< John 11 >
1 Ara ọkùnrin kan kò sì dá, Lasaru, ará Betani, tí í ṣe ìlú Maria àti Marta arábìnrin rẹ̀.
Na rĩrĩ, kwarĩ na mũndũ wetagwo Lazaro, nake aarĩ mũrũaru. Aarĩ wa Bethania, itũũra rĩa Mariamu na mwarĩ wa nyina Maritha.
2 Maria náà ni ẹni tí ó fi òróró ìkunra kun Olúwa, tí ó sì fi irun orí rẹ̀ nù ún, arákùnrin rẹ̀ ni Lasaru í ṣe, ara ẹni tí kò dá.
Mariamu ũyũ nowe waitĩrĩirie Mwathani maguta manungi wega na akĩmũgiria nyarĩrĩ na njuĩrĩ yake, na aarĩ mwarĩ wa nyina na Lazaro ũcio warĩ mũrũaru.
3 Nítorí náà, àwọn arábìnrin rẹ̀ ránṣẹ́ sí i, wí pé, “Olúwa, wò ó, ara ẹni tí ìwọ fẹ́ràn kò dá.”
Nĩ ũndũ ũcio aarĩ acio a nyina magĩtũmanĩra Jesũ akeerwo atĩrĩ, “Mwathani, ũrĩa wendete nĩmũrũaru.”
4 Nígbà tí Jesu sì gbọ́, ó wí pé, “Àìsàn yìí kì í ṣe sí ikú, ṣùgbọ́n fún ògo Ọlọ́run, kí a lè yin Ọmọ Ọlọ́run lógo nípasẹ̀ rẹ̀.”
Rĩrĩa Jesũ aiguire ũhoro ũcio, akiuga atĩrĩ, “Ndwari ĩno ndĩkũrĩĩkĩrĩra na gĩkuũ. Aca, nĩ ya kũgoocithia Ngai, nĩgeetha Mũrũ wa Ngai agoocithio nĩyo.”
5 Jesu sì fẹ́ràn Marta, àti arábìnrin rẹ̀ àti Lasaru.
Jesũ nĩendete Maritha na mwarĩ wa nyina, o na Lazaro.
6 Nítorí náà, nígbà tí ó ti gbọ́ pé, ara rẹ̀ kò dá, ó gbé ọjọ́ méjì sí i níbìkan náà tí ó gbé wà.
No o na thuutha wa kũigua atĩ Lazaro aarĩ mũrũaru-rĩ, aikarire kũu aarĩ mĩthenya ĩngĩ ĩĩrĩ.
7 Ǹjẹ́ lẹ́yìn èyí ni ó wí fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ pé, “Ẹ jẹ́ kí a tún padà lọ sí Judea.”
Agĩcooka akĩĩra arutwo ake atĩrĩ, “Nĩtũcookei Judea.”
8 Àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ sì wí fún un pé, “Rabbi, ní àìpẹ́ yìí ni àwọn Júù ń wá ọ̀nà láti sọ ọ́ ní òkúta; ìwọ sì tún padà lọ síbẹ̀?”
Nao makĩmwĩra atĩrĩ, “No rĩrĩ Rabii, o rĩu ica ikuhĩ Ayahudi marageragia gũkũhũũra na mahiga nyuguto, na rĩu ũrenda gũcooka kuo?”
9 Jesu dáhùn pé, “Wákàtí méjìlá kọ́ ni ó bẹ nínú ọ̀sán kan bí? Bí ẹnìkan bá rìn ní ọ̀sán, kì yóò kọsẹ̀, nítorí tí ó rí ìmọ́lẹ̀ ayé yìí.
Nake Jesũ akĩmacookeria atĩrĩ, “Githĩ mũthenya ti wa mathaa ikũmi na meerĩ? Mũndũ ũrĩa ũthiiaga mũthenya ndangĩhĩngwo, nĩgũkorwo onaga na ũtheri wa gũkũ thĩ.
10 Ṣùgbọ́n bí ẹnìkan bá rìn ní òru, yóò kọsẹ̀, nítorí tí kò sí ìmọ́lẹ̀ nínú rẹ̀.”
