< John 12 >
1 Nítorí náà, nígbà tí àjọ ìrékọjá ku ọjọ́ mẹ́fà, Jesu wá sí Betani, níbi tí Lasaru wà, ẹni tí ó ti kú, tí Jesu jí dìde kúrò nínú òkú.
និស្តារោត្សវាត៑ បូវ៌្វំ ទិនឞដ្កេ ស្ថិតេ យីឝុ រ្យំ ប្រមីតម៑ ឥលិយាសរំ ឝ្មឝានាទ៑ ឧទស្ថាបរត៑ តស្យ និវាសស្ថានំ ពៃថនិយាគ្រាមម៑ អាគច្ឆត៑។
2 Wọ́n sì ṣe àsè alẹ́ fún un níbẹ̀. Marta sì ń ṣe ìránṣẹ́, ṣùgbọ́n Lasaru jẹ́ ọ̀kan nínú àwọn tí ó jókòó níbi tábìlì rẹ̀.
តត្រ តទត៌្ហំ រជន្យាំ ភោជ្យេ ក្ឫតេ មត៌្ហា បយ៌្យវេឞយទ៑ ឥលិយាសរ៑ ច តស្យ សង្គិភិះ សាទ៌្ធំ ភោជនាសន ឧបាវិឝត៑។
3 Nígbà náà ni Maria mú òróró ìkunra nadi, òsùwọ̀n lita kan, àìlábùlà, olówó iyebíye, ó sì ń fi kun Jesu ní ẹsẹ̀, ó sì ń fi irun orí rẹ̀ nu ẹsẹ̀ rẹ̀ nù. Ilé sì kún fún òórùn ìkunra náà.
តទា មរិយម៑ អទ៌្ធសេដកំ ពហុមូល្យំ ជដាមាំសីយំ តៃលម៑ អានីយ យីឝោឝ្ចរណយោ រ្មទ៌្ទយិត្វា និជកេឝ រ្មាឞ៌្ដុម៑ អារភត; តទា តៃលស្យ បរិមលេន គ្ឫហម៑ អាមោទិតម៑ អភវត៑។
4 Nígbà náà ni ọ̀kan nínú àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀, Judasi Iskariotu, ọmọ Simoni ẹni tí yóò fi í hàn, wí pé,
យះ ឝិមោនះ បុត្រ រិឞ្ករិយោតីយោ យិហូទានាមា យីឝុំ បរករេឞុ សមប៌យិឞ្យតិ ស ឝិឞ្យស្តទា កថិតវាន៑,
5 “Èéṣe tí a kò ta òróró ìkunra yìí ní ọ̀ọ́dúnrún owó idẹ kí a sì fi fún àwọn tálákà?”
ឯតត្តៃលំ ត្រិភិះ ឝតៃ រ្មុទ្រាបទៃ រ្វិក្រីតំ សទ៑ ទរិទ្រេភ្យះ កុតោ នាទីយត?
6 Ṣùgbọ́n ó wí èyí, kì í ṣe nítorí tí ó náání àwọn tálákà; ṣùgbọ́n nítorí tí ó jẹ́ olè, òun ni ó ni àpò, a sì máa jí ohun tí a fi sínú rẹ̀ láti fi ran ara rẹ lọ́wọ́.
ស ទរិទ្រលោកាត៌្ហម៑ អចិន្តយទ៑ ឥតិ ន, កិន្តុ ស ចៅរ ឯវំ តន្និកដេ មុទ្រាសម្បុដកស្ថិត្យា តន្មធ្យេ យទតិឞ្ឋត៑ តទបាហរត៑ តស្មាត៑ ការណាទ៑ ឥមាំ កថាមកថយត៑។
