá dé, ẹni tí èmi ó rán sí yín láti ọ̀dọ̀ Baba wá, àní Ẹ̀mí òtítọ́ nì, tí ń ti ọ̀dọ̀ Baba wá, òun náà ni yóò jẹ́rìí mi.
Kodwa nxa esefikile uMduduzi, engizamthuma mina kini evela kuBaba, uMoya weqiniso, ophuma kuBaba, lo uzangifakazela;
27 Ẹ̀yin pẹ̀lú yóò sì jẹ́rìí mi, nítorí tí ẹ̀yin ti wà pẹ̀lú mi láti ìpilẹ̀ṣẹ̀ wá.
lani futhi lizafakaza, ngoba belilami kusukela ekuqaleni.

< John 15 >