Ahĩngagwo rĩrĩa egũthiĩ ũtukũ, nĩ ũndũ ndarĩ na ũtheri.”
11 Nǹkan wọ̀nyí ni ó sọ, lẹ́yìn èyí nì ó sì wí fún wọn pé, “Lasaru ọ̀rẹ́ wa sùn; ṣùgbọ́n èmi ń lọ kí èmi kí ó lè jí i dìde nínú orun rẹ̀.”
Aarĩkia kuuga ũguo, agĩcooka akĩmeera atĩrĩ, “Mũrata witũ Lazaro nĩakomete; no nĩngũthiĩ kũu ngamũũkĩrie.”
12 Nítorí náà àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ wí fún un pé, “Olúwa, bí ó bá ṣe pé ó sùn, yóò sàn.”
Arutwo ake makĩmũcookeria atĩrĩ, “Mwathani, akorwo nĩ gũkoma akomete-rĩ, nĩekũhona.”
13 Ṣùgbọ́n Jesu ń sọ ti ikú rẹ̀, ṣùgbọ́n wọ́n rò pé, ó ń sọ ti orun sísùn.
Jesũ aaragia ũhoro wa gĩkuũ gĩake, no arutwo ake meciiragia aaragia ũhoro wa toro wa ndũire.
14 Nígbà náà ni Jesu wí fún wọn gbangba pé, “Lasaru ti kú.
Nĩ ũndũ ũcio akĩmeera na njĩra ĩgũtaũka, atĩrĩ, “Lazaro nĩmũkuũ,
15 Èmi sì yọ̀ nítorí yín, tí èmi kò sí níbẹ̀. Kí ẹ le gbàgbọ́; ṣùgbọ́n ẹ jẹ́ kí a lọ sọ́dọ̀ rẹ̀.”
no nĩ ũndũ wanyu nĩngenete nĩgũkorwo ndiraarĩ kuo, nĩgeetha mwĩtĩkie. No rĩrĩ, nĩtũthiĩi kũrĩ we.”
16 Nítorí náà Tomasi, ẹni tí à ń pè ní Didimu, wí fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn ẹgbẹ́ rẹ̀ pé, “Ẹ jẹ́ kí àwa náà lọ, kí a lè bá a kú pẹ̀lú.”
Nake Toma (ũrĩa wetagwo Wa-mahatha) akĩĩra arutwo arĩa angĩ atĩrĩ, “Nĩtũthiĩi o na ithuĩ, tũgakuanĩre nake.”
17 Nítorí náà nígbà tí Jesu dé, ó rí i pé a ti tẹ́ ẹ sínú ibojì ní ọjọ́ mẹ́rin ná,
Jesũ aakinya-rĩ, agĩkora Lazaro nĩaniinĩte mĩthenya ĩna thĩinĩ wa mbĩrĩra.
18 ǹjẹ́ Betani súnmọ́ Jerusalẹmu tó ibùsọ̀ mẹ́ẹ̀ẹ́dógún.
Na rĩrĩ, itũũra rĩa Bethania rĩtiakinyĩtie kilomita ithatũ kuuma Jerusalemu,
19 Ọ̀pọ̀ nínú àwọn Júù sì wá sọ́dọ̀ Marta àti Maria láti tù wọ́n nínú nítorí ti arákùnrin wọn.
nao Ayahudi aingĩ nĩmokĩte kũu kwa Maritha na Mariamu kũmomĩrĩria nĩ ũndũ wa gũkuĩrwo nĩ mũrũ wa nyina wao.
20 Nítorí náà, nígbà tí Marta gbọ́ pé Jesu ń bọ̀ wá, ó jáde lọ pàdé rẹ̀, ṣùgbọ́n Maria jókòó nínú ilé.
Rĩrĩa Maritha aiguire atĩ Jesũ nĩarooka, akiuma, agĩthiĩ kũmũtũnga, no Mariamu agĩikara kũu mũciĩ.
21 Nígbà náà, ni Marta wí fún Jesu pé, “Olúwa, ìbá ṣe pé ìwọ ti wà níhìn-ín, arákùnrin mi kì bá kú.
Maritha akĩĩra Jesũ atĩrĩ, “Mwathani ũngĩraarĩ gũkũ-rĩ, mũrũ wa maitũ ndangĩrakuire.