7 Nígbà náà ni Jesu wí pé, “Ẹ fi í sílẹ̀, ó ṣe é sílẹ̀ de ọjọ́ ìsìnkú mi.
តទា យីឝុរកថយទ៑ ឯនាំ មា វារយ សា មម ឝ្មឝានស្ថាបនទិនាត៌្ហំ តទរក្ឞយត៑។
8 Nígbà gbogbo ni ẹ̀yin sá à ní tálákà pẹ̀lú yín; ṣùgbọ́n èmi ni ẹ kò ní nígbà gbogbo.”
ទរិទ្រា យុឞ្មាកំ សន្និធៅ សវ៌្វទា តិឞ្ឋន្តិ កិន្ត្វហំ សវ៌្វទា យុឞ្មាកំ សន្និធៅ ន តិឞ្ឋាមិ។
9 Nítorí náà, ìjọ ènìyàn nínú àwọn Júù ni ó mọ̀ pé ó wà níbẹ̀; wọ́n sì wá, kì í ṣe nítorí Jesu nìkan, ṣùgbọ́n kí wọn lè rí Lasaru pẹ̀lú, ẹni tí ó ti jí dìde kúrò nínú òkú.
តតះ បរំ យីឝុស្តត្រាស្តីតិ វាត៌្តាំ ឝ្រុត្វា ពហវោ យិហូទីយាស្តំ ឝ្មឝានាទុត្ថាបិតម៑ ឥលិយាសរញ្ច ទ្រឞ្ដុំ តត៑ ស្ថានម៑ អាគច្ឆន។
10 Ṣùgbọ́n àwọn olórí àlùfáà gbìmọ̀ kí wọn lè pa Lasaru pẹ̀lú,
តទា ប្រធានយាជកាស្តម៑ ឥលិយាសរមបិ សំហត៌្តុម៑ អមន្ត្រយន៑;
11 nítorí pé nípasẹ̀ rẹ̀ ni ọ̀pọ̀ nínú àwọn Júù jáde lọ, wọ́n sì gbà Jesu gbọ́.
យតស្តេន ពហវោ យិហូទីយា គត្វា យីឝៅ វ្យឝ្វសន៑។
12 Ní ọjọ́ kejì nígbà tí ọ̀pọ̀ ènìyàn tí ó wá sí àjọ gbọ́ pé, Jesu ń bọ̀ wá sí Jerusalẹmu.
អនន្តរំ យីឝុ រ្យិរូឝាលម៑ នគរម៑ អាគច្ឆតីតិ វាត៌្តាំ ឝ្រុត្វា បរេៜហនិ ឧត្សវាគតា ពហវោ លោកាះ
13 Wọ́n mú imọ̀ ọ̀pẹ, wọ́n sì jáde lọ pàdé rẹ̀, wọ́n sì ń kígbe pé, “Hosana!” “Olùbùkún ni ẹni tí ń bọ̀ wá ní orúkọ Olúwa!” “Olùbùkún ni ọba Israẹli!”
ខជ៌្ជូរបត្រាទ្យានីយ តំ សាក្ឞាត៑ កត៌្តុំ ពហិរាគត្យ ជយ ជយេតិ វាចំ ប្រោច្ចៃ រ្វក្តុម៑ អារភន្ត, ឥស្រាយេលោ យោ រាជា បរមេឝ្វរស្យ នាម្នាគច្ឆតិ ស ធន្យះ។
14 Nígbà tí Jesu sì rí ọmọ kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ kan, ó gùn ún; gẹ́gẹ́ bí a ti kọ̀wé pé,
តទា "ហេ សិយោនះ កន្យេ មា ភៃឞីះ បឝ្យាយំ តវ រាជា គទ៌្ទភឝាវកម៑ អារុហ្យាគច្ឆតិ"
15 “Má bẹ̀rù, ọmọbìnrin Sioni; wò ó, ọba rẹ ń bọ̀ wá, o jókòó lórí ọmọ kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́.”
ឥតិ ឝាស្ត្រីយវចនានុសារេណ យីឝុរេកំ យុវគទ៌្ទភំ ប្រាប្យ តទុបយ៌្យារោហត៑។
16 Nǹkan wọ̀nyí kò tètè yé àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀, ṣùgbọ́n nígbà tí a ṣe Jesu lógo, nígbà náà ni wọ́n rántí pé, a kọ̀wé nǹkan wọ̀nyí nípa rẹ̀ sí i.
