< John 11 >

1 Ara ọkùnrin kan kò sì dá, Lasaru, ará Betani, tí í ṣe ìlú Maria àti Marta arábìnrin rẹ̀.
Omuntu omo itawa lyakwe ali yo Lazalo ali bhinu. Afumiye hu Bethania, eshijiji sha Mariamu na odaada wakwe oMasa.
2 Maria náà ni ẹni tí ó fi òróró ìkunra kun Olúwa, tí ó sì fi irun orí rẹ̀ nù ún, arákùnrin rẹ̀ ni Lasaru í ṣe, ara ẹni tí kò dá.
Ali yo Mariamu yayola wapeshe Ogosi Amarhamu na hufute amagaga gakwe hwii sisi lyakwe, ola oholo wakwe oLazalo wali bhinu.
3 Nítorí náà, àwọn arábìnrin rẹ̀ ránṣẹ́ sí i, wí pé, “Olúwa, wò ó, ara ẹni tí ìwọ fẹ́ràn kò dá.”
Ailombo ebha bhatumile oujumbe hwa Yesu na yanje, “Gosi, enya ola wogene abhawa.”
4 Nígbà tí Jesu sì gbọ́, ó wí pé, “Àìsàn yìí kì í ṣe sí ikú, ṣùgbọ́n fún ògo Ọlọ́run, kí a lè yin Ọmọ Ọlọ́run lógo nípasẹ̀ rẹ̀.”
O Yesu na honvwa ajile, “Empongo ene se yafwe, ila, baada yeshoye umwamihwe wa Ngolobhe aje Omwana wa Ngolobhe apate amwamihwe ashilile hwenyo empongo.”
5 Jesu sì fẹ́ràn Marta, àti arábìnrin rẹ̀ àti Lasaru.
O Yesu agene oMasa no dada wakwe no Lazalo.
6 Nítorí náà, nígbà tí ó ti gbọ́ pé, ara rẹ̀ kò dá, ó gbé ọjọ́ méjì sí i níbìkan náà tí ó gbé wà.
Lwa honvwezye aje oLozalo bhinu, oYesu akheye insiku izbhele ashizanye pala pahali.
7 Ǹjẹ́ lẹ́yìn èyí ni ó wí fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ pé, “Ẹ jẹ́ kí a tún padà lọ sí Judea.”
Eshi baada yelyo abhabhozya abhanafunzi bhakwe, “Saali huu Yahudi nantele.”
8 Àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ sì wí fún un pé, “Rabbi, ní àìpẹ́ yìí ni àwọn Júù ń wá ọ̀nà láti sọ ọ́ ní òkúta; ìwọ sì tún padà lọ síbẹ̀?”
Abhanafunzi bhabhozya, “Mwalimu, Ayahudi bhali bhalenga ahupole na mawe, na aweohonza awele hwohwo nantele?”
9 Jesu dáhùn pé, “Wákàtí méjìlá kọ́ ni ó bẹ nínú ọ̀sán kan bí? Bí ẹnìkan bá rìn ní ọ̀sán, kì yóò kọsẹ̀, nítorí tí ó rí ìmọ́lẹ̀ ayé yìí.
O Yesu ayanga, “Esala zya pasanya sezili kumi ne zibhele? Omuntu ajenda pasanya sawezizye abomele, afuatanaje alola hulukhozyo lwa pasanya.
10 Ṣùgbọ́n bí ẹnìkan bá rìn ní òru, yóò kọsẹ̀, nítorí tí kò sí ìmọ́lẹ̀ nínú rẹ̀.”
Ata sheshi nkashe anzajende no siku, anzabomele afuatanaje olukhozyo nalumo muhati yakwe.”
11 Nǹkan wọ̀nyí ni ó sọ, lẹ́yìn èyí nì ó sì wí fún wọn pé, “Lasaru ọ̀rẹ́ wa sùn; ṣùgbọ́n èmi ń lọ kí èmi kí ó lè jí i dìde nínú orun rẹ̀.”
O Yesu ayanga enongwa ezi, baada ye nongwa ezi, abhabhozya, “Owamwetu oLazalo agonile, ila embala aje empate ahubhosye afume mutulo.”