22 Ṣùgbọ́n nísinsin yìí náà, mo mọ̀ pé, ohunkóhun tí ìwọ bá béèrè lọ́wọ́ Ọlọ́run, Ọlọ́run yóò fi fún ọ.”
No rĩrĩ, nĩnjũũĩ atĩ o na rĩu Ngai nĩegũkũhe o kĩrĩa gĩothe ũngĩhooya.”
23 Jesu wí fún un pé, “Arákùnrin rẹ yóò jíǹde.”
Nake Jesũ akĩmwĩra atĩrĩ, “Mũrũ wa maitũguo nĩekũriũka.” Nake Maritha akĩmũcookeria atĩrĩ,
24 Marta wí fún un pé, “Mo mọ̀ pé yóò jíǹde ní àjíǹde ìkẹyìn.”
“Nĩnjũũĩ nĩakariũka hĩndĩ ya iriũkĩro mũthenya wa mũthia.”
25 Jesu wí fún un pé, “Èmi ni àjíǹde àti ìyè, ẹni tí ó bá gbà mí gbọ́, bí ó tilẹ̀ kú, yóò yè.
Nake Jesũ akĩmwĩra atĩrĩ, “Niĩ nĩ niĩ kũriũka na nĩ niĩ muoyo. Nake ũrĩa wothe ũnjĩtĩkĩtie, o na aakua, nĩagatũũra muoyo;
26 Ẹnikẹ́ni tí ó ń bẹ láààyè, tí ó sì gbà mí gbọ́, kì yóò kú láéláé ìwọ gbà èyí gbọ́?” (aiōn )
nake ũrĩa wothe ũtũũraga muoyo na nĩanjĩtĩkĩtie, ndarĩ hĩndĩ agaakua. Wee nĩwĩtĩkĩtie ũguo?” (aiōn )
27 Ó wí fún un pé, “Bẹ́ẹ̀ ni, Olúwa, èmi gbàgbọ́ pé, ìwọ ni Kristi náà Ọmọ Ọlọ́run, ẹni tí ń bọ̀ wá sí ayé.”
Nake Maritha akĩmwĩra atĩrĩ, “Ĩĩ Mwathani, nĩnjĩtĩkĩtie atĩ wee nĩwe Kristũ, Mũrũ wa Ngai, ũrĩa wĩrĩtwo nĩagooka gũkũ thĩ.”
28 Nígbà tí ó sì ti wí èyí tan, ó lọ, ó sì pe Maria arábìnrin rẹ̀ sẹ́yìn wí pé, “Olùkọ́ dé, ó sì ń pè ọ́.”
Nake aarĩkia kuuga ũguo, agĩcooka agĩthiĩ agĩĩta mwarĩ wa nyina Mariamu keeheri-inĩ, akĩmwĩra atĩrĩ, “Mũrutani arĩ gũkũ na nĩarakũũria.”
29 Nígbà tí ó gbọ́, ó dìde lọ́gán, ó sì wá sọ́dọ̀ rẹ̀.
Rĩrĩa Mariamu aiguire ũguo, akĩrũgama na ihenya agĩthiĩ kũrĩ we.
30 Jesu kò tí ì wọ ìlú, ṣùgbọ́n ó wà ní ibi kan náà tí Marta ti pàdé rẹ̀.
Na hĩndĩ ĩyo Jesũ ndaakoretwo atoonyete itũũra, no aarĩ o harĩa Maritha aamũtũngĩte.
31 Nígbà tí àwọn Júù tí ó wà lọ́dọ̀ rẹ̀ nínú ilé, tí wọ́n ń tù ú nínú rí Maria tí ó dìde kánkán, tí ó sì jáde, wọ́n tẹ̀lé, wọ́n ṣe bí ó ń lọ sí ibojì láti sọkún níbẹ̀.
Rĩrĩa Ayahudi acio maarĩ na Mariamu kũu nyũmba makĩmũũmĩrĩria monire ũrĩa okĩra na ihenya oimĩte nja, makĩmũrũmĩrĩra, magĩĩciiria atĩ aathiiaga mbĩrĩra-inĩ akarĩrĩre ho.