អស្យាះ ឃដនាយាស្តាត្បយ៌្យំ ឝិឞ្យាះ ប្រថមំ នាពុធ្យន្ត, កិន្តុ យីឝៅ មហិមានំ ប្រាប្តេ សតិ វាក្យមិទំ តស្មិន អកថ្យត លោកាឝ្ច តម្ប្រតីត្ថម៑ អកុវ៌្វន៑ ឥតិ តេ ស្ម្ឫតវន្តះ។
17 Nítorí náà, ìjọ ènìyàn tí ó wà lọ́dọ̀ rẹ̀ nígbà tí o pé Lasaru jáde nínú ibojì rẹ̀, tí ó sì jí i dìde kúrò nínú òkú, jẹ́rìí sí i.
ស ឥលិយាសរំ ឝ្មឝានាទ៑ អាគន្តុម៑ អាហ្វតវាន៑ ឝ្មឝានាញ្ច ឧទស្ថាបយទ៑ យេ យេ លោកាស្តត្កម៌្យ សាក្ឞាទ៑ អបឝ្យន៑ តេ ប្រមាណំ ទាតុម៑ អារភន្ត។
18 Nítorí èyí ni ìjọ ènìyàn sì ṣe lọ pàdé rẹ̀, nítorí tí wọ́n gbọ́ pé ó ti ṣe iṣẹ́ àmì yìí.
ស ឯតាទ្ឫឝម៑ អទ្ភុតំ កម៌្មករោត៑ តស្យ ជនឝ្រុតេ រ្លោកាស្តំ សាក្ឞាត៑ កត៌្តុម៑ អាគច្ឆន៑។
19 Nítorí náà àwọn Farisi wí fún ara wọn pé, “Ẹ kíyèsi bí ẹ kò ti lè borí ní ohunkóhun? Ẹ wo bí gbogbo ayé ti ń wọ́ tọ̀ ọ́!”
តតះ ផិរូឝិនះ បរស្បរំ វក្តុម៑ អារភន្ត យុឞ្មាកំ សវ៌្វាឝ្ចេឞ្ដា វ្ឫថា ជាតាះ, ឥតិ កិំ យូយំ ន ពុធ្យធ្វេ? បឝ្យត សវ៌្វេ លោកាស្តស្យ បឝ្ចាទ្វត៌្តិនោភវន៑។
20 Àwọn Giriki kan sì wà nínú àwọn tí ó gòkè wá láti sìn nígbà àjọ,
ភជនំ កត៌្តុម៑ ឧត្សវាគតានាំ លោកានាំ កតិបយា ជនា អន្យទេឝីយា អាសន៑,
21 Àwọn wọ̀nyí ni ó tọ Filipi wá, ẹni tí í ṣe ará Betisaida tí Galili, wọ́n sì ń béèrè lọ́wọ́ rẹ̀, pé, “Alàgbà, àwa ń fẹ́ rí Jesu!”
តេ គាលីលីយពៃត្សៃទានិវាសិនះ ផិលិបស្យ សមីបម៑ អាគត្យ វ្យាហរន៑ ហេ មហេច្ឆ វយំ យីឝុំ ទ្រឞ្ដុម៑ ឥច្ឆាមះ។
22 Filipi wá, ó sì sọ fún Anderu; Anderu àti Filipi wá, wọ́n sì sọ fún Jesu.
តតះ ផិលិបោ គត្វា អាន្ទ្រិយម៑ អវទត៑ បឝ្ចាទ៑ អាន្ទ្រិយផិលិបៅ យីឝវេ វាត៌្តាម៑ អកថយតាំ។
23 Jesu sì dá wọn lóhùn pé, “Wákàtí náà dé, tí a ó ṣe Ọmọ Ènìyàn lógo.
តទា យីឝុះ ប្រត្យុទិតវាន៑ មានវសុតស្យ មហិមប្រាប្តិសមយ ឧបស្ថិតះ។
24 Lóòótọ́, lóòótọ́ ni mo wí fún yín, bí kò ṣe pé alikama bá bọ́ sí ilẹ̀, tí ó bá sì kú, ó wà ní òun nìkan; ṣùgbọ́n bí ó bá kú, yóò sì so ọ̀pọ̀lọpọ̀ èso.