12 Nítorí náà àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ wí fún un pé, “Olúwa, bí ó bá ṣe pé ó sùn, yóò sàn.”
Abhanafunzi bhabhozya, “Gosi, nkashe agonile, anzabhoshe.
13 Ṣùgbọ́n Jesu ń sọ ti ikú rẹ̀, ṣùgbọ́n wọ́n rò pé, ó ń sọ ti orun sísùn.
Ensiku izyo oYesu ali ayanga ahusu enfwa ya Lazalo, ila abhene bhamenye aje ayanga ahusu agone otulo.
14 Nígbà náà ni Jesu wí fún wọn gbangba pé, “Lasaru ti kú.
O Yesu nkayanga na bhene pazelu pazelu, “O Lazalo afwiye.
15 Èmi sì yọ̀ nítorí yín, tí èmi kò sí níbẹ̀. Kí ẹ le gbàgbọ́; ṣùgbọ́n ẹ jẹ́ kí a lọ sọ́dọ̀ rẹ̀.”
Lusongwo lwendiinalwo hulimwe aje senahali hula aje mubhe no lweteshelo. Saali hwa mwene.”
16 Nítorí náà Tomasi, ẹni tí à ń pè ní Didimu, wí fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn ẹgbẹ́ rẹ̀ pé, “Ẹ jẹ́ kí àwa náà lọ, kí a lè bá a kú pẹ̀lú.”
O Tomaso wa hetwaga Pacha, abhozya abhanafunzi amwabho, “Nate saalitifwe pamo no Yesu.”
17 Nítorí náà nígbà tí Jesu dé, ó rí i pé a ti tẹ́ ẹ sínú ibojì ní ọjọ́ mẹ́rin ná,
O Yesu lwa henzaga amweje oLazalo akheye mwilende insiku zine.
18 ǹjẹ́ Betani súnmọ́ Jerusalẹmu tó ibùsọ̀ mẹ́ẹ̀ẹ́dógún.
Yope e Bethania yaali pepe ne Yelusalemu nanshi ekilometa arubaini ne zisanu eshi.
19 Ọ̀pọ̀ nínú àwọn Júù sì wá sọ́dọ̀ Marta àti Maria láti tù wọ́n nínú nítorí ti arákùnrin wọn.
Abhinji kati ya Yahudi bhahenzele hwa Masa no Mariamu abhazinde alengane no holo wabho.
20 Nítorí náà, nígbà tí Marta gbọ́ pé Jesu ń bọ̀ wá, ó jáde lọ pàdé rẹ̀, ṣùgbọ́n Maria jókòó nínú ilé.
O Masa ahonvwa aje oYesu ahwenza, abhalile akhomane nawo, ila oMariamu ahendeleye akhale pakhaya.
21 Nígbà náà, ni Marta wí fún Jesu pé, “Olúwa, ìbá ṣe pé ìwọ ti wà níhìn-ín, arákùnrin mi kì bá kú.
O Masa abhozya oYesu, “Gosi, nkashe ogabhiye epa, okolo wane handa safwiye.
22 Ṣùgbọ́n nísinsin yìí náà, mo mọ̀ pé, ohunkóhun tí ìwọ bá béèrè lọ́wọ́ Ọlọ́run, Ọlọ́run yóò fi fún ọ.”
Ata sheshehwelewa aje lyalyonti lyobhalabhe afume hwa Ngolobhe, anzahupele.”
23 Jesu wí fún un pé, “Arákùnrin rẹ yóò jíǹde.”
O Yesu abhozya, okolo waho anzavyoshe nantele.”
24 Marta wí fún un pé, “Mo mọ̀ pé yóò jíǹde ní àjíǹde ìkẹyìn.”
O Masa abhozya, emenye aje anzavyonshe huu vyoho wi siku lya mwisho.”