32 Nígbà tí Maria sì dé ibi tí Jesu wà, tí ó sì rí i, ó wólẹ̀ lẹ́bàá ẹsẹ̀ rẹ̀, ó wí fún un pé, “Olúwa, ìbá ṣe pé ìwọ ti wà níhìn-ín, arákùnrin mi kì bá kú.”
Hĩndĩ ĩrĩa Mariamu aakinyire harĩa Jesũ aarĩ na akĩmuona, akĩgũa thĩ magũrũ-inĩ make, akĩmwĩra atĩrĩ, “Mwathani, ũngĩraarĩ gũkũ, mũrũ wa maitũ ndangĩrakuire.”
33 Nígbà tí Jesu rí i, tí ó ń sọkún, àti àwọn Júù tí ó bá a wá ń sọkún pẹ̀lú rẹ̀, ó kérora nínú ẹ̀mí, inú rẹ̀ sì bàjẹ́.
Hĩndĩ ĩrĩa Jesũ aamuonire akĩrĩra, na Ayahudi arĩa mokĩte hamwe nake o nao makĩrĩra-rĩ, agĩcaaya mũno roho-inĩ thĩinĩ na agĩtangĩka ngoro.
34 Ó sì wí pé, “Níbo ni ẹ̀yin gbé tẹ́ ẹ sí?” Wọ́n sì wí fún un pé, “Olúwa, wá wò ó.”
Akĩmooria atĩrĩ, “Mũmũigĩte ha?” Nao makĩmũcookeria atĩrĩ, “Mwathani, ũka wone.”
36 Nítorí náà àwọn Júù wí pé, “Sá wò ó bí ó ti fẹ́ràn rẹ̀ tó!”
Nao Ayahudi makiuga atĩrĩ, “Onei ũrĩa aramwendete!”
37 Àwọn kan nínú wọn sì wí pé, “Ọkùnrin yìí, ẹni tí ó la ojú afọ́jú, kò lè ṣe é kí ọkùnrin yìí má kú bí?”
No amwe ao makĩũrania atĩrĩ, “Mũndũ ũyũ ũrahingũrire mũtumumu maitho-rĩ, ndangĩrahotire kũgiria akue?”
38 Nígbà náà ni Jesu tún kérora nínú ara rẹ̀, ó wá sí ibojì, ó sì jẹ́ ihò, a sì gbé òkúta lé ẹnu rẹ̀.
Nake Jesũ, o rĩngĩ acaaĩte mũno, agĩthiĩ mbĩrĩra-inĩ. Mbĩrĩra ĩyo yarĩ ngurunga na yahingĩtwo na ihiga.
39 Jesu wí pé, “Ẹ gbé òkúta náà kúrò!” Marta, arábìnrin ẹni tí ó kú náà wí fún un pé, “Olúwa, ó ti ń rùn nísinsin yìí, nítorí pé ó di ọjọ́ kẹrin tí ó tí kú.”
Nake Jesũ akĩmeera atĩrĩ, “Eheriai ihiga.” No Maritha, mwarĩ wa nyina na mũndũ ũcio wakuĩte, akĩmwĩra atĩrĩ, “Mwathani, rĩu nĩmũnungu nĩ ũndũ nĩaniinĩte mĩthenya ĩna ho.”
40 Jesu wí fún un pé, “Èmi kò ti wí fún ọ pé, bí ìwọ bá gbàgbọ́, ìwọ yóò rí ògo Ọlọ́run?”
Nake Jesũ akĩmwĩra atĩrĩ, “Githĩ ndikwĩrire atĩ wetĩkia nĩũkuona riiri wa Ngai?”
41 Nígbà náà ni wọ́n gbé òkúta náà kúrò (níbi tí a tẹ́ ẹ sí). Jesu sì gbé ojú rẹ̀ sókè, ó sì wí pé, “Baba, mo dúpẹ́ lọ́wọ́ rẹ nítorí tí ìwọ gbọ́ tèmi.