អហំ យុឞ្មានតិយថាត៌្ហំ វទាមិ, ធាន្យពីជំ ម្ឫត្តិកាយាំ បតិត្វា យទិ ន ម្ឫយតេ តហ៌្យេកាកី តិឞ្ឋតិ កិន្តុ យទិ ម្ឫយតេ តហ៌ិ ពហុគុណំ ផលំ ផលតិ។
25 Ẹni tí ó bá fẹ́ ẹ̀mí rẹ̀ yóò sọ ọ́ nù; ẹni tí ó bá sì kórìíra ẹ̀mí rẹ̀ láyé yìí ni yóò sì pa á mọ́ títí ó fi di ìyè àìnípẹ̀kun. (aiōnios )
យោ ជនេ និជប្រាណាន៑ ប្រិយាន៑ ជានាតិ ស តាន៑ ហារយិឞ្យតិ កិន្តុ យេ ជន ឥហលោកេ និជប្រាណាន៑ អប្រិយាន៑ ជានាតិ សេនន្តាយុះ ប្រាប្តុំ តាន៑ រក្ឞិឞ្យតិ។ (aiōnios )
26 Bí ẹnikẹ́ni bá ń sìn mí, kí ó máa tọ̀ mí lẹ́yìn, àti pe níbi tí èmi bá wà, níbẹ̀ ni ìránṣẹ́ mi yóò wà pẹ̀lú, bí ẹnikẹ́ni bá ń sìn mí, òun ni Baba yóò bu ọlá fún.
កឝ្ចិទ៑ យទិ មម សេវកោ ភវិតុំ វាញ្ឆតិ តហ៌ិ ស មម បឝ្ចាទ្គាមី ភវតុ, តស្មាទ៑ អហំ យត្រ តិឞ្ឋាមិ មម សេវកេបិ តត្រ ស្ថាស្យតិ; យោ ជនោ មាំ សេវតេ មម បិតាបិ តំ សម្មំស្យតេ។
27 “Ní ìsinsin yìí ni a ń pọ́n ọkàn mi lójú; kín ni èmi ó sì wí? ‘Baba, gbà mí kúrò nínú wákàtí yìí’? Rárá, ṣùgbọ́n nítorí èyí ni mo ṣe wá sí wákàtí yìí.
សាម្ប្រតំ មម ប្រាណា វ្យាកុលា ភវន្តិ, តស្មាទ៑ ហេ បិតរ ឯតស្មាត៑ សមយាន៑ មាំ រក្ឞ, ឥត្យហំ កិំ ប្រាត៌្ហយិឞ្យេ? កិន្ត្វហម៑ ឯតត្សមយាត៌្ហម៑ អវតីណ៌វាន៑។
28 Baba, ṣe orúkọ rẹ lógo!” Nígbà náà ni ohùn kan ti ọ̀run wá, wí pé, “Èmi ti ṣe é lógo!”
ហេ បិត: ស្វនាម្នោ មហិមានំ ប្រកាឝយ; តនៃវ ស្វនាម្នោ មហិមានម៑ អហំ ប្រាកាឝយំ បុនរបិ ប្រកាឝយិឞ្យាមិ, ឯឞា គគណីយា វាណី តស្មិន៑ សមយេៜជាយត។
29 Nítorí náà ìjọ ènìyàn tí ó dúró níbẹ̀, tí wọ́n sì gbọ́ ọ, wí pé, “Àrá ń sán.” Àwọn ẹlòmíràn wí pé, “Angẹli kan ni ó ń bá a sọ̀rọ̀.”