25 Jesu wí fún un pé, “Èmi ni àjíǹde àti ìyè, ẹni tí ó bá gbà mí gbọ́, bí ó tilẹ̀ kú, yóò yè.
O Yesu abhozya, “Ane endi luvionsyono womi; omwane waneteshela, ata nkashe aifwa, hata sheshi aibha ahwizya;
26 Ẹnikẹ́ni tí ó ń bẹ láààyè, tí ó sì gbà mí gbọ́, kì yóò kú láéláé ìwọ gbà èyí gbọ́?” (aiōn g165)
no mwene wahwizya na netehsele ane saga ifwa. Uhweteshela eli?” (aiōn g165)
27 Ó wí fún un pé, “Bẹ́ẹ̀ ni, Olúwa, èmi gbàgbọ́ pé, ìwọ ni Kristi náà Ọmọ Ọlọ́run, ẹni tí ń bọ̀ wá sí ayé.”
Wabhozya aje, “'Sawa, Gosi ehweteshela aje awe oli Kilisiti, Mwana wa Ngolobhe, omwene wa hwenza munsi.”
28 Nígbà tí ó sì ti wí èyí tan, ó lọ, ó sì pe Maria arábìnrin rẹ̀ sẹ́yìn wí pé, “Olùkọ́ dé, ó sì ń pè ọ́.”
Nahamala ayanje eli, abhalile ahukwizye odada wakwe oMariamu hufaraga. Ajile, “Omwalimu ali epa nantele ahukwizya.”
29 Nígbà tí ó gbọ́, ó dìde lọ́gán, ó sì wá sọ́dọ̀ rẹ̀.
O Mariamu na hovwezye ega, abhoshele nanali na bhale hwa Yesu.
30 Jesu kò tí ì wọ ìlú, ṣùgbọ́n ó wà ní ibi kan náà tí Marta ti pàdé rẹ̀.
Wope oYesu ali sayenzele aliseele muhati ye shijiji, aliseele lwa khomanaga no Masa.
31 Nígbà tí àwọn Júù tí ó wà lọ́dọ̀ rẹ̀ nínú ilé, tí wọ́n ń tù ú nínú rí Maria tí ó dìde kánkán, tí ó sì jáde, wọ́n tẹ̀lé, wọ́n ṣe bí ó ń lọ sí ibojì láti sọkún níbẹ̀.
Ayahudi bhabhali no Maliamu munyumba na bhala bhabhli wahuzinda, bhabhoshele nanali na afume honze, bhalondoleye; bhamenye aje abhala hwi kaburi aje alile ohwo.
32 Nígbà tí Maria sì dé ibi tí Jesu wà, tí ó sì rí i, ó wólẹ̀ lẹ́bàá ẹsẹ̀ rẹ̀, ó wí fún un pé, “Olúwa, ìbá ṣe pé ìwọ ti wà níhìn-ín, arákùnrin mi kì bá kú.”
O Mariamu, ahafiha pala oYesu palolaga na agwiye pansi pamagaga gakwe na hobhozye, “Gosi, nkashe ogahali epa, oholo wane hande sagaafwiye.”
33 Nígbà tí Jesu rí i, tí ó ń sọkún, àti àwọn Júù tí ó bá a wá ń sọkún pẹ̀lú rẹ̀, ó kérora nínú ẹ̀mí, inú rẹ̀ sì bàjẹ́.
O Yesu nalola alila, na Ayahudi bhahenzele pamo nawo bhali bhalila huu moyo gabho na sebhelele;
34 Ó sì wí pé, “Níbo ni ẹ̀yin gbé tẹ́ ẹ sí?” Wọ́n sì wí fún un pé, “Olúwa, wá wò ó.”
ajile, “Mugonizye hwii? Bhabhozye, Gosi, enza oyenye.”
35 Jesu sọkún.
O Yesu alilile.
36 Nítorí náà àwọn Júù wí pé, “Sá wò ó bí ó ti fẹ́ràn rẹ̀ tó!”
Ayahudi nkabhayanga, “Oyenye sha gene oLazalo!”
37 Àwọn kan nínú wọn sì wí pé, “Ọkùnrin yìí, ẹni tí ó la ojú afọ́jú, kò lè ṣe é kí ọkùnrin yìí má kú bí?”
Bhamo muhati yabho bhajile, “Sio yayono, omuntu wabhombile amaso gola wali mpofu, sagabhombile ono muntu aje agaje afwe?”