Nĩ ũndũ ũcio makĩeheria ihiga. Jesũ agĩcooka agĩtiira maitho, akiuga atĩrĩ, “Baba, nĩndagũcookeria ngaatho nĩ ũndũ nĩũnjiguaga.
42 Èmi sì ti mọ̀ pé, ìwọ a máa gbọ́ ti èmi nígbà gbogbo, ṣùgbọ́n nítorí ìjọ ènìyàn tí ó dúró yìí ni mo ṣe wí i, kí wọn ba à lè gbàgbọ́ pé ìwọ ni ó rán mi.”
Nĩnjũũĩ atĩ nĩũnjiguaga hĩndĩ ciothe, no ndoiga ũguo nĩ ũndũ wa andũ aya marũgamĩte haha, nĩguo metĩkie atĩ nĩwe wandũmire.”
43 Nígbà tí ó sì wí bẹ́ẹ̀ tan, ó kígbe lóhùn rara pé, “Lasaru, jáde wá.”
Jesũ aarĩkia kuuga ũguo, akĩanĩrĩra na mũgambo mũnene, akiuga atĩrĩ, “Lazaro, uma!”
44 Ẹni tí ó kú náà sì jáde wá, tí a fi aṣọ òkú dì tọwọ́ tẹsẹ̀ a sì fi gèlè dì í lójú. Jesu wí fún wọn pé, “Ẹ tú u, ẹ sì jẹ́ kí ó máa lọ!”
Nake mũndũ ũcio warĩ mũkuũ akiuma, ohetwo na ndaamĩ cia gatani moko na magũrũ, na akarigiicĩrio taama ũthiũ. Jesũ akĩmeera atĩrĩ, “Muohorei mataama macio ma mbĩrĩra, mũreke athiĩ.”
45 Nítorí náà ni ọ̀pọ̀ àwọn Júù tí ó wá sọ́dọ̀ Maria, tí wọ́n rí ohun tí Jesu ṣe, ṣe gbà á gbọ́.
Nĩ ũndũ ũcio Ayahudi aingĩ arĩa mokĩte gũceerera Mariamu, moona ũrĩa Jesũ eekire, makĩmwĩtĩkia.
46 Ṣùgbọ́n àwọn ẹlòmíràn nínú wọn tọ àwọn Farisi lọ, wọ́n sì sọ fún wọn ohun tí Jesu ṣe.
No amwe ao magĩthiĩ kũrĩ Afarisai, makĩmeera ũrĩa Jesũ ekĩte.
47 Nígbà náà ni àwọn olórí àlùfáà àti àwọn Farisi pe ìgbìmọ̀ jọ. Wọ́n sì wí pé, “Kín ni yóò jẹ àṣeyọrí wa? Nítorí ọkùnrin yìí ń ṣe ọ̀pọ̀lọpọ̀ iṣẹ́ àmì.
Hĩndĩ ĩyo athĩnjĩri-Ngai arĩa anene hamwe na Afarisai magĩĩta Kĩama. Makĩũrania atĩrĩ, “Nĩ kĩĩ tũreka? Onei ũrĩa mũndũ ũyũ araringa ciama nyingĩ.
48 Bí àwa bá fi í sílẹ̀ bẹ́ẹ̀, gbogbo ènìyàn ni yóò gbà á gbọ́, àwọn ará Romu yóò sì wá gba ilẹ̀ àti orílẹ̀-èdè wa pẹ̀lú.”
Twareka athiĩ na mbere ũguo, andũ othe nĩmekũmwĩtĩkia, nao Aroma moke meyoere hekarũ iitũ, o na rũrĩrĩ rwitũ.”
49 Ṣùgbọ́n Kaiafa, ọ̀kan nínú wọn, ẹni tí í ṣe olórí àlùfáà ní ọdún náà, ó wí fún wọn pé, “Ẹ̀yin kò mọ ohunkóhun rárá!
Hĩndĩ ĩyo ũmwe wao wetagwo Kaiafa, ũrĩa warĩ mũthĩnjĩri-Ngai mũnene mwaka ũcio, akiuga atĩrĩ, “Inyuĩ mũtirĩ ũndũ mũũĩ o na atĩa!