តច្ឝ្រុត្វា សមីបស្ថលោកានាំ កេចិទ៑ អវទន៑ មេឃោៜគជ៌ីត៑, កេចិទ៑ អវទន៑ ស្វគ៌ីយទូតោៜនេន សហ កថាមចកថត៑។
30 Jesu sì dáhùn wí pé, “Kì í ṣe nítorí mi ni ohùn yìí ṣe wá, bí kò ṣe nítorí yín.
តទា យីឝុះ ប្រត្យវាទីត៑, មទត៌្ហំ ឝព្ទោយំ នាភូត៑ យុឞ្មទត៌្ហមេវាភូត៑។
31 Ní ìsinsin yìí ni ìdájọ́ ayé yìí dé: nísinsin yìí ni a ó lé aládé ayé yìí jáde.
អធុនា ជគតោស្យ វិចារ: សម្បត្ស្យតេ, អធុនាស្យ ជគត: បតី រាជ្យាត៑ ច្យោឞ្យតិ។
32 Àti èmi, bí a bá gbé mi sókè kúrò ní ayé, èmi ó fa gbogbo ènìyàn sọ́dọ̀ ara mi!”
យទ្យឦ ប្ឫថិវ្យា ឩទ៌្វ្វេ ប្រោត្ថាបិតោស្មិ តហ៌ិ សវ៌្វាន៑ មានវាន៑ ស្វសមីបម៑ អាកឞ៌ិឞ្យាមិ។
33 Ṣùgbọ́n ó wí èyí, ó ń ṣe àpẹẹrẹ irú ikú tí òun yóò kú.
កថំ តស្យ ម្ឫតិ រ្ភវិឞ្យតិ, ឯតទ៑ ពោធយិតុំ ស ឥមាំ កថាម៑ អកថយត៑។
34 Nítorí náà àwọn ìjọ ènìyàn dá a lóhùn pé, “Àwa gbọ́ nínú òfin pé, Kristi wà títí láéláé, ìwọ ha ṣe wí pé, ‘A ó gbé Ọmọ Ènìyàn sókè’? Ta ni ó ń jẹ́ ‘Ọmọ Ènìyàn yìí’?” (aiōn )
តទា លោកា អកថយន៑ សោភិឞិក្តះ សវ៌្វទា តិឞ្ឋតីតិ វ្យវស្ថាគ្រន្ថេ ឝ្រុតម៑ អស្មាភិះ, តហ៌ិ មនុឞ្យបុត្រះ ប្រោត្ថាបិតោ ភវិឞ្យតីតិ វាក្យំ កថំ វទសិ? មនុឞ្យបុត្រោយំ កះ? (aiōn )
35 Nígbà náà ni Jesu wí fún wọn pé, “Nígbà díẹ̀ sí i ni ìmọ́lẹ̀ wà láàrín yín, ẹ máa rìn nígbà tí ẹ̀yin ní ìmọ́lẹ̀, kí òkùnkùn má ṣe bá yín, ẹni tí ó bá sì ń rìn ní òkùnkùn kò mọ ibi òun ń lọ.
តទា យីឝុរកថាយទ៑ យុឞ្មាភិះ សាទ៌្ធម៑ អល្បទិនានិ ជ្យោតិរាស្តេ, យថា យុឞ្មាន៑ អន្ធការោ នាច្ឆាទយតិ តទត៌្ហំ យាវត្កាលំ យុឞ្មាភិះ សាទ៌្ធំ ជ្យោតិស្តិឞ្ឋតិ តាវត្កាលំ គច្ឆត; យោ ជនោៜន្ធការេ គច្ឆតិ ស កុត្រ យាតីតិ ន ជានាតិ។
36 Nígbà tí ẹ̀yin ní ìmọ́lẹ̀, ẹ gba ìmọ́lẹ̀ gbọ́, kí ẹ lè jẹ́ ọmọ ìmọ́lẹ̀!” Nǹkan wọ̀nyí ni Jesu sọ, ó sì jáde lọ, ó fi ara pamọ́ fún wọn.
អតឯវ យាវត្កាលំ យុឞ្មាកំ និកដេ ជ្យោតិរាស្តេ តាវត្កាលំ ជ្យោតីរូបសន្តានា ភវិតុំ ជ្យោតិឞិ វិឝ្វសិត; ឥមាំ កថាំ កថយិត្វា យីឝុះ ប្រស្ថាយ តេភ្យះ ស្វំ គុប្តវាន៑។
37 Ṣùgbọ́n bí ó ti ṣe ọ̀pọ̀lọpọ̀ iṣẹ́ àmì tó báyìí lójú wọn, wọn kò gbà á gbọ́.
យទ្យបិ យីឝុស្តេឞាំ សមក្ឞម៑ ឯតាវទាឝ្ចយ៌្យកម៌្មាណិ ក្ឫតវាន៑ តថាបិ តេ តស្មិន៑ ន វ្យឝ្វសន៑។
38 Kí ọ̀rọ̀ wòlíì Isaiah lè ṣẹ, èyí tí ó sọ pé, “Olúwa, ta ni ó gba ìwàásù wa gbọ́ Àti ta ni a sì fi apá Olúwa hàn fún?”
អតឯវ កះ ប្រត្យេតិ សុសំវាទំ បរេឝាស្មត៑ ប្រចារិតំ? ប្រកាឝតេ បរេឝស្យ ហស្តះ កស្យ ច សន្និធៅ? យិឝយិយភវិឞ្យទ្វាទិនា យទេតទ៑ វាក្យមុក្តំ តត៑ សផលម៑ អភវត៑។
39 Nítorí èyí ni wọn kò fi lè gbàgbọ́, nítorí Isaiah sì tún sọ pé,
តេ ប្រត្យេតុំ នាឝន្កុវន៑ តស្មិន៑ យិឝយិយភវិឞ្យទ្វាទិ បុនរវាទីទ៑,
40 “Ó ti fọ́ wọn lójú, Ó sì ti sé àyà wọn le; kí wọn má ba à fi ojú wọn rí, kí wọn má ba à fi ọkàn wọn mọ̀, kí wọn má ba à yípadà, kí èmi má ba à mú wọn láradá.”
យទា, "តេ នយនៃ រ្ន បឝ្យន្តិ ពុទ្ធិភិឝ្ច ន ពុធ្យន្តេ តៃ រ្មនះសុ បរិវត៌្តិតេឞុ ច តានហំ យថា ស្វស្ថាន៑ ន ករោមិ តថា ស តេឞាំ លោចនាន្យន្ធានិ ក្ឫត្វា តេឞាមន្តះករណានិ គាឍានិ ករិឞ្យតិ។ "
41 Nǹkan wọ̀nyí ni Isaiah wí, nítorí ó ti rí ògo rẹ̀, ó sì sọ̀rọ̀ rẹ̀.
យិឝយិយោ យទា យីឝោ រ្មហិមានំ វិលោក្យ តស្មិន៑ កថាមកថយត៑ តទា ភវិឞ្យទ្វាក្យម៑ ឦទ្ឫឝំ ប្រកាឝយត៑។
42 Síbẹ̀ ọ̀pọ̀ nínú àwọn olórí gbà á gbọ́ pẹ̀lú; ṣùgbọ́n nítorí àwọn Farisi wọn kò jẹ́wọ́ rẹ̀, kí a má ba à yọ wọ́n kúrò nínú Sinagọgu,
តថាប្យធិបតិនាំ ពហវស្តស្មិន៑ ប្រត្យាយន៑។ កិន្តុ ផិរូឝិនស្តាន៑ ភជនគ្ឫហាទ៑ ទូរីកុវ៌្វន្តីតិ ភយាត៑ តេ តំ ន ស្វីក្ឫតវន្តះ។
43 nítorí wọ́n fẹ́ ìyìn ènìyàn ju ìyìn ti Ọlọ́run lọ.