38 Nígbà náà ni Jesu tún kérora nínú ara rẹ̀, ó wá sí ibojì, ó sì jẹ́ ihò, a sì gbé òkúta lé ẹnu rẹ̀.
O Yesu alilaga humwoyo gwakwe nantele, abhalile hwi lende. Hwali ligwenya, niiwe libhehwele pamwanya lyakwe.
39 Jesu wí pé, “Ẹ gbé òkúta náà kúrò!” Marta, arábìnrin ẹni tí ó kú náà wí fún un pé, “Olúwa, ó ti ń rùn nísinsin yìí, nítorí pé ó di ọjọ́ kẹrin tí ó tí kú.”
O Yesu ajile, “Lyefwi iwe.” O Masa, oilombo wakwe oLazalo, omwene wafwiye, abhozya oYesu, “Gosi, hu muda ogu, obele gubhabhe gu bholile, alenganaje ali fwee ensiku zine.”
40 Jesu wí fún un pé, “Èmi kò ti wí fún ọ pé, bí ìwọ bá gbàgbọ́, ìwọ yóò rí ògo Ọlọ́run?”
O Yesu abhozya, “Ane senabhozezye aje, nkashe ohweteshela, obhaulole oumwamu wa Ngolobhe?”
41 Nígbà náà ni wọ́n gbé òkúta náà kúrò (níbi tí a tẹ́ ẹ sí). Jesu sì gbé ojú rẹ̀ sókè, ó sì wí pé, “Baba, mo dúpẹ́ lọ́wọ́ rẹ nítorí tí ìwọ gbọ́ tèmi.
Nnkabhalyefwa iwe. O Yesu abhosya amaso gakwe amwanya naje, “Daada, ehusombezya afuatanaje onomvwa.
42 Èmi sì ti mọ̀ pé, ìwọ a máa gbọ́ ti èmi nígbà gbogbo, ṣùgbọ́n nítorí ìjọ ènìyàn tí ó dúró yìí ni mo ṣe wí i, kí wọn ba à lè gbàgbọ́ pé ìwọ ni ó rán mi.”
Namenye aje ononvwa omuda gwonti, ila alengane no lubhongano lwalwe meleye anzongole aje enjanjile ega, aje bhapate ahweteshele aje awe ontumile.”
43 Nígbà tí ó sì wí bẹ́ẹ̀ tan, ó kígbe lóhùn rara pé, “Lasaru, jáde wá.”
Naayanga ega, alilile hwizu igosi, “Lazalo, fuma honze!”
44 Ẹni tí ó kú náà sì jáde wá, tí a fi aṣọ òkú dì tọwọ́ tẹsẹ̀ a sì fi gèlè dì í lójú. Jesu wí fún wọn pé, “Ẹ tú u, ẹ sì jẹ́ kí ó máa lọ!”
Ofwe afumile honze apinyilwe amakhono na magaga husanda zyakhatile, na amaso gakwe apinyilwe ne shitambala.” O Yesu abhabhozya, “Mwigulili muleshele abhalaje.”
45 Nítorí náà ni ọ̀pọ̀ àwọn Júù tí ó wá sọ́dọ̀ Maria, tí wọ́n rí ohun tí Jesu ṣe, ṣe gbà á gbọ́.
Oyahudi abhinji bhabhahenzele hwa Mariamu nalole oYesu habhombaga, bhamweteshela;
46 Ṣùgbọ́n àwọn ẹlòmíràn nínú wọn tọ àwọn Farisi lọ, wọ́n sì sọ fún wọn ohun tí Jesu ṣe.
bhamo bhabhalile hwa Mafarisayo na bhabhozye enongwa zyazibhombile oYesu.
47 Nígbà náà ni àwọn olórí àlùfáà àti àwọn Farisi pe ìgbìmọ̀ jọ. Wọ́n sì wí pé, “Kín ni yóò jẹ àṣeyọrí wa? Nítorí ọkùnrin yìí ń ṣe ọ̀pọ̀lọpọ̀ iṣẹ́ àmì.
Agosi bha dimi na Mafarisayo bhabhongene pandwemo mwi baraza na yaanje, “Tibhabhombe yenu? Omuntu ono abhoembombo enyinji.
48 Bí àwa bá fi í sílẹ̀ bẹ́ẹ̀, gbogbo ènìyàn ni yóò gbà á gbọ́, àwọn ará Romu yóò sì wá gba ilẹ̀ àti orílẹ̀-èdè wa pẹ̀lú.”