50 Bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò sì ronú pé, ó ṣàǹfààní fún wa, kí ènìyàn kan kú fún àwọn ènìyàn kí gbogbo orílẹ̀-èdè má ba à ṣègbé.”
Inyuĩ mũtiũĩ atĩ nĩ kaba mũndũ ũmwe akue nĩ ũndũ wa kĩrĩndĩ, handũ ha rũrĩrĩ ruothe rũthire.”
51 Kì í ṣe fún ara rẹ̀ ni ó sọ èyí ṣùgbọ́n bí ó ti jẹ́ olórí àlùfáà ní ọdún náà, ó sọtẹ́lẹ̀ pé, Jesu yóò kú fún orílẹ̀-èdè náà,
Ũndũ ũcio ndaaririe etaarĩte we mwene, no aarathire ũguo arĩ ta mũthĩnjĩri-Ngai mũnene wa mwaka ũcio, atĩ Jesũ nĩagakuĩra rũrĩrĩ rwa Ayahudi,
52 kì sì í ṣe kìkì fún orílẹ̀-èdè náà nìkan, ṣùgbọ́n fún àwọn ọmọ Ọlọ́run tí ó fọ́nká kiri, kí ó le kó wọn papọ̀, kí ó sì sọ wọ́n di ọ̀kan.
na to rũrĩrĩ rũu rwiki, no o na ningĩ akue nĩ ũndũ wa ciana cia Ngai iria ciahurunjũkĩte, nĩgeetha acicookanĩrĩrie atũme ituĩke kĩndũ kĩmwe.
53 Nítorí náà, láti ọjọ́ náà lọ ni wọ́n ti jọ gbìmọ̀ pọ̀ láti pa á.
nĩ ũndũ ũcio kuuma mũthenya ũcio magĩciirĩra kũmũũraga.
54 Nítorí náà Jesu kò rìn ní gbangba láàrín àwọn Júù mọ́; ṣùgbọ́n ó ti ibẹ̀ lọ sí ìgbèríko kan tí ó súnmọ́ aginjù, sí ìlú ńlá kan tí a ń pè ní Efraimu, níbẹ̀ ni ó sì wà pẹ̀lú àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀.
Nĩ ũndũ ũcio Jesũ ndaacookire gũthiĩ akĩĩonithanagia kũrĩ Ayahudi. Handũ ha ũguo, akĩehera agĩthiĩ kũndũ kwarĩ hakuhĩ na werũ, gatũũra geetagwo Efiraimu, agĩikara kuo na arutwo ake.
55 Àjọ ìrékọjá àwọn Júù sì súnmọ́ etílé, ọ̀pọ̀lọpọ̀ láti ìgbèríko sì gòkè lọ sí Jerusalẹmu ṣáájú ìrékọjá, láti ya ara wọn sí mímọ́.
Na rĩrĩa Bathaka ya Ayahudi yakuhĩrĩirie, andũ aingĩ makĩambata kuuma matũũra-inĩ, magĩthiĩ Jerusalemu nĩ ũndũ wa igongona rĩa gwĩtheria Bathaka ĩtanakinya.
56 Nígbà náà ni wọ́n ń wá Jesu, wọ́n sì ń bá ara wọn sọ̀, bí wọ́n ti dúró ní tẹmpili, wí pé, “Kín ni ẹyin ti rò ó sí pé kì yóò wá sí àjọ?”
Andũ acio magĩikara magĩcaragia Jesũ, na rĩrĩa maarũngiĩ nja ya hekarũ, makĩũrania atĩrĩ, “Mũgwĩciiria atĩa? Kaĩ hihi ategũũka Gĩathĩ-inĩ?”
57 Ǹjẹ́ àwọn olórí àlùfáà àti àwọn Farisi ti pàṣẹ pé bí ẹnìkan bá mọ ibi tí ó gbé wà, kí ó fi í hàn, kí wọn ba à lè mú un.
No athĩnjĩri-Ngai arĩa anene na Afarisai nĩmarutĩte watho atĩ mũndũ o wothe ũngĩamenyire harĩa Jesũ aarĩ, amarehere ũhoro nĩgeetha mamũnyiite.