យត ឦឝ្វរស្យ ប្រឝំសាតោ មានវានាំ ប្រឝំសាយាំ តេៜប្រិយន្ត។
44 Jesu sì kígbe ó sì wí pé, “Ẹni tí ó bá gbà mí gbọ́, èmi kọ́ ni ó gbàgbọ́ ṣùgbọ́n ẹni tí ó rán mi.
តទា យីឝុរុច្ចៃះការម៑ អកថយទ៑ យោ ជនោ មយិ វិឝ្វសិតិ ស កេវលេ មយិ វិឝ្វសិតីតិ ន, ស មត្ប្រេរកេៜបិ វិឝ្វសិតិ។
45 Ẹni tí ó bá sì rí mi, ó rí ẹni tí ó rán mi.
យោ ជនោ មាំ បឝ្យតិ ស មត្ប្រេរកមបិ បឝ្យតិ។
46 Èmi ni ìmọ́lẹ̀ tí ó wá sí ayé, kí ẹnikẹ́ni tí ó bá gbà mí gbọ́ má ṣe wà nínú òkùnkùn.
យោ ជនោ មាំ ប្រត្យេតិ ស យថាន្ធការេ ន តិឞ្ឋតិ តទត៌្ហម៑ អហំ ជ្យោតិះស្វរូបោ ភូត្វា ជគត្យស្មិន៑ អវតីណ៌វាន៑។
47 “Bí ẹnikẹ́ni bá sì gbọ́ ọ̀rọ̀ mi, tí kò sì pa wọ́n mọ́, èmi kì yóò ṣe ìdájọ́ rẹ̀ nítorí tí èmi kò wá láti ṣe ìdájọ́ ayé, bí kò ṣe láti gba ayé là.
មម កថាំ ឝ្រុត្វា យទិ កឝ្ចិន៑ ន វិឝ្វសិតិ តហ៌ិ តមហំ ទោឞិណំ ន ករោមិ, យតោ ហេតោ រ្ជគតោ ជនានាំ ទោឞាន៑ និឝ្ចិតាន៑ កត៌្តុំ នាគត្យ តាន៑ បរិចាតុម៑ អាគតោស្មិ។
48 Ẹni tí ó bá kọ̀ mí, tí kò sì gba ọ̀rọ̀ mi, ó ní ẹnìkan tí ń ṣe ìdájọ́ rẹ̀; ọ̀rọ̀ tí mo ti sọ, òun náà ni yóò ṣe ìdájọ́ rẹ̀ ní ọjọ́ ìkẹyìn.
យះ កឝ្ចិន៑ មាំ ន ឝ្រទ្ធាយ មម កថំ ន គ្ឫហ្លាតិ, អន្យស្តំ ទោឞិណំ ករិឞ្យតិ វស្តុតស្តុ យាំ កថាមហម៑ អចកថំ សា កថា ចរមេៜន្ហិ តំ ទោឞិណំ ករិឞ្យតិ។
49 Nítorí èmi kò dá ọ̀rọ̀ sọ fún ara mi, ṣùgbọ́n Baba tí ó rán mi, ni ó ti fún mi ní àṣẹ, ohun tí èmi ó sọ, àti èyí tí èmi ó wí.
យតោ ហេតោរហំ ស្វតះ កិមបិ ន កថយាមិ, កិំ កិំ មយា កថយិតវ្យំ កិំ សមុបទេឞ្ដវ្យញ្ច ឥតិ មត្ប្រេរយិតា បិតា មាមាជ្ញាបយត៑។
50 Èmi sì mọ̀ pé ìyè àìnípẹ̀kun ni òfin rẹ̀, nítorí náà, àwọn ohun tí mo bá wí, gẹ́gẹ́ bí Baba ti sọ fún mi, bẹ́ẹ̀ ni mo wí!” (aiōnios )
តស្យ សាជ្ញា អនន្តាយុរិត្យហំ ជានាមិ, អតឯវាហំ យត៑ កថយាមិ តត៑ បិតា យថាជ្ញាបយត៑ តថៃវ កថយាម្យហម៑។ (aiōnios )