Nkashe tibhahuleshe eshi mwene, bhonti bhanza humweteshe; Alumi bhayenza na hweje vyonti evyetu ni taifa lyetu.”
49 Ṣùgbọ́n Kaiafa, ọ̀kan nínú wọn, ẹni tí í ṣe olórí àlùfáà ní ọdún náà, ó wí fún wọn pé, “Ẹ̀yin kò mọ ohunkóhun rárá!
Hata omuntu omuntu muhati yabho, oKayafa, waali dimi Ogosi omwaha ogwo, abhabhozya, “Semumenye hahonti.
50 Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò sì ronú pé, ó ṣàǹfààní fún wa, kí ènìyàn kan kú fún àwọn ènìyàn kí gbogbo orílẹ̀-èdè má ba à ṣègbé.”
Sahusebhelela aje ehwanziwa aje omuntu omo afwe esababu ya bhanje ashile itaifa lyonti na litega.”
51 Kì í ṣe fún ara rẹ̀ ni ó sọ èyí ṣùgbọ́n bí ó ti jẹ́ olórí àlùfáà ní ọdún náà, ó sọtẹ́lẹ̀ pé, Jesu yóò kú fún orílẹ̀-èdè náà,
Eege sohagayanjile afuatanaje no mwene, mhati yakwe, ali dimi ogosi omwaha gula, ayanjile aje oYesu aifwa sababu ya bha munsi;
52 kì sì í ṣe kìkì fún orílẹ̀-èdè náà nìkan, ṣùgbọ́n fún àwọn ọmọ Ọlọ́run tí ó fọ́nká kiri, kí ó le kó wọn papọ̀, kí ó sì sọ wọ́n di ọ̀kan.
na se huje hwabha munsi bhene ila oYesu apate abhabhonganye abhana bha Ngolobhe bhabha nyanpene hutali hutali.
53 Nítorí náà, láti ọjọ́ náà lọ ni wọ́n ti jọ gbìmọ̀ pọ̀ láti pa á.
Eshi ahwandile isiku elyo na hwendelela bhapanjile ahugoje oYesu.
54 Nítorí náà Jesu kò rìn ní gbangba láàrín àwọn Júù mọ́; ṣùgbọ́n ó ti ibẹ̀ lọ sí ìgbèríko kan tí ó súnmọ́ aginjù, sí ìlú ńlá kan tí a ń pè ní Efraimu, níbẹ̀ ni ó sì wà pẹ̀lú àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀.
O Yesu sagajendile apazelu pazelu hwa Yahudi, ila asogeye epa na bhale ensi yelipeepe ni poli hunsi yehwetwa Efraimu. Epo akheye nabhanafunzi.
55 Àjọ ìrékọjá àwọn Júù sì súnmọ́ etílé, ọ̀pọ̀lọpọ̀ láti ìgbèríko sì gòkè lọ sí Jerusalẹmu ṣáájú ìrékọjá, láti ya ara wọn sí mímọ́.
Epasaka ya Yahudi yali pepe, na bhinji bhazubhile abhale hu Yelusalemu honze yensi sheli sele ePasaka nkabhahwiyozye bhebho.
56 Nígbà náà ni wọ́n ń wá Jesu, wọ́n sì ń bá ara wọn sọ̀, bí wọ́n ti dúró ní tẹmpili, wí pé, “Kín ni ẹyin ti rò ó sí pé kì yóò wá sí àjọ?”
Bhali bha humwanza oYesu, na ayanje kila muntu na bhali bhemeleye mshibhanza, “Musebha yenu? Aje saga ayenza mushi kulukulu?”
57 Ǹjẹ́ àwọn olórí àlùfáà àti àwọn Farisi ti pàṣẹ pé bí ẹnìkan bá mọ ibi tí ó gbé wà, kí ó fi í hàn, kí wọn ba à lè mú un.
Owakati ou ogosi wa dimi na Mafarisayo bhali bhafumizye endajizyo aje nkashe omo aimanya oYesu hwali, ahwanziwa afumye etaarifa aje nkabhapate ahukhate.

< John 